< Psalms 102 >
1 Àdúrà olùpọ́njú tí àárẹ̀ mú, tí ó sí ọkàn rẹ̀ payá níwájú Olúwa. Gbọ́ àdúrà mi, Olúwa, jẹ́ kí igbe ẹ̀bẹ̀ mi kí ó wá sí ọ̀dọ̀ rẹ.
Wee Jehova, igua ihooya rĩakwa; reke gũkaya gwakwa ngĩhooya ũteithio gũgũkinyĩre.
2 Má ṣe pa ojú rẹ mọ́ kúrò lọ́dọ̀ mi ní ọjọ́ tí èmi wà nínú ìpọ́njú. Dẹ etí rẹ sí mi; nígbà tí mo bá pè, dá mi lóhùn kíákíá.
Tiga kũũhitha ũthiũ waku rĩrĩa ndĩ mĩnyamaro-inĩ. Inamĩrĩria gũtũ gwaku ũnjigue; ndagũkaĩra, njĩtĩka o narua.
3 Nítorí tí ọjọ́ mi run bí èéfín; egungun mi sì jóná bí ààrò.
Nĩgũkorwo matukũ makwa marathira o ta ũrĩa ndogo ĩthiraga; namo mahĩndĩ makwa maraakana o ta gĩcinga.
4 Àyà mi lù, ó sì rọ bí i koríko; mo gbàgbé láti jẹ oúnjẹ mi.
Ngoro yakwa ĩringĩkĩte na ĩkahooha o ta nyeki; ndiganĩirwo o na nĩ kũrĩa irio.
5 Nítorí ohùn ìkérora mi, egungun mi lẹ̀ mọ́ ẹran-ara mi.
Tondũ wa ũrĩa ndĩracaaya nyanĩrĩire, hĩnjĩte ngatigara o gĩkonde na mahĩndĩ.
6 Èmi dàbí ẹyẹ igún ní ijù: èmi dàbí òwìwí ibi ahoro.
Haana ta ndundu ya werũ-inĩ, ngahaana ta ndundu ĩrĩa ĩikaraga kũrĩa kwanangĩku.
7 Èmi dìde; èmi dàbí ẹyẹ lórí ilé.
Ndaaraga itarĩ toro; haanĩte ta nyoni ĩrĩ o iiki nyũmba igũrũ.
8 Ní ọjọ́ gbogbo, àwọn ọ̀tá ológoṣẹ́ mi ń gàn mí; àwọn tí ń ṣe ìkanra sí mi ń fi orúkọ mi bú.
Mũthenya wothe thũ ciakwa itindaga igĩĩthirĩkia; acio maanyũrũragia mahũthagĩra rĩĩtwa rĩakwa taarĩ kĩrumi.
9 Èmi jẹ eérú gẹ́gẹ́ bí oúnjẹ mi, èmi sì da ohun mímu mi pọ̀ pẹ̀lú omijé.
Nĩgũkorwo ndĩĩaga mũhu taarĩ irio ciakwa, na kĩrĩa nyuuaga ngagĩtukania na maithori,
10 Nítorí ìbínú ríru rẹ, nítorí ìwọ ti gbé mi sókè, ìwọ sì gbé mi ṣánlẹ̀.
tondũ wa mangʼũrĩ maku manene, ũnjoete na igũrũ ũkanjikia mwena-inĩ.
11 Ọjọ́ mi dàbí òjìji àṣálẹ́ èmi sì rọ bí koríko.
Matukũ makwa mahaana o ta kĩĩruru kĩa hwaĩ-inĩ; hoohaga ta nyeki.
12 Ṣùgbọ́n ìwọ, Olúwa, ni yóò dúró láéláé; ìrántí rẹ láti ìran dé ìran.
No rĩrĩ, Wee Jehova ũgũtũũra ũikarĩire gĩtĩ kĩa ũnene nginya tene na tene; ngumo yaku ĩgũtũũra njiarwa na njiarwa.
13 Ìwọ ó dìde ìwọ ó sì ṣàánú fún Sioni, nítorí ìgbà àti ṣe ojúrere sí i; àkókò náà ti dé.
Wee nĩũkwarahũka ũiguĩre itũũra rĩa Zayuni tha, nĩgũkorwo ihinda rĩa kũrĩĩka wega nĩ ikinyu; ihinda rĩrĩa rĩathĩrĩre nĩ ikinyu.
14 Nítorí tí àwọn òkúta jẹ́ inú dídùn sí àwọn ìránṣẹ́ rẹ; wọ́n sì káàánú erùpẹ̀ rẹ.
Nĩgũkorwo mahiga makuo nĩmakenagĩrwo nĩ ndungata ciaku; o na rũkũngũ rwakuo nĩrũtũmaga iringwo nĩ tha.
15 Àwọn kèfèrí yóò bẹ̀rù orúkọ Olúwa, gbogbo ọba ayé yóò máa bẹ̀rù ògo rẹ.
Ndũrĩrĩ nĩigeetigĩra rĩĩtwa rĩa Jehova, athamaki othe a thĩ mekĩrĩre riiri waku.
16 Torí tí Olúwa yóò gbé Sioni ró, yóò farahàn nínú ògo rẹ̀.
Nĩgũkorwo Jehova nĩagaaka itũũra rĩa Zayuni rĩngĩ, na eyumĩrie arĩ na riiri wake.
17 Yóò dáhùn àdúrà àwọn aláìní; kì yóò sì gan ẹ̀bẹ̀ wọn.
Nĩakaigua mahooya ma andũ arĩa aagi; ndakanyarara mahooya mao.
18 Jẹ́ kí a kọ èyí fún ìran tí ń bọ̀, àwọn ènìyàn tí a kò tí ì dá yóò yin Olúwa:
Ũhoro ũyũ nĩwandĩkwo nĩ ũndũ wa rũciaro rũrĩa rũgooka, nĩguo andũ arĩa mataciarĩtwo makaagooca Jehova:
19 “Olúwa wo ilẹ̀ láti òkè mímọ́ rẹ̀ wá láti ọ̀run wá ni ó bojú wo ayé,
“Jehova nĩacũthĩrĩirie thĩ arĩ harĩa hake haamũre kũu igũrũ; arĩ kũu igũrũ Jehova nĩkũrora aarorire thĩ,
20 láti gbọ́ ìrora ará túbú, láti tú àwọn tí a yàn sí ikú sílẹ̀.”
nĩguo aigue gũcaaya kwa arĩa moheetwo, na ohorithie arĩa maatuĩrĩirwo gũkua.”
21 Kí a lè sọ orúkọ Olúwa ní Sioni àti ìyìn rẹ̀ ní Jerusalẹmu.
Nĩ ũndũ ũcio rĩĩtwa rĩa Jehova nĩrĩkoimbũrwo kũu Zayuni, na nĩakagoocwo kũu Jerusalemu
22 Ní ìgbà tí a kó àwọn ènìyàn àti ìjọba pọ̀ láti máa sìn Olúwa.
rĩrĩa andũ a ndũrĩrĩ na mothamaki makoongana, mathathaiye Jehova.
23 Ní ipa ọ̀nà mi, ó rẹ agbára mi sílẹ̀, ó gé ọjọ́ mi kúrú.
Hĩndĩ ya mũtũũrĩre wakwa nĩanyiihirie hinya wakwa; nĩakuhĩhirie matukũ makwa.
24 Èmi sì wí pé: “Ọlọ́run mi, má ṣe mú mi kúrò ní agbede-méjì ọjọ́ mi; ọdún rẹ̀ ń lọ láti ìran dé ìran.
Nĩ ũndũ ũcio ngĩkiuga atĩrĩ: “Wee Ngai wakwa, ndũkanjũrage o rĩrĩa ndaiganĩria matukũ makwa; wee-rĩ, mĩaka yaku ĩthiiaga o na mbere nginya njiarwa na njiarwa.
25 Ní ìbẹ̀rẹ̀ ní ìwọ fi ìpìlẹ̀ ayé sọlẹ̀, ọ̀run sì jẹ́ iṣẹ́ ọwọ́ rẹ.
O kĩambĩrĩria-inĩ, nĩwaarire mĩthingi ya thĩ, o narĩo igũrũ nĩ wĩra wa moko maku.
26 Wọn yóò ṣègbé, wọn yóò parun, ṣùgbọ́n ìwọ yóò wà; gbogbo wọn ni yóò gbó bí aṣọ. Bí ẹ̀wù ni ìwọ yóò pààrọ̀ wọn wọn yóò sì di àpatì.
Icio nĩgũthira igaathira, no wee nĩgũtũũra ũgaatũũra; igaakũra o ta nguo, ithire. Ũgaacigarũrĩra ta nguo, icooke iteeo.
27 Ṣùgbọ́n ìwọ wà digbí síbẹ̀, ọdún rẹ kò sì ní òpin.
No Wee ndũgarũrũkaga, nayo mĩaka yaku ndĩrĩ mũthia.
28 Àwọn ọmọ ìránṣẹ́ rẹ̀ yóò dúró ní iwájú rẹ pẹ́; a ó sì fi ẹsẹ̀ irú-ọmọ wọn sọlẹ̀ ní iwájú rẹ.”
Ciana cia ndungata ciaku igaatũũra na thayũ mbere yaku; nacio njiaro ciacio cigaikara irũmĩte irĩ mbere yaku.”