< Psalms 10 >

1 Èéha ti ṣe, Olúwa, tí ìwọ fi dúró ní òkè réré? Èéha ti ṣe, tí ìwọ fi ara rẹ pamọ́ ní ìgbà ìpọ́njú?
De ce stai departe, DOAMNE? De ce te ascunzi în timpuri de necaz?
2 Nínú àrékérekè ni ènìyàn búburú tí mu aláìlera, ẹni ti ó mú nínú ìdẹ̀kùn àrékérekè rẹ̀.
Cel stricat, în mândria lui, persecută pe sărac, să fie ei prinși în planurile pe care și le-au închipuit.
3 Nítorí ènìyàn búburú ń ṣògo ìfẹ́ inú ọkàn rẹ̀; Ó bùkún olójúkòkòrò, ó sì ń kẹ́gàn Olúwa.
Fiindcă cel stricat se fălește cu dorința inimii lui și binecuvântează pe cel lacom, pe care DOMNUL îl detestă.
4 Ènìyàn búburú kò lè rí nínú ìgbéraga rẹ̀; kò sí ààyè fún Ọlọ́run nínú gbogbo èrò rẹ̀.
Cel stricat, prin mândria înfățișării sale, refuză să caute pe Dumnezeu; Dumnezeu nu este în toate gândurile sale.
5 Ọ̀nà rẹ̀ ń gún régé nígbà gbogbo; òun ń gbéraga, òfin rẹ̀ sì jìnnà sí i; òun kẹ́gàn àwọn ọ̀tá rẹ̀.
Căile lui sunt întotdeauna apăsătoare; judecățile tale sunt cu mult deasupra și în afara vederii lui; cât despre toți dușmanii lui, el pufnește către ei.
6 O wí fún ara rẹ̀, “Kò sí ohun tí ó lè mì mí. Inú mi yóò máa dùn nígbà gbogbo, èmi kò sì ní ní wàhálà.”
A spus în inima lui: Nu mă voi clătina, pentru că niciodată nu voi fi în restriște.
7 Ẹnu rẹ̀ kún fún ègún àti irọ́ àti ìtànjẹ; wàhálà àti ohun búburú wà lábẹ́ ahọ́n rẹ̀.
Gura lui este plină de blestem și înșelăciune și fraudă; sub limba lui este ticăloșie și deșertăciune.
8 Ó lúgọ ní bùba nítòsí ìletò. Ò gọ níbi ìkọ̀kọ̀ láti pa aláìṣẹ̀. Ojú rẹ̀ ń ṣọ́ àwọn tálákà ní ìkọ̀kọ̀.
El șade în locurile de pândă ale satelor, în locurile tainice îl ucide pe cel nevinovat; ochii săi sunt ațintiți pe ascuns împotriva celui sărac.
9 Ó ba ní ní bùba bí i kìnnìún nínú pàǹtí; Ó ba ní bùba láti mú àwọn aláìní ìrànwọ́; ó mú àwọn aláìlólùrànlọ́wọ́, ó sì wọ́ wọn lọ sínú àwọ̀n rẹ̀.
Stă la pândă în taină, ca un leu în vizuina lui; stă la pândă să prindă pe sărac; îl prinde pe sărac după ce îl conduce în plasa lui.
10 Ó ba, ó rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀; kí tálákà ba à le bọ́ sí ọwọ́ agbára rẹ̀.
Se tupilează și se umilește, ca cel sărac să cadă prin puternicii lui.
11 Ó wí fún ara rẹ̀, “Ọlọ́run ti gbàgbé; Ó pa ojú rẹ̀ mọ́, òun kì yóò rí i láéláé.”
El a spus în inima lui: Dumnezeu a uitat, își ascunde fața, niciodată nu va vedea aceasta.
12 Dìde, Olúwa! Gbé ọwọ́ rẹ sókè, Ọlọ́run. Má ṣe gbàgbé àwọn olùpọ́njú.
Ridică-te DOAMNE; ridică-ți mâna Dumnezeule, nu uita pe cei umili.
13 Èéṣe tí ènìyàn búburú ṣe ń kẹ́gàn Ọlọ́run? Èéṣe tí o fi wí nínú ọkàn ara rẹ̀, “Kò ní pè mí láti ṣe ìṣirò”?
Pentru ce disprețuiește cel stricat pe Dumnezeu? El a spus în inima lui: Nu îmi vei cere socoteală.
14 Ṣùgbọ́n ìwọ, Ọlọ́run, ni ó rí wàhálà àti ìrora; Ìwọ rò láti fi sí ọwọ́ rẹ. Tálákà fi ara rẹ̀ jì fún ọ; Ìwọ ni olùrànlọ́wọ́ àwọn aláìní baba.
Ai văzut aceasta, fiindcă privești ticăloșie și ciudă pentru a răsplăti cu mâna ta; cel sărac ți se încredințează, tu ești ajutorul celui fără tată.
15 Ṣẹ́ apá àwọn ènìyàn búburú àti ènìyàn ibi; pè é láti wá ṣírò fún ìwà ìkà rẹ̀ tí a kò le è rí.
Frânge brațul celui stricat și pe cel rău, caută stricăciunea lui până nu o găsești deloc.
16 Olúwa ń jẹ ọba láé àti láéláé; àwọn orílẹ̀-èdè yóò ṣègbé lórí ilé rẹ.
DOMNUL este Împărat pentru totdeauna și întotdeauna; păgânii au pierit din țara lui.
17 Ìwọ́ gbọ́, Olúwa, ìfẹ́ àwọn tí a ni lára; Ìwọ gbà wọ́n níyànjú, ó sì gbọ́ igbe wọn,
DOAMNE, tu ai auzit dorința celor umili, vei pregăti inima lor, vei face urechea ta să audă,
18 láti ṣe ìdájọ́ àwọn aláìní baba àti àwọn ti a ni lára, kí ọkùnrin, tí ó wà ní ayé, kí ó má ṣe dẹ́rùbà ni mọ́.
Pentru a judeca pe cel fără tată și pe cel oprimat, ca omul de pe pământ să nu mai oprime.

< Psalms 10 >