< Proverbs 7 >

1 Ọmọ mi, pa ọ̀rọ̀ mi mọ́, sì fi àwọn òfin mi pamọ́ sínú ọkàn rẹ.
Nagofe! Dawa: ma na adi sia: be di mae gogolema amola na dima hamoma: ne sia: be maedafa gogolema!
2 Pa òfin mi mọ́, ìwọ yóò sì yè tọ́jú ẹ̀kọ́ mi bí ẹyinlójú rẹ.
Na sia: be amo defele hamoma, amasea di da esalumu. Amola di da dia si noga: le ouligibi defele, na olelebe amo noga: le fa: no bobogema.
3 Kọ wọ́n sí ọwọ́ òsì rẹ, má ṣe fi jẹun kọ wọ́n sí inú wàláà àyà rẹ.
Na olelebe liligi eso huluane dawa: laloma amola fedege agoane, dia dogoga noga: le dedema.
4 Wí fún ọgbọ́n pé, “Ìwọ ni arábìnrin mi,” sì pe òye ní ìbátan rẹ.
Di Bagade Dawa: su Hou amoma hou dia dalusi amoma hamobe defele hamoma amola dawa: su dia dogo ganodini diala amo dia na: iyado ema hamobe defele hamoma.
5 Wọn yóò pa ó mọ́ kúrò lọ́wọ́ obìnrin alágbèrè, kúrò lọ́wọ́ àjèjì obìnrin àti ọ̀rọ̀ ìtànjẹ rẹ̀.
Ilia da dia hou huluane ouligili, di da inia uda amoma hobeamu amola ea sefe sia: amo hame nabimu.
6 Ní ojú fèrèsé ilé è mi mo wo ìta láti ojú fèrèsé.
Eso afaega na da na diasu fo misa: ne agenesi amoga ba: lalu.
7 Mo rí i láàrín àwọn aláìmọ̀kan mo sì kíyèsi láàrín àwọn ọ̀dọ́kùnrin, ọ̀dọ́ kan tí ó ṣe aláìgbọ́n.
Amola na ba: loba goi logoga manebe ba: i. Ilia da asigi dawa: su noga: i hame galu amola afadafa da gagaoui dunu agoai ba: i.
8 Ó ń lọ ní pópónà ní tòsí i ilé alágbèrè obìnrin náà, ó ń rìn lọ sí ọ̀nà ilé e rẹ̀.
Amo goi da uda afadafa ea diasu gadenene misini,
9 Ní ìrọ̀lẹ́ bí oòrùn ṣe ń wọ̀, bí òkùnkùn ṣe ń bo ni lára.
eso amola sa: i dagoi gadenene gasi dagoi.
10 Bẹ́ẹ̀ ni obìnrin kan jáde wá láti pàdé rẹ̀, ó múra bí panṣágà pẹ̀lú ètè búburú.
Amo uda e da hina: da: i bidi lasu uda defele abula ida: iwane ga: i amola e da hou ilegelalu.
11 (Ó jẹ́ aláriwo àti alágídí, ìdí rẹ̀ kì í jókòó nílé;
Goe uda amo da gasa fi hamosu uda amola gogosiasu hame dawa: i. E da moilai logoga lalusu.
12 bí ó ti ń já níhìn-ín ní ó ń já lọ́hùn ún gbogbo orígun ni ó ti ń ba ní ibùba.)
E da logoga udigili lalu amola bidi lama: ne diasu labe soge ganodini amola dunu hogosa lalala.
13 Ó dìímú, ó sì fẹnukò ó ní ẹnu pẹ̀lú ojú díndín ó wí pé,
Amola na ba: i, amalalu amo uda e da goi ayeligi amo ea galogoa amoga ea lobo la: boloi dagoi amo lalu e da amo goi nonogonanu e hedolowane si damana ba: i amalalu e amane sia: i,
14 “Mo ní ọrẹ àlàáfíà ní ilé; lónìí ni mo san ẹ̀jẹ́ mi.
“Wali na da gobele salasu hamoi amola amo gobele salasu hu da na diasuga diala.
15 Nítorí náà ni n o ṣe jáde wá pàdé è rẹ; mo wá ọ káàkiri mo sì ti rí ọ!
Amaiba: le na da na diasu yolesili di hogola misi amola wali na da di ba: i dagoi.
16 Mo ti tẹ́ ibùsùn mi pẹ̀lú aṣọ aláràbarà láti ilẹ̀ Ejibiti.
Na da hedolowane midunusa: diaheda: su ida: iwane hahamoi dagoi amo dedebosu abula ida: iwane gala amo da na Idibidi soge amoga gaguli misi.
17 Mo ti fi nǹkan olóòórùn dídùn sí ibùsùn mi bí i òjìá, aloe àti kinamoni.
Na da amo ganodini manoma ida: iwane gala amo me, a:lou, sinamone amola amo manoma gabusiga: ida: iwane gala fafai da: iya sogadigi.
18 Wá, jẹ́ kí a lo ìfẹ́ papọ̀ ní kíkún títí di àárọ̀; jẹ́ kí a gbádùn ara wa pẹ̀lú ìfẹ́!
Misa! Na amola di gilisili hedelala soge hadigimu. Ani da gilisili nonogomuba: le hahawane bagade ba: mu.
19 Ọkọ ọ̀ mi ò sí nílé; ó ti lọ sí ìrìnàjò jíjìn.
Di da na dunuba: le mae beda: ma. E da soge sedaga asi esala.
20 Ó mú owó púpọ̀ lọ́wọ́ kò sì ní darí dé kí ó tó di ọ̀sán.”
E da su bagade gaguli asi. E da hedolo hame bu misunu. E da esala hi aduna aligimu.”
21 Pẹ̀lú ọ̀rọ̀ dídùn ó sì í lọ́nà; ó tàn án jẹ pẹ̀lú ẹnu dídùn.
Goe uda ea sefe sia: bagadewane sia: beba: le, goi ayeligi da dafai dagoi.
22 Òun sì tọ̀ ọ́ lọ lẹsẹ̀ kan náà, bí i màlúù tí ń lọ sí ibi pípa, tàbí bí àgbọ̀nrín tí ń lọ sí ibi okùn ìso.
Amo dunu e da amo sia: nababeba: le, e da hedolowane amo uda fa: no bobogele diasuga asi. Fedege sia: e da bulamagau bogoma: ne fasu sogebi amoga oule ahoasu defele asi. Fedege sia: eno e da ‘dia’ ohe amo da sani sa: ima: ne hahawane ahoa amo defele asi.
23 Títí tí ọ̀kọ̀ fi gún un ní ẹ̀dọ̀, bí ẹyẹ ṣe ń fẹ́ wọ inú okùn, láìmọ̀ pé yóò gba ẹ̀mí òun.
Amo ‘dia’ ohe e da hame dawa: i ea dogo ganodini souga gala: be defele e da bogomu da hame dawa: i. Amo dunu ea hamobe da sio afae e hagili ahoanebe defele ba: i. Amo sio e da segega: i amo mae ba: le ahoabe amola sio e amo segega: i amo hame dawa: i amoga gaguli bogomu amo hame dawa: i.
24 Nítorí náà báyìí ẹ̀yin ọmọ mi, tẹ́tí sí mi fọkàn sí nǹkan tí mo sọ.
Wali na gofelali, dilia na sia: noga: le nabima. Noga: le dawa: ma!
25 Má ṣe jẹ́ kí ọkàn rẹ kí ó yà sí ọ̀nà rẹ̀, tàbí kí ó rìn lọ sí ipa ọ̀nà rẹ̀.
Agoaiwane uda amo ea sefe sia: mae nabima! Ema mae fa: no bobogema!
26 Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ni àwọn tí ó ti fà lulẹ̀. Ogunlọ́gọ̀ àwọn alágbára ni ó ti pa.
Amo uda e da dunu bagohame ilia hou wadela: lesi dagoi. Amola dunu bagohame idimu hame gala, ilia da ea hou hamobeba: le bogoi dagoi.
27 Ilé e rẹ̀ ni ọ̀nà tààrà sí isà òkú, tí ó lọ tààrà sí àgbàlá ikú. (Sheol h7585)
Amola di da amo uda ea diasuga ahoasea, di da bogosu logo amoga ahoa. Amo ahoasu da hedolodafa bogosu amoga doaga: sa. (Sheol h7585)

< Proverbs 7 >