< Psalms 102 >

1 Àdúrà olùpọ́njú tí àárẹ̀ mú, tí ó sí ọkàn rẹ̀ payá níwájú Olúwa. Gbọ́ àdúrà mi, Olúwa, jẹ́ kí igbe ẹ̀bẹ̀ mi kí ó wá sí ọ̀dọ̀ rẹ.
Mangdaeng a rhae vaengah BOEIPA mikhmuh ah a kohuetnah a hawk tih a thangthuinah BOEIPA aw ka thangthuinah he ya lamtah ka pang ol loh nang taengla ham pha saeh.
2 Má ṣe pa ojú rẹ mọ́ kúrò lọ́dọ̀ mi ní ọjọ́ tí èmi wà nínú ìpọ́njú. Dẹ etí rẹ sí mi; nígbà tí mo bá pè, dá mi lóhùn kíákíá.
Kai kah puencak tue vaengah na maelhmai te kai taeng lamkah thuh boeh. Kang khue tue vaengah kai taengla na hna han kaeng lamtah kai he koe n'doo lah.
3 Nítorí tí ọjọ́ mi run bí èéfín; egungun mi sì jóná bí ààrò.
Ka khohnin he hmaikhu bangla hmata tih ka rhuhrhong khaw hmaingen bangla tlum.
4 Àyà mi lù, ó sì rọ bí i koríko; mo gbàgbé láti jẹ oúnjẹ mi.
Ka lungbuei he baelhing bangla a haih tih a rhae sut dongah ka buh caak pataeng ka hnilh coeng.
5 Nítorí ohùn ìkérora mi, egungun mi lẹ̀ mọ́ ẹran-ara mi.
Ka hueinah ol dongah ka pumsa tah ka rhuh dongla kap coeng.
6 Èmi dàbí ẹyẹ igún ní ijù: èmi dàbí òwìwí ibi ahoro.
Khosoek kah khosoek saelbu bangla ka lutlat sut tih, imrhong thathawt bangla ka om.
7 Èmi dìde; èmi dàbí ẹyẹ lórí ilé.
Ka hak ah khaw imphu kah aka pangoe vaa bangla ka om.
8 Ní ọjọ́ gbogbo, àwọn ọ̀tá ológoṣẹ́ mi ń gàn mí; àwọn tí ń ṣe ìkanra sí mi ń fi orúkọ mi bú.
Ka thunkha loh hnin takuem kai m'veet uh tih kai aka yan rhoek loh kai ming neh a toemngam uh.
9 Èmi jẹ eérú gẹ́gẹ́ bí oúnjẹ mi, èmi sì da ohun mímu mi pọ̀ pẹ̀lú omijé.
Hmaiphu te buh la ka caak tih ka tuiok khaw rhahnah neh ka thoek.
10 Nítorí ìbínú ríru rẹ, nítorí ìwọ ti gbé mi sókè, ìwọ sì gbé mi ṣánlẹ̀.
Kai nan ludoeng tangtae khaw na kosi, na thinhul neh kai nan voeih.
11 Ọjọ́ mi dàbí òjìji àṣálẹ́ èmi sì rọ bí koríko.
Ka khohnin he mueihlip bangla puh tih baelhing bangla ka rhae sut.
12 Ṣùgbọ́n ìwọ, Olúwa, ni yóò dúró láéláé; ìrántí rẹ láti ìran dé ìran.
Tedae BOEIPA namah tah kumhal ah na ngol coeng tih namah poekkoepnah tah cadilcahma phoeikah cadilcahma duela om.
13 Ìwọ ó dìde ìwọ ó sì ṣàánú fún Sioni, nítorí ìgbà àti ṣe ojúrere sí i; àkókò náà ti dé.
Na thoo vetih a tue bangla Zion na haidam bitni. Anih rhen hamla khoning a pha coeng dongah.
14 Nítorí tí àwọn òkúta jẹ́ inú dídùn sí àwọn ìránṣẹ́ rẹ; wọ́n sì káàánú erùpẹ̀ rẹ.
Na sal rhoek loh Zion kah lungto te a ngaingaih uh tih a laipi te khaw a rhen uh.
15 Àwọn kèfèrí yóò bẹ̀rù orúkọ Olúwa, gbogbo ọba ayé yóò máa bẹ̀rù ògo rẹ.
Te dongah BOEIPA namah ming te namtom rhoek loh, namah thangpomnah te diklai manghai boeih loh a rhih uh ni.
16 Torí tí Olúwa yóò gbé Sioni ró, yóò farahàn nínú ògo rẹ̀.
Zion te BOEIPA loh a thoh vetih a thangpomnah neh phoe ni.
17 Yóò dáhùn àdúrà àwọn aláìní; kì yóò sì gan ẹ̀bẹ̀ wọn.
Dueidah thahnoeng thangthuinah taengla mael vetih amih kah thangthuinah te sit mahpawh.
18 Jẹ́ kí a kọ èyí fún ìran tí ń bọ̀, àwọn ènìyàn tí a kò tí ì dá yóò yin Olúwa:
Hmailong kah cadilcahma ham khaw hekah he daek saeh lamtah a suen pilnam loh BOEIPA thangthen saeh.
19 “Olúwa wo ilẹ̀ láti òkè mímọ́ rẹ̀ wá láti ọ̀run wá ni ó bojú wo ayé,
A sang hmuencim lamkah a dan tih diklai te BOEIPA loh vaan lamkah a paelki.
20 láti gbọ́ ìrora ará túbú, láti tú àwọn tí a yàn sí ikú sílẹ̀.”
Thongtl a kah a kiinah hnatun ham, dueknah khuikah hlang rhoek te hlah ham,
21 Kí a lè sọ orúkọ Olúwa ní Sioni àti ìyìn rẹ̀ ní Jerusalẹmu.
BOEIPA ming te Zion ah, amah koehnah te khaw Jerusalem ah doek ham om ni.
22 Ní ìgbà tí a kó àwọn ènìyàn àti ìjọba pọ̀ láti máa sìn Olúwa.
BOEIPA taengah thothueng ham pilnam rhoek neh ram rhoek tah tun tingtun uh ni.
23 Ní ipa ọ̀nà mi, ó rẹ agbára mi sílẹ̀, ó gé ọjọ́ mi kúrú.
Ka thadueng he longpuei ah a khah tih, ka khohnin khaw a rhaem.
24 Èmi sì wí pé: “Ọlọ́run mi, má ṣe mú mi kúrò ní agbede-méjì ọjọ́ mi; ọdún rẹ̀ ń lọ láti ìran dé ìran.
Te dongah, “Ka Pathen aw, kai kah ka khohnin he a boengli ah lo boel mai. Namah kah kum tah cadilcahma phoeikah cadilcahma due khaw a pha kanoek.
25 Ní ìbẹ̀rẹ̀ ní ìwọ fi ìpìlẹ̀ ayé sọlẹ̀, ọ̀run sì jẹ́ iṣẹ́ ọwọ́ rẹ.
A cuek vaengah diklai na suen tih vaan ke khaw namah kutngo ni.
26 Wọn yóò ṣègbé, wọn yóò parun, ṣùgbọ́n ìwọ yóò wà; gbogbo wọn ni yóò gbó bí aṣọ. Bí ẹ̀wù ni ìwọ yóò pààrọ̀ wọn wọn yóò sì di àpatì.
Amih te milh uh cakhaw namah tah na nguel yoeyah. Te dongah amih te himbai bangla boeih hnawn uh vetih pueinak bangla na tho vaengah thovael uh van ni.
27 Ṣùgbọ́n ìwọ wà digbí síbẹ̀, ọdún rẹ kò sì ní òpin.
Tedae namah tah amah la na om tih na kum khaw bawt pawh.
28 Àwọn ọmọ ìránṣẹ́ rẹ̀ yóò dúró ní iwájú rẹ pẹ́; a ó sì fi ẹsẹ̀ irú-ọmọ wọn sọlẹ̀ ní iwájú rẹ.”
Na sal rhoek kah a ca rhoek loh kho a sak uh vetih a tiingan loh namah mikhmuh ah pai ni,” ka ti.

< Psalms 102 >