< Psalms 10 >

1 Èéha ti ṣe, Olúwa, tí ìwọ fi dúró ní òkè réré? Èéha ti ṣe, tí ìwọ fi ara rẹ pamọ́ ní ìgbà ìpọ́njú?
Kāpēc Tu, Kungs, stāvi no tālienes, paslēpies bēdu laikā?
2 Nínú àrékérekè ni ènìyàn búburú tí mu aláìlera, ẹni ti ó mú nínú ìdẹ̀kùn àrékérekè rẹ̀.
No bezdievīgā lepnības bailes nāk nabagam; lai tie top gūstīti savās blēņās, ko tie izdomājuši.
3 Nítorí ènìyàn búburú ń ṣògo ìfẹ́ inú ọkàn rẹ̀; Ó bùkún olójúkòkòrò, ó sì ń kẹ́gàn Olúwa.
Jo bezdievīgais lielās ar savas dvēseles kārību, plēsējs lād, viņš zaimo To Kungu.
4 Ènìyàn búburú kò lè rí nínú ìgbéraga rẹ̀; kò sí ààyè fún Ọlọ́run nínú gbogbo èrò rẹ̀.
Bezdievīgais savā lielā lepnībā nebēdā par nevienu; visas viņa domas ir: Dieva neesam.
5 Ọ̀nà rẹ̀ ń gún régé nígbà gbogbo; òun ń gbéraga, òfin rẹ̀ sì jìnnà sí i; òun kẹ́gàn àwọn ọ̀tá rẹ̀.
Viņa ceļi allažiņ izdodas, Tava sodība ir tālu no viņa; šņākdams viņš turas pret visiem saviem pretiniekiem.
6 O wí fún ara rẹ̀, “Kò sí ohun tí ó lè mì mí. Inú mi yóò máa dùn nígbà gbogbo, èmi kò sì ní ní wàhálà.”
Viņš saka savā sirdī: es netapšu kustināts, jo ļaunumā es nenākšu līdz radu radiem.
7 Ẹnu rẹ̀ kún fún ègún àti irọ́ àti ìtànjẹ; wàhálà àti ohun búburú wà lábẹ́ ahọ́n rẹ̀.
Viņa mute pilna lāstu un viltus un varmācības, apakš viņa mēles ir grūtums un bēdas.
8 Ó lúgọ ní bùba nítòsí ìletò. Ò gọ níbi ìkọ̀kọ̀ láti pa aláìṣẹ̀. Ojú rẹ̀ ń ṣọ́ àwọn tálákà ní ìkọ̀kọ̀.
Viņš, sēž paslēpies aiz sētām, viņš nokauj nenoziedzīgo slepenās vietās, viņa acis glūn uz nabagu.
9 Ó ba ní ní bùba bí i kìnnìún nínú pàǹtí; Ó ba ní bùba láti mú àwọn aláìní ìrànwọ́; ó mú àwọn aláìlólùrànlọ́wọ́, ó sì wọ́ wọn lọ sínú àwọ̀n rẹ̀.
Viņš glūn slepenībā kā lauva savā alā, viņš glūn sakampt bēdīgo, viņš sakampj bēdīgo, to ievilkdams savā tīklā.
10 Ó ba, ó rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀; kí tálákà ba à le bọ́ sí ọwọ́ agbára rẹ̀.
Viņš tup un nometās un uzkrīt ar varu nelaimīgiem.
11 Ó wí fún ara rẹ̀, “Ọlọ́run ti gbàgbé; Ó pa ojú rẹ̀ mọ́, òun kì yóò rí i láéláé.”
Viņš saka savā sirdī: Dievs ir aizmirsis, Viņš Savu vaigu apslēpis, Viņš neredz ne mūžam.
12 Dìde, Olúwa! Gbé ọwọ́ rẹ sókè, Ọlọ́run. Má ṣe gbàgbé àwọn olùpọ́njú.
Celies, ak Dievs Kungs, pacel Savu roku, neaizmirsti bēdīgos.
13 Èéṣe tí ènìyàn búburú ṣe ń kẹ́gàn Ọlọ́run? Èéṣe tí o fi wí nínú ọkàn ara rẹ̀, “Kò ní pè mí láti ṣe ìṣirò”?
Kādēļ bezdievīgais Dievu zaimos un sacīs savā sirdī: Tu nemeklēsi?
14 Ṣùgbọ́n ìwọ, Ọlọ́run, ni ó rí wàhálà àti ìrora; Ìwọ rò láti fi sí ọwọ́ rẹ. Tálákà fi ara rẹ̀ jì fún ọ; Ìwọ ni olùrànlọ́wọ́ àwọn aláìní baba.
Tu gan redzi, jo Tu uzlūko mokas un sirdēstus, likdams to Savās rokās; nelaimīgais uz Tevi paļaujas, Tu esi bāriņa palīgs.
15 Ṣẹ́ apá àwọn ènìyàn búburú àti ènìyàn ibi; pè é láti wá ṣírò fún ìwà ìkà rẹ̀ tí a kò le è rí.
Salauz bezdievīgā elkoni un meklē ļaunā bezdievību, ka to vairs neatrod.
16 Olúwa ń jẹ ọba láé àti láéláé; àwọn orílẹ̀-èdè yóò ṣègbé lórí ilé rẹ.
Tas Kungs ir ķēniņš mūžīgi mūžam; pagāni ir bojā gājuši no Viņa zemes,
17 Ìwọ́ gbọ́, Olúwa, ìfẹ́ àwọn tí a ni lára; Ìwọ gbà wọ́n níyànjú, ó sì gbọ́ igbe wọn,
Nabagu ilgošanos Tu klausi, ak Kungs! Tu viņiem sirdi stiprini, Tava auss to liek vērā,
18 láti ṣe ìdájọ́ àwọn aláìní baba àti àwọn ti a ni lára, kí ọkùnrin, tí ó wà ní ayé, kí ó má ṣe dẹ́rùbà ni mọ́.
Tiesu nesdams bāriņam un apspiestam, lai cilvēks, kas no zemes, vairs nedara varas darbus.

< Psalms 10 >