< Proverbs 29 >

1 Ẹni tí ó sì ń ṣorí kunkun lẹ́yìn ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìbáwí yóò parun lójijì láìsí àtúnṣe.
Dunu da dima dawa: ma: ne gagabole sia: sea, di da eso huluane ilia sia: hihini amola hame nabasea, eso enoga di da dafane, bu wa: legadomu gogolemu.
2 Nígbà tí olódodo bá ń gbilẹ̀, àwọn ènìyàn a yọ̀ nígbà tí ènìyàn búburú ń ṣàkóso, àwọn ènìyàn ń kórìíra.
Moloidafa ouligisu dunu amo ea fi dunu da noga: le hahawane esala. Be moloi hame ouligisu dunu amo ea fi dunu da gayane, da: i dione esala.
3 Ènìyàn tí ó fẹ́ràn ọgbọ́n mú kí baba rẹ̀ láyọ̀ ṣùgbọ́n ẹni ti ń bá panṣágà kẹ́gbẹ́ ba ọrọ̀ ọ rẹ̀ jẹ́.
Nowa dunu e da Bagade Dawa: su Hou hogoi helesea, ea ada da ema hahawane amola nodoi ganumu. Be nowa dunu da sasagesu uda ema muni bagade galagasea da gagaoui bagade agoai.
4 Nípa ìdájọ́ òdodo ni ọba fi í mú ìlú tòrò nini, ṣùgbọ́n èyí tí ń ṣe ojúkòkòrò àbẹ̀tẹ́lẹ̀ fà á lulẹ̀.
Hina bagade da moloidafa hou hanai galea, ea fifi asi gala da gasa bagade dialumu. Be hina bagade da muni hanai fawane galea, e da ea fi dunu wadela: lesimu.
5 Ẹnikẹ́ni tí ó bá tan aládùúgbò rẹ̀ ó ń dẹ àwọ̀n de ẹsẹ̀ ẹ rẹ̀.
Di da dia dogolegei ilima dabua hahaeafusia, di da dina: sa: ima: ne sanisa.
6 Ẹ̀ṣẹ̀ ènìyàn ibi ni ó jẹ́ ìdẹ̀kùn rẹ̀ ṣùgbọ́n olódodo le è kọrin kí ó sì máa yọ̀.
Wadela: le hamosu dunu ilia hou da ilila: sa: ima: ne sani agoai gala. Be molole hamosu dunu da hahawane halegale lala.
7 Olódodo ń máa ro ọ̀rọ̀ tálákà, ṣùgbọ́n ènìyàn búburú kò sú sí i láti rò ó.
Noga: i dunu da hame gagui dunu amola dunu huluane defele ba: sa. Be wadela: le hamosu dunu ilia amo hou hame dawa: sa.
8 Àwọn ẹlẹ́yà a máa ru ìlú sókè, ṣùgbọ́n àwọn ọlọ́gbọ́n ènìyàn máa ń mú ìbínú kúrò.
Hina: hou gaguia gadosu dunu da moilai bai bagade ilia fi wili gala: musa: hamosa. Be bagade dawa: su dunu da hou bu olofoma: ne hamosa.
9 Bí ọlọ́gbọ́n ènìyàn bá lọ sí ilé ẹjọ́ pẹ̀lú aláìgbọ́n aláìgbọ́n a máa bínú a sì máa jà, kò sì ní sí àlàáfíà.
Dadawa: su dunu da gagaoui dunu ema fofada: sea, gagaoui dunu da dodona: gini ofesega: su fawane hamosa.
10 Àwọn tí ó ń tàjẹ̀ sílẹ̀ kò rí ẹni dídúró ṣinṣin wọ́n sì ń wá ọ̀nà láti pa olódodo.
Fuga: su dunu da molole hamosu dunu higasa. Be moloidafa dunu da asabole molole hamosu dunu ilia esalusu gaga: sa.
11 Aláìgbọ́n ènìyàn fi gbogbo ẹnu rẹ̀ bínú ṣùgbọ́n ọlọ́gbọ́n ènìyàn a máa kó ìbínú rẹ̀ ní ìjánu.
Noga: le hame dawa: su dunu ilia da ilia ougi hou dunu huluane ba: ma: ne olelesa. Be noga: le dawa: su dunu ilia da ilia ougi hou gagulaligisa.
12 Bí olórí bá fetí sí irọ́, gbogbo àwọn ìjòyè rẹ̀ a di ènìyàn búburú lójú rẹ̀.
Ouligisu dunu da ogogosu sia: amo nabasea, e fidili hawa: hamosu dunu huluane da ogogosu dunu agoai ba: mu.
13 Tálákà ènìyàn àti aninilára jọ ní àbùdá yìí, Olúwa jẹ́ kí ojú àwọn méjèèjì máa ríran.
Hame gagui dunu amola ema se iabe banenesisu dunu elea hou da hisu hisu. Be liligi afadafa da defele. Hina Gode da elama si defele i dagoi.
14 Bí ọba kan bá ń ṣe ìdájọ́ tálákà pẹ̀lú òtítọ́ ìtẹ́ ìjọba rẹ yóò fìdímúlẹ̀ nígbà gbogbo.
Hina bagade da hame gagui dunu noga: le gaga: sea, e da ode bagohame ouligisa ahoanumu.
15 Ọ̀pá ìbániwí ń fún ni ní ọgbọ́n ṣùgbọ́n ọmọ tí a fi sílẹ̀ fúnra rẹ̀ a dójútì ìyá rẹ̀.
Mano fofonobo huluane dawa: ma: ne mololesisia, amo da ilia hou noga: le fidisa. Be mano da hi hanai hou hamosea, eme da gogosiamu.
16 Nígbà tí ènìyàn búburú ń gbilẹ̀, bẹ́ẹ̀ náà ni ẹ̀ṣẹ̀ ń gbilẹ̀ ṣùgbọ́n olódodo yóò rí ìṣubú wọn.
Wadela: le hamosu dunu da fi dunu ouligisia, wadela: i hou da bagade heda: sa. Be moloidafa dunu da mae bogole amo wadela: i ouligisu dunu ilia dafabe ba: mu.
17 Bá ọmọ rẹ wí, yóò sì fún ọ ní àlàáfíà yóò sì mú inú dídùn wá sí inú ọkàn rẹ.
Dia gofe da hou noga: le dawa: ma: ne, ema noga: le dawa: ma: ne se ianu mololesima. Amasea, di da ea hou hamoi noga: iba: le, hame gogosiamu.
18 Níbi tí kò ti sí ìfihàn, àwọn ènìyàn a gbé ìgbé ayé àìbìkítà, ṣùgbọ́n ìbùkún ní fún àwọn tí ń pa òfin mọ́.
Fifi asi gala da Godema hame fa: no bobogesea, da udigili gugunufisa. Nowa dunu da Gode Ea sema nabawane fa: no bobogesea da hahawane gala.
19 A kò le fi ọ̀rọ̀ lásán kìlọ̀ fún ìránṣẹ́ bí ó tilẹ̀ yé e, kò ní kọbi ara sí i.
Di da dia hawa: hamosu dunuma ea hou mololesimusa: sia: fawane sia: sea, e da dia sia: ea gega nabimu, be ea hou hame afadenemu.
20 Ǹjẹ́ ó rí ènìyàn tí ń kánjú sọ̀rọ̀? Ìrètí wà fún aláìgbọ́n jù ú lọ.
Gagaoui dunu ea hou da hamedei gala. Be momabone sia: su dunu da mae dawa: le hedolo sia: sea, ea hou da baligili hamedei agoai ba: sa.
21 Bí ènìyàn kan bá kẹ́ ìránṣẹ́ rẹ̀ lákẹ̀ẹ́jù láti kékeré yóò mú ìbànújẹ́ wá ní ìgbẹ̀yìn.
Di da dia hawa: hamosu dunu amoma ea goihadiniganini eso amola fa: no, amo hi hanai liligi huluane ema iasea, e da eso enoga dia liligi huluane ladili dagomu.
22 Oníbìínú ènìyàn a ru ìjà sókè, onínú-fùfù ènìyàn a sì máa dá ọ̀pọ̀lọpọ̀ ẹ̀ṣẹ̀.
Hedolo momabone ougisu dunu ilia hamobeba: le, sia: ga gegesu amola bidi hamosu bagade doaga: sa.
23 Ìgbéraga ènìyàn a máa sọ ọ́ di ẹni ilẹ̀ ṣùgbọ́n onírẹ̀lẹ̀ ènìyàn a máa gba iyì kún iyì.
Di da gasa fi hou hamosea, fa: no dafamu. Be di da asabole hamosea, eno dunu da dima nodone dawa: mu.
24 Ẹni tí ó ń kó ẹgbẹ́, olè kórìíra ọkàn ara rẹ̀, ó ń gbọ́ èpè olóhun kò sì le è fọhùn.
Wamolasu dunu ea na: iyado da hihima ha laidafa gala. E da fofada: su dunuma molole sia: sea, ea na: iyado da ema se imunu. Be e da ogogosea, e da Gode Ea se iasu ba: mu.
25 Ìbẹ̀rù ènìyàn kan yóò sì di ìdẹ̀kùn ṣùgbọ́n ẹnikẹ́ni tí ó bẹ̀rù Olúwa wà láìléwu.
Di da dunu eno ilia dia hou habaila: le dawa: su, di bagade da: i dione dawa: sea da se nabasu liligi agoane. Be di da Hina Godema dafawaneyale dawa: sea, E da di gaga: mu.
26 Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ni ń wá ojúrere alákòóso, ṣùgbọ́n láti ọ̀dọ̀ Olúwa ni ènìyàn tí ń gba ìdájọ́ òdodo.
Dunu huluane da ouligisu dunu ea ilima nodone dawa: ma: ne hanasa. Be Hina Gode Hi fawane da ilima moloidafa hou hamosa.
27 Olódodo kórìíra àwọn aláìṣòótọ́: ènìyàn búburú kórìíra olódodo.
Molole hamosu dunu ilia da wadela: le hamosu dunuma higasa. Amola wadela: le hamosu dunu, ilia da molole hamosu dunuma higasa.

< Proverbs 29 >