< Psalms 10 >

1 Èéha ti ṣe, Olúwa, tí ìwọ fi dúró ní òkè réré? Èéha ti ṣe, tí ìwọ fi ara rẹ pamọ́ ní ìgbà ìpọ́njú?
Némishqa, i Perwerdigar, yiraqta turisen? Némishqa azabliq künlerde özüngni yoshurisen?
2 Nínú àrékérekè ni ènìyàn búburú tí mu aláìlera, ẹni ti ó mú nínú ìdẹ̀kùn àrékérekè rẹ̀.
Rezil ademler tekebburluqi bilen ajiz möminlerni tap basturup qoghlap yüridu; Ular özliri tapqan hiyliler bilen ilinip, bablinidu.
3 Nítorí ènìyàn búburú ń ṣògo ìfẹ́ inú ọkàn rẹ̀; Ó bùkún olójúkòkòrò, ó sì ń kẹ́gàn Olúwa.
Chünki reziller öz arzu-hewesliri bilen maxtinidu; Ach közler üchün bext tileydu; Perwerdigarni bolsa közige ilmaydu.
4 Ènìyàn búburú kò lè rí nínú ìgbéraga rẹ̀; kò sí ààyè fún Ọlọ́run nínú gbogbo èrò rẹ̀.
Ular chirayidin hakawurluq yaghdurup, Xudani izdimeydu; Ular barliq xiyallirida: «Héchbir Xuda yoqtur!» deydu.
5 Ọ̀nà rẹ̀ ń gún régé nígbà gbogbo; òun ń gbéraga, òfin rẹ̀ sì jìnnà sí i; òun kẹ́gàn àwọn ọ̀tá rẹ̀.
Ularning yolliri hemishe rawan bolidu; Séning hökümliring ularning neziridin yiraq we üstün turidu; Ularning reqibliri bolsa, ulargha qarap «tüfi!» dep mazaq qilidu.
6 O wí fún ara rẹ̀, “Kò sí ohun tí ó lè mì mí. Inú mi yóò máa dùn nígbà gbogbo, èmi kò sì ní ní wàhálà.”
[Rezil adem] könglide: «Men héch tewrenmey turiwérimen! Dewrdin-dewrge héch musheqqetke uchrimaymen» — deydu.
7 Ẹnu rẹ̀ kún fún ègún àti irọ́ àti ìtànjẹ; wàhálà àti ohun búburú wà lábẹ́ ahọ́n rẹ̀.
Uning aghzi qarghash, aldamchiliq hem zulumgha tolghan; Tili astida eskilik we qebihlik yatidu.
8 Ó lúgọ ní bùba nítòsí ìletò. Ò gọ níbi ìkọ̀kọ̀ láti pa aláìṣẹ̀. Ojú rẹ̀ ń ṣọ́ àwọn tálákà ní ìkọ̀kọ̀.
U mehellilerde yoshurunche marap olturidu; U pinhan jaylarda gunahsizlarni öltürüwétidu; Közliri yoqsullarni közleydu;
9 Ó ba ní ní bùba bí i kìnnìún nínú pàǹtí; Ó ba ní bùba láti mú àwọn aláìní ìrànwọ́; ó mú àwọn aláìlólùrànlọ́wọ́, ó sì wọ́ wọn lọ sínú àwọ̀n rẹ̀.
U chatqalliqida yatqan shirdek yoshurunche paylap yatidu; U möminlerni tutuwélish üchün yoshurunche marap yatidu; Möminlerni tutuwélip, ularni öz torigha chüshüridu.
10 Ó ba, ó rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀; kí tálákà ba à le bọ́ sí ọwọ́ agbára rẹ̀.
[Yoqsullar] ézilidu, pükülidu; Derdmenler uning yawuzluqliri bilen yiqilidu.
11 Ó wí fún ara rẹ̀, “Ọlọ́run ti gbàgbé; Ó pa ojú rẹ̀ mọ́, òun kì yóò rí i láéláé.”
U könglide: «Tengri buni untup qaldi, U yüzini yépiwélip, qarimaydu; Buni hergiz körmeydu» — deydu.
12 Dìde, Olúwa! Gbé ọwọ́ rẹ sókè, Ọlọ́run. Má ṣe gbàgbé àwọn olùpọ́njú.
Ornungdin turghin, i Perwerdigar; I Tengrim, qolungni kötürgin; Ézilgen möminlerni untuma!
13 Èéṣe tí ènìyàn búburú ṣe ń kẹ́gàn Ọlọ́run? Èéṣe tí o fi wí nínú ọkàn ara rẹ̀, “Kò ní pè mí láti ṣe ìṣirò”?
Rezil adem némishqa [Sen] Xudani közige ilmaydu? U könglide: «[Xuda] buni sürüshtürmeydu!» — deydu.
14 Ṣùgbọ́n ìwọ, Ọlọ́run, ni ó rí wàhálà àti ìrora; Ìwọ rò láti fi sí ọwọ́ rẹ. Tálákà fi ara rẹ̀ jì fún ọ; Ìwọ ni olùrànlọ́wọ́ àwọn aláìní baba.
Sen buni körgensen; Sen Öz qolung bilen yamanliq hem zulumni özlirige qayturush üchün, Özüng bularni közlep yürisen; Derdmenler özlirini Sanga amanet qilidu; Chünki Sen yétim-yésirlerge yar-yölek bolup kelgensen;
15 Ṣẹ́ apá àwọn ènìyàn búburú àti ènìyàn ibi; pè é láti wá ṣírò fún ìwà ìkà rẹ̀ tí a kò le è rí.
Rezil, yaman ademning bilikini sunduruwetkeysen; Uning rezillikini birmubir sürüshtürüp, üzül-késil yoqatqaysen.
16 Olúwa ń jẹ ọba láé àti láéláé; àwọn orílẹ̀-èdè yóò ṣègbé lórí ilé rẹ.
Perwerdigar ebedil’ebedgiche padishahdur; [Imansiz] eller bolsa [Perwerdigarning] zéminidin yoqilar.
17 Ìwọ́ gbọ́, Olúwa, ìfẹ́ àwọn tí a ni lára; Ìwọ gbà wọ́n níyànjú, ó sì gbọ́ igbe wọn,
Perwerdigar, Sen ajiz möminlerning armanlirini anglaysen; Ularning dilini toq qilisen;
18 láti ṣe ìdájọ́ àwọn aláìní baba àti àwọn ti a ni lára, kí ọkùnrin, tí ó wà ní ayé, kí ó má ṣe dẹ́rùbà ni mọ́.
Yétim-yésirlar we ézilgüchiler üchün adaletni yaqlap, Yer yüzidiki insanlarning [ajiz-möminlerge] qaytidin wehime salghuchi bolmasliqi üchün, Quliqingni ding tutisen.

< Psalms 10 >