< Proverbs 3 >

1 Ọmọ mi, má ṣe gbàgbé ẹ̀kọ́ mi. Ṣùgbọ́n pa òfin mi mọ́ sí ọkàn rẹ.
Mũrũ wakwa, ndũkariganĩrwo nĩ ũrutani wakwa, no ngoro yaku nĩĩrũmagie maathani makwa,
2 Nítorí ọjọ́ gígùn, ẹ̀mí gígùn, àti àlàáfíà, ni wọn yóò fi kùn un fún ọ.
nĩgũkorwo nĩmagakuongerera matukũ ũtũũre mĩaka mĩingĩ, na matũme ũgaacĩre.
3 Má ṣe jẹ́ kí ìfẹ́ àti òtítọ́ ṣíṣe fi ọ́ sílẹ̀ láéláé so wọ́n mọ́ ọrùn rẹ, kọ wọ́n sí wàláà àyà rẹ.
Ndũkanareke wendani na wĩhokeku ikweherere; cioherere ngingo yaku, ũciandĩke kĩhengere-inĩ kĩa ngoro yaku.
4 Nígbà náà ni ìwọ yóò rí ojúrere àti orúkọ rere ní ojú Ọlọ́run àti lójú ènìyàn.
Weka ũguo nĩũgeetĩkĩrĩka, na ũgĩe na rĩĩtwa rĩega maitho-inĩ ma Ngai o na ma andũ.
5 Gbẹ́kẹ̀lé Olúwa pẹ̀lú gbogbo ọkàn rẹ má ṣe sinmi lé òye ara à rẹ.
Wĩhoke Jehova na ngoro yaku yothe, na ndũkanehoke ũmenyo waku mwene;
6 Mọ̀ ọ́n ní gbogbo ọ̀nà rẹ òun yóò sì máa tọ́ ipa ọ̀nà rẹ.
mũmenyithagie mĩthiĩre yaku yothe, na nĩarĩrũngaga njĩra ciaku.
7 Má ṣe jẹ́ ọlọ́gbọ́n lójú ara à rẹ bẹ̀rù Olúwa kí o sì kórìíra ibi.
Tiga kwĩonaga ũrĩ mũũgĩ maitho-inĩ maku mwene; wĩtigĩre Jehova na ũtheemage maũndũ marĩa mooru.
8 Èyí yóò mú ìlera fún ara rẹ àti okun fún àwọn egungun rẹ.
Ũndũ ũcio nĩũrĩkũrehagĩra ũgima wa mwĩrĩ, na mahĩndĩ maku makoragwo marĩ na hinya.
9 Fi ọrọ̀ rẹ bọ̀wọ̀ fún Olúwa, pẹ̀lú àkọ́so oko rẹ,
Tĩĩaga Jehova na ũtonga waku, ningĩ ũmũtĩĩage na maciaro mothe ma mbere ma irio ciaku cia mĩgũnda;
10 nígbà náà ni àká rẹ yóò kún àkúnya àgbá rẹ yóò kún àkúnwọ́sílẹ̀ fún wáìnì tuntun.
namo makũmbĩ maku nĩmakaiyũrĩrĩra, nayo mĩtũngi yaku ĩiyũrĩrĩre ndibei ya mũhihano.
11 Ọmọ mi, má ṣe kẹ́gàn ìbáwí Olúwa má sì ṣe bínú nígbà tí ó bá ń bá ọ wí,
Mũrũ wakwa, tiga kũnyarara ihũũra rĩa Jehova, na ndũgathũũre irũithia rĩake,
12 nítorí Olúwa a máa bá àwọn tí ó fẹ́ràn wí bí baba ti í bá ọmọ tí ó bá nínú dídùn sí wí.
nĩgũkorwo Jehova arũithagia arĩa endete, o ta ũrĩa ithe wa mũndũ arũithagia mũriũ ũrĩa akenagĩra.
13 Ìbùkún ni fún ẹni tí ó ní ìmọ̀, ẹni tí ó tún ní òye sí i,
Kũrathimwo-rĩ, nĩ mũndũ ũrĩa wonete ũũgĩ, mũndũ ũcio wĩgĩĩrĩire na ũmenyo,
14 nítorí ó ṣe èrè ju fàdákà lọ ó sì ní èrè lórí ju wúrà lọ.
nĩgũkorwo ũũgĩ nĩ wa bata mũno gũkĩra betha, na ũciaraga uumithio ũkĩrĩte wa thahabu.
15 Ó ṣe iyebíye ju iyùn lọ; kò sí ohunkóhun tí a lè fiwé e nínú ohun gbogbo tí ìwọ fẹ́.
Ũũgĩ ũrĩ goro gũkĩra ruru iria ndune; kĩrĩa gĩothe ũngĩĩrirĩria gũtirĩ kĩngĩringithanio naguo.
16 Ẹ̀mí gígùn ń bẹ ní ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀; ní ọwọ́ òsì rẹ sì ni ọrọ̀ àti ọlá.
Guoko-inĩ gwake kwa ũrĩo harĩ ũingĩ wa matukũ; guoko-inĩ gwake kwa ũmotho harĩ na ũtonga na gĩtĩĩo.
17 Àwọn ọ̀nà rẹ jẹ́ ọ̀nà ìtura, òpópónà rẹ sì jẹ́ ti àlàáfíà.
Mĩthiĩre ya ũũgĩ nĩ mĩthiĩre ya kwendeka, na njĩra ciaguo ciothe nĩ cia thayũ.
18 Igi ìyè ni ó jẹ́ fún gbogbo ẹni tí ó bá gbà á; àwọn tí ó bá sì dìímú yóò rí ìbùkún gbà.
Ũũgĩ nĩ mũtĩ wa muoyo kũrĩ arĩa maũhĩmbagĩria; arĩa megĩagĩra naguo-rĩ, nĩmarĩrathimagwo.
19 Nípa ọgbọ́n, Olúwa fi ìpìlẹ̀ ilẹ̀ ayé sọlẹ̀; nípa òye, ó fi àwọn ọ̀run sí ipò wọn;
Jehova aahandire mĩthingi ya thĩ na ũũgĩ, na akĩrũmia igũrũ na ũmenyo wake;
20 nípa ìmọ̀ rẹ̀ ó pín ibú omi ní yà, àwọsánmọ̀ sì ń sẹ ìrì.
ũmenyo wake nĩguo wagayanirie kũrĩa kũriku, namo matu magatatagia ime.
21 Ọmọ mi, pa ọgbọ́n tí ó yè kooro àti ìmòye mọ́, má jẹ́ kí wọn lọ kúrò ní ibi tí ojú rẹ ti le tó wọn.
Mũrũ wakwa tũũria matua mega na ũkũũrani maũndũ, ndũkanareke ciehere maitho-inĩ maku;
22 Wọn yóò jẹ́ ìyè fún ọ, àti ẹ̀ṣọ́ fún ọrùn rẹ.
nĩcio igaagũtũũria muoyo, na nĩ ithaga rĩa kũgemagia ngingo yaku.
23 Nígbà náà ni ìwọ yóò bá ọ̀nà rẹ lọ ní àìléwu, ìwọ kì yóò sì kọsẹ̀.
Ningĩ ũrĩthiiaga na njĩra yaku ũrĩ na thayũ, na kũgũrũ gwaku gũtikahĩngwo;
24 Nígbà tí ìwọ bá dùbúlẹ̀, ìwọ kì yóò bẹ̀rù, nígbà tí ìwọ bá dùbúlẹ̀, oorun rẹ yóò jẹ́ oorun ayọ̀.
Wakoma-rĩ, ndũgetigĩra; wakoma-rĩ, ũrĩkomaga toro mwega.
25 Má ṣe bẹ̀rù ìdààmú òjijì, tàbí ti ìparun tí ó ń dé bá àwọn ènìyàn búburú.
Ndũgetigĩre mwanangĩko wa narua, kana kĩhuhũkanio kĩrĩa gĩkoragĩrĩra andũ arĩa aaganu,
26 Nítorí Olúwa yóò jẹ́ ìgbẹ́kẹ̀lé rẹ, kì yóò sì jẹ́ kí ẹsẹ̀ rẹ bọ́ sínú pàkúté.
nĩgũkorwo Jehova nĩwe ũgaatuĩka mwĩhoko waku, na amenyagĩrĩre kũgũrũ gwaku gũtikanyiitwo nĩ mũtego.
27 Má ṣe fa ọwọ́ ìre sẹ́yìn kúrò lọ́dọ̀ àwọn tí ṣe tìrẹ, nígbà tí ó bá wà ní ìkápá rẹ láti ṣe ohun kan.
Ndũkanagirĩrĩrie ũndũ mwega ũkinyĩre arĩa maagĩrĩirwo nĩgũkinyĩrĩrwo nĩguo, rĩrĩa ũrĩ na ũhoti wa kũhingia ũndũ ũcio.
28 Má ṣe wí fún aládùúgbò rẹ pé, “Padà wá nígbà tó ṣe díẹ̀; èmi yóò fi fún ọ ní ọ̀la,” nígbà tí o ní i pẹ̀lú rẹ nísinsin yìí.
Ndũkaneere mũndũ wa itũũra rĩaku atĩrĩ, “Thiĩ ũgooka rĩngĩ; kĩu ũrenda nĩngakũhe rũciũ,” o rĩrĩa ũrĩ na kĩndũ kĩu hakuhĩ.
29 Má ṣe pète ohun búburú fún aládùúgbò rẹ, ti o gbé nítòsí rẹ, tí ó sì fọkàn tán ọ.
Ndũkanaciirĩre gwĩka mũndũ wa itũũra rĩaku ũũru, ũcio ũtũũraga hakuhĩ nawe akwĩhokete.
30 Má ṣe fẹ̀sùn kan ènìyàn láìnídìí, nígbà tí kò ṣe ọ́ ní ibi kankan rárá.
Ndũkanarũithie mũndũ tũhũ, rĩrĩa atarĩ ũndũ mũũru agwĩkĩte.
31 Má ṣe ṣe ìlara ènìyàn jàgídíjàgan tàbí kí o yàn láti rìn ní ọ̀nà rẹ̀.
Ndũkanacumĩkĩre maũndũ ma mũndũ wa ngũĩ, kana ũthuure njĩra o na ĩmwe yake,
32 Nítorí Olúwa kórìíra ènìyàn aláyídáyidà ṣùgbọ́n a máa fọkàn tán ẹni dídúró ṣinṣin.
nĩgũkorwo Jehova nĩathũire mũndũ mwaganu, no nĩagĩĩaga ndundu na andũ arĩa arũngĩrĩru.
33 Ègún Olúwa ń bẹ lórí ilé ènìyàn búburú, ṣùgbọ́n ó bùkún fún ilé olódodo.
Nyũmba ya arĩa aaganu ĩtũũraga na kĩrumi kĩa Jehova, no mũciĩ wa arĩa athingu nĩaũrathimaga.
34 Ó fi àwọn ẹlẹ́yà ṣe yẹ̀yẹ́, ṣùgbọ́n ó fi oore-ọ̀fẹ́ fún onírẹ̀lẹ̀.
Jehova nĩanyũrũragia andũ arĩa manyũrũranagia na mwĩtĩĩo, no arĩa menyiihagia nĩamaheaga wega wake.
35 Ọlọ́gbọ́n jogún iyì, ṣùgbọ́n àwọn aṣiwèrè ni yóò ru ìtìjú wọn.
Andũ arĩa oogĩ magayaga gĩtĩĩo, no andũ arĩa akĩĩgu magayaga njono.

< Proverbs 3 >