< Proverbs 1 >

1 Àwọn òwe ti Solomoni, ọmọ Dafidi, ọba Israẹli.
Israil padixaⱨi Dawutning oƣli Sulaymanning pǝnd-nǝsiⱨǝtliri: —
2 Láti le ní ọgbọ́n àti ẹ̀kọ́, láti ní òye àwọn ọ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀.
Bu pǝnd-nǝsiⱨǝtlǝr sanga ǝⱪil-parasǝt, ǝdǝp-ǝhlaⱪni ɵgitip, seni ibrǝtlik sɵzlǝrni qüxinidiƣan ⱪilidu;
3 Láti gba ẹ̀kọ́ ọgbọ́n, òdodo, àti ìdájọ́, àti àìṣègbè;
sanga danaliⱪ, ⱨǝⱪⱪaniyliⱪ, pǝm-parasǝt wǝ durusluⱪning yolyoruⱪ-tǝrbiyisini ⱪobul ⱪilduridu.
4 láti fi òye fún onírẹ̀lẹ̀, ìmọ̀ àti ìṣọ́ra fún àwọn èwe.
Bu [pǝnd-nǝsiⱨǝtlǝr] nadanlarni zerǝk ⱪilip, yaxlarni bilimlik wǝ sǝzgür ⱪilidu;
5 Jẹ́ kí ọlọ́gbọ́n tẹ́tí kí ó sì ní ìmọ̀ kún ìmọ̀, sì jẹ́ kí ẹni òye gba ìtọ́sọ́nà.
bularƣa ⱪulaⱪ selixi bilǝn danalar bilimini axuridu, yorutulƣan kixilǝr tehimu dana mǝsliⱨǝtkǝ erixidu,
6 Láti mọ ìtumọ̀ òwe àti ìtán-dòwe, àwọn ọ̀rọ̀ àti àlọ́ àwọn ọlọ́gbọ́n.
xundaⱪla pǝnd-nǝsiⱨǝtlǝr ⱨǝm tǝmsillǝrning mǝnisini, danixmǝnlǝrning ⱨekmǝtliri ⱨǝm tilsim sɵzlirini qüxinidiƣan ⱪilinidu.
7 Ìbẹ̀rù Olúwa ni ìbẹ̀rẹ̀ ìmọ̀, ṣùgbọ́n aláìgbọ́n kẹ́gàn ọgbọ́n àti ẹ̀kọ́.
Pǝrwǝrdigardin ⱪorⱪux bilimning baxlinixidur; Əhmǝⱪlǝr danaliⱪni wǝ tǝrbiyini kɵzgǝ ilmaydu.
8 Tẹ́tí, ìwọ ọmọ mi sí ẹ̀kọ́ baba rẹ, má ṣe kọ ẹ̀kọ́ màmá rẹ sílẹ̀.
I oƣlum, atangning tǝrbiyisigǝ ⱪulaⱪ sal, anangning sɵz-nǝsiⱨǝtidin ayrilma;
9 Wọn yóò jẹ́ òdòdó ẹ̀yẹ olóòórùn dídùn lórí rẹ àti ọ̀ṣọ́ tí ó dára yí ọrùn rẹ ká.
qünki ular sening bexingƣa taⱪalƣan gül qǝmbirǝk, boynungƣa esilƣan marjan bolidu.
10 Ọmọ mi, bí àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀ bá ń tàn ọ́, má ṣe gbà fún wọn.
I oƣlum, yamanlar seni azdursa, ularƣa ǝgǝxmigin.
11 Bí wọn bá wí pé, “Wá pẹ̀lú wa; jẹ́ kí á ba ní ibùba fún ẹ̀jẹ̀ ẹnìkan, jẹ́ kí á lúgọ ní ìkọ̀kọ̀ de aláìṣẹ̀ ní àìnídìí;
Əgǝr ular: — Yür, tuzaⱪ ⱪurup adǝm ɵltürǝyli; Yoxuruniwelip, birǝr bigunaⱨ kǝlgǝndǝ urayli!
12 jẹ́ ká gbé wọn mì láààyè, bí ibojì òkú, àti lódidi, bí àwọn tí ń sọ̀kalẹ̀ lọ sínú kòtò; (Sheol h7585)
Tǝⱨtisaradǝk ularni yutuwetǝyli, Saⱪ bolsimu, ⱨangƣa qüxkǝnlǝrdǝk ularni yiⱪitayli; (Sheol h7585)
13 a ó rí ọ̀pọ̀lọpọ̀ nǹkan tó níye lórí a ó sì fi ìkógun kún inú ilé wa,
Ulardin hilmuhil ⱪimmǝtlik mal-dunyaƣa igǝ bolup, Ɵylirimizni olja bilǝn toldurimiz.
14 da ìpín rẹ pọ̀ mọ́ àárín wa, a ó sì jọ pawó sínú àpò kan náà,”
Biz bilǝn xerik bol, Ⱨǝmyanimiz bir bolsun, desǝ, —
15 ọmọ mi, má ṣe bá wọn lọ, má ṣe rìn ní ojú ọ̀nà wọn.
I oƣlum, ularƣa yoldax bolma, Ɵzüngni ularning izidin neri ⱪil!
16 Nítorí ẹsẹ̀ wọn ń sáré sí ẹ̀ṣẹ̀, wọ́n yára láti ta ẹ̀jẹ̀ sílẹ̀.
Qünki ularning putliri rǝzillikkǝ yügüridu, Ⱪolini ⱪan ⱪilix üqün aldiraydu.
17 Wàhálà asán ni kí ènìyàn máa dẹ àwọ̀n sílẹ̀, ní ojú ẹyẹ!
Ⱨǝrⱪandaⱪ uqar ⱪanat tuyup ⱪalƣanda tuzaⱪ ⱪoyux bikar awariqiliktur;
18 Àwọn ọkùnrin wọ̀nyí ń lúgọ fún ẹ̀jẹ̀ ara wọn. Ara wọn ni wọ́n ń dá lọ́nà.
Lekin bular dǝl ɵz ⱪenini tɵküx üqün saⱪlaydu; Ɵz janliriƣa zamin boluxni kütidu.
19 Báyìí ni ìgbẹ̀yìn gbogbo àwọn tí ń wá èrè àìtọ́; yóò mú ẹ̀mí gbogbo ẹni tí ó rí i lọ.
Nǝpsi yoƣinap kǝtkǝn ⱨǝrbir adǝmning yollirining aⱪiwiti mana xundaⱪ; [Ⱨaram mal-dunya] ɵz igilirining jenini alidu.
20 Ọgbọ́n kígbe sókè ní pópó ó gbé ohùn rẹ̀ sókè láàrín ọjà;
[Büyük] danaliⱪ koqida oquⱪ-axkara hitab ⱪilmaⱪta, Qong mǝydanlarda sadasini anglatmaⱪta.
21 láàrín ọjà ni ó ti kígbe jáde ní ibodè ìlú ni ó ti sọ̀rọ̀ ọ rẹ̀:
Koqa doⱪmuxlirida adǝmlǝrni qaⱪirmaⱪta, Xǝⱨǝr dǝrwazilirida sɵzlirini jakarlimaⱪta: —
22 “Yóò ha ti pẹ́ tó tí ẹ̀yin aláìmọ̀kan yóò fi fẹ́ àìmọ̀kan yín tó? Yóò ha ti pẹ́ tó tí àwọn ẹlẹ́gàn yóò ṣe inú dídùn sí ìpẹ̀gàn tó? Àwọn aláìgbọ́n kórìíra ìmọ̀?
I saddilar, ⱪaqanƣiqǝ muxundaⱪ nadanliⱪⱪa berilisilǝr? Mǝshirǝ ⱪilƣuqilar ⱪaqanƣiqǝ mǝshiriliktin ⱨuzur alsun? Əhmǝⱪlǝr ⱪaqanƣiqǝ bilimdin nǝprǝtlǝnsun?!
23 Bí ẹ bá ti gbọ́ ìbáwí ì mi ni, ǹ bá ti tú ohun tí ó wà nínú ọkàn mi jáde fún yín kí n sì fi inú mi hàn sí i yín.
Tǝnbiⱨlirimgǝ ⱪulaⱪ selip mangƣan yolunglardin yanƣan bolsanglar idi! Roⱨimni silǝrgǝ tɵküp berǝttim, Sɵzlirimni silǝrgǝ bildürgǝn bolattim.
24 Ṣùgbọ́n níwọ̀n bí ẹ ti kọ ìpè ní ìgbà tí mo pè kò sì sí ẹni tí ó kọ ibi ara sí mi gbà tí mo na ọwọ́ sí wọn,
Lekin qaⱪirsam, anglimidinglar; Ⱪolumni uzartsam, ⱨeqⱪaysinglar ⱪarimidinglar.
25 níwọ́n bí ẹ ti kọ gbogbo ìmọ̀ràn mi, tí ẹ̀yin kò sì gba ìbáwí mi,
Nǝsiⱨǝtlirimning ⱨǝmmisigǝ pǝrwa ⱪilmidinglar, Tǝnbiⱨimni anglaxni ⱪilqǝ halimidinglar.
26 Èmi pẹ̀lú yóò fi ìdààmú yín rẹ́rìn-ín; èmi yóò ṣẹ̀fẹ̀ nígbà tí ìyọnu bá dé bá a yín.
Xunga, bexinglarƣa bala-ⱪaza kǝlgǝndǝ külimǝn, Wǝⱨimǝ silǝrgǝ yetixi bilǝn mǝshirǝ ⱪilimǝn.
27 Nígbà tí ìyọnu bá dé bá a yín bí ìjì líle, nígbà tí ìdààmú bá dé bá ọ bí ààjà, nígbà tí wàhálà àti ìbànújẹ́ ọkàn bá bò ọ́ mọ́lẹ̀.
Ⱨalakǝt elip kǝlgǝn wǝⱨimǝ üstünglǝrgǝ qüxkǝndǝ, Wǝyranqiliⱪ silǝrgǝ ⱪuyuntazdǝk kǝlgǝndǝ, Silǝr eƣir ⱪayƣuƣa wǝ azabⱪa muptila bolƣininglarda —
28 “Nígbà náà ni wọn yóò ké pè mí ṣùgbọ́n, èmi kò ní dáhùn; wọn yóò fi ara balẹ̀ wá mi ṣùgbọ́n wọn kì yóò rí mi.
U qaƣda muxu kixilǝr mǝndin ɵtünüp qaⱪiridu, Mǝn pǝrwa ⱪilmaymǝn, Meni tǝlmürüp izdisimu, tapalmaydu.
29 Níwọ́n bí wọ́n ti kórìíra ìmọ̀ tí wọ́n sì kọ̀ láti bẹ̀rù Olúwa.
Ular bilimgǝ nǝprǝtlǝnginidin, Pǝrwǝrdigardin ǝyminixni tallimiƣinidin,
30 Níwọ́n bí wọn kò ti gbà ìmọ̀ràn mi tí wọ́n sì kẹ́gàn ìmọ̀ràn mi,
Mening nǝsiⱨitimni ⱪilqǝ ⱪobul ⱪilƣusi yoⱪluⱪidin, Tǝnbiⱨimgimu pǝrwa ⱪilmiƣininglardin,
31 wọn yóò jẹ èrè iṣẹ́ ọwọ́ wọn wọn yóò sì jèrè èso ètè wọn ní kíkún.
Ular ɵz bexini yǝydu, Ɵz ⱪǝstliridin toluⱪ azab tartidu;
32 Nítorí ìrìnkurìn àwọn aláìmọ̀kan ni yóò pa wọ́n ìkáwọ́gbera aláìgbọ́n ni yóò pa á run;
Qünki saddilarning yoldin qiⱪixi ɵz jeniƣa zamin bolidu; Əhmǝⱪlǝr raⱨǝtlik turmuxidin ɵzlirini ⱨalak ⱪilidu.
33 ṣùgbọ́n ẹnìkan tí ó bá fetí sí mi, yóò gbé láìléwu yóò sì wà nínú ìdẹ̀ra, láìsí ìbẹ̀rù ìpalára.”
Lekin manga ⱪulaⱪ salƣanlar aman-esǝn yaxaydu, Bala-ⱪazalardin, ƣǝm-ǝndixlǝrdin haliy bolup, hatirjǝm turidu.

< Proverbs 1 >