< Proverbs 19 >

1 Ó sàn kí ènìyàn jẹ́ tálákà tí ìrìn rẹ̀ kò lábùkù ju aláìgbọ́n tí ètè rẹ̀ jẹ́ àyídáyidà.
Nĩ kaba mũndũ mũthĩĩni ũrĩa ũthiiaga na mĩthiĩre ĩtarĩ ũcuuke, gũkĩra mũndũ mũkĩĩgu waragia waganu.
2 Kò dára láti ní ìtara láìní ìmọ̀, tàbí kí ènìyàn kánjú kí ó sì ṣìnà.
Ti wega kũgĩa na kĩyo hatarĩ na ũmenyo, ningĩ kũhĩkĩka mũno gũtũmaga mũndũ ahĩtie njĩra.
3 Ìwà òmùgọ̀ ènìyàn fúnra rẹ̀ a pa ẹ̀mí rẹ̀ run; síbẹ̀ ọkàn rẹ̀ yóò máa bínú sí Olúwa.
Ũrimũ wa mũndũ nĩguo wanangaga muoyo wake, nayo ngoro yake ĩtetagia Jehova.
4 Ọrọ̀ máa ń fa ọ̀rẹ́ púpọ̀; ṣùgbọ́n ọ̀rẹ́ tálákà tún kọ̀ ọ́ sílẹ̀.
Ũtonga nĩwongagĩrĩra mũndũ arata aingĩ, no mũndũ mũthĩĩni nĩeheragĩrwo nĩ mũratawe.
5 Ajẹ́rìí èké kò ní lọ láìjìyà, ẹni tí ó sì ń tú irọ́ jáde kò ní lọ lọ́fẹ̀ẹ́.
Mũira wa maheeni ndakaaga kũherithio, na ũrĩa ũitũrũraga maheeni ndageethara.
6 Ọ̀pọ̀ ń wá ojúrere olórí; gbogbo ènìyàn sì ni ọ̀rẹ́ ẹni tí ó lawọ́.
Andũ aingĩ macaragia ũrĩa mangĩendwo nĩ mũnene, na mũndũ mũheani iheo-rĩ, nĩ mũrata wa andũ othe.
7 Gbogbo ará ilé e tálákà ni ó pa á tì, mélòó mélòó ni ti àwọn ọ̀rẹ́ rẹ̀ tí ń sá fún un! Bí ó tilẹ̀ ń lé wọn kiri pẹ̀lú ẹ̀bẹ̀, kò tilẹ̀ le rí wọn rárá.
Angĩkorwo mũndũ mũthĩĩni nĩatiganagio nĩ andũ ao othe-rĩ, ĩ nao arata ake mangĩkĩmwĩtheema atĩa! O na angĩmathingata akĩmathaithaga, nĩmethiĩrĩire, matirĩ ho.
8 Ẹni tí ó gba ọgbọ́n fẹ́ràn ọkàn ara rẹ̀; ẹni tí ó bá káràmáṣìkí òye yóò gbèrú.
Mũndũ ũrĩa wĩgĩĩagĩra na ũũgĩ nĩ ngoro yake mwene endete; ũrĩa ũkenagĩra ũtaũku nĩagaacagĩra.
9 Ajẹ́rìí èké kì yóò lọ láìjìyà ẹni tí ó sì ń tú irọ́ jáde yóò parun.
Mũira wa maheeni ndakaaga kũherithio, na ũrĩa ũitũrũraga maheeni nĩakoorwo nĩ muoyo.
10 Kò yẹ aláìgbọ́n láti máa gbé nínú ọláńlá, mélòó mélòó bí ó ti burú tó fún ẹrú láti jẹ ọba lórí ọmọ-aládé.
Gũtiagĩrĩire mũndũ mũkĩĩgu gũikaraga egangarĩte; gũkĩrĩ ũũru makĩria ngombo gwatha anene!
11 Ọgbọ́n ènìyàn a máa fún un ní sùúrù; fún ògo rẹ̀ ni láti fojú fo àṣìṣe dá.
Ũũgĩ wa mũndũ nĩũmũheaga ũkirĩrĩria, riiri wake nĩkũrekera andũ arĩa angĩ mahĩtia mao.
12 Ìbínú ọba dàbí kíké e kìnnìún, ṣùgbọ́n ojúrere rẹ̀ dàbí ìrì lára koríko.
Marakara ma mũthamaki nĩ ta mũraramo wa mũrũũthi, no ũtugi wake nĩ ta ime rĩrĩ nyeki-inĩ.
13 Aṣiwèrè ọmọ jẹ́ ìparun baba rẹ̀, aya tí ó máa ń jà sì dàbí ọ̀ṣọ̀ọ̀rọ̀ òjò.
Mwana mũkĩĩgu nĩ mwanangĩko harĩ ithe, na mũtumia wa haaro ahaana ta maaĩ maratata mategũtigithĩria.
14 A máa ń jogún ilé àti ọrọ̀ lọ́dọ̀ òbí, ṣùgbọ́n aya olóye láti ọ̀dọ̀ Olúwa ni.
Nyũmba na ũtonga igayagwo kuuma kũrĩ aciari, no mũtumia mũbaarĩrĩri maũndũ oimaga kũrĩ Jehova.
15 Ọ̀lẹ ṣíṣe máa ń fa oorun sísùn fọnfọn, ebi yóò sì máa pa ènìyàn tí ó lọ́ra.
Ũgũũta ũrehaga toro mũnene, na mũndũ gĩthayo arĩĩagwo nĩ ngʼaragu.
16 Ẹnikẹ́ni tí ó gbọ́ ẹ̀kọ́ pa ẹnu rẹ̀ mọ́, ṣùgbọ́n ẹni tí ó bá kẹ́gàn ọ̀nà rẹ̀ yóò kú.
Mũndũ ũrĩa wathĩkagĩra maathani-rĩ, nĩ muoyo wake amenyagĩrĩra, no ũrĩa ũtoonaga bata wa kũmenyerera mĩthiĩre yake nĩagaakua.
17 Ẹni tí ó ṣàánú tálákà, Olúwa ní ó yá, yóò sì pín in lérè ohun tí ó ti ṣe.
Mũndũ ũrĩa ũiguagĩra athĩĩni tha nĩ Jehova akombagĩra indo, nake Jehova nĩakamũrĩha nĩ ũndũ wa ũrĩa ekĩte.
18 Bá ọmọ rẹ wí nítorí nínú ìyẹn ni ìrètí wà; àìṣe bẹ́ẹ̀ ìwọ lọ́wọ́ nínú ìparun un rẹ̀.
Rũithagia mũrũguo hĩndĩ ĩrĩa kũrĩ na kĩĩrĩgĩrĩro; tiga kwenda gũtũma akooragwo.
19 Ènìyàn onínú-fùfù gbọdọ̀ gba èrè ìwà rẹ̀; bí ìwọ bá gbà á là, ìwọ yóò tún ní láti ṣe é lẹ́ẹ̀kan sí i.
Mũndũ wa marakara mahiũ no nginya aherithio; ũngĩmũteithũra rĩmwe no nginya ũkaamũteithũra rĩngĩ.
20 Fetí sí ìmọ̀ràn kí o sì gba ẹ̀kọ́, ní ìgbẹ̀yìn gbẹ́yín ìwọ yóò di ọlọ́gbọ́n.
Thikĩrĩria mataaro na wĩtĩkĩre ũrutani, marigĩrĩrio-inĩ nĩũgaatuĩka mũndũ mũũgĩ.
21 Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ni ète inú ọkàn ènìyàn, ṣùgbọ́n ìfẹ́ Olúwa ní ó máa ń borí.
Mĩbango ya ngoro ya mũndũ nĩ mĩingĩ, no muoroto wa Jehova noguo ũkaahinga.
22 Ohun tí ènìyàn ń fẹ́ ni ìfẹ́ tí kì í yẹ̀; ó sàn láti jẹ́ tálákà ju òpùrọ́ lọ.
Kĩrĩa mũndũ eriragĩria nĩ wendo ũrĩa ũtathiraga, nĩ kaba gũthĩĩna gũkĩra mũndũ wa maheeni.
23 Ìbẹ̀rù Olúwa ń mú ìyè wá; nígbà náà ọkàn ń balẹ̀, láìsí ewu.
Gwĩtigĩra Jehova gũkinyagia mũndũ muoyo-inĩ: Hĩndĩ ĩyo mũndũ akahurũka aiganĩire, atarĩ na thĩĩna.
24 Ọ̀lẹ ki ọwọ́ rẹ̀ bọ inú àwo oúnjẹ; kò tilẹ̀ ní mú u padà wá sí ẹnu rẹ̀.
Kĩgũũta kĩrikagia guoko gwakĩo thaani-inĩ; gĩgakĩremwo o na nĩgũgũcookia kanua!
25 Na ẹlẹ́gàn, òpè yóò sì kọ́gbọ́n; bá olóye ènìyàn wí, yóò sì ní ìmọ̀ sí i.
Hũũra mũnyũrũrania, nao arĩa mateciiragia merute kũgĩa na ũbaarĩrĩri; kaania mũkũũrani maũndũ, na nĩekuongerera ũmenyo.
26 Ẹni tí ó ṣìkà sí baba rẹ̀, tí ó sì lé ìyá rẹ̀ jáde òun ni ọmọ tí ń ṣe ìtìjú, tí ó sì mú ẹ̀gàn wá.
Mũndũ ũrĩa ũtunyaga ithe indo na akaingata nyina, nĩ mwana wa kũrehe thoni na gĩconoko.
27 Ọmọ mi, dẹ́kun láti tẹ́tí sí ẹ̀kọ́, tí í mú ni ṣìnà kúrò nínú ọ̀rọ̀-ìmọ̀.
Mũrũ wakwa, ũngĩtiga gũthikĩrĩria mataaro-rĩ, nĩũkoora njĩra ũtigane na ciugo cia ũmenyo.
28 Ẹlẹ́rìí búburú fi ìdájọ́ ṣẹ̀sín, ẹnu ènìyàn búburú sì ń gbé ibi mì.
Mũira wa kũhakwo anyũrũragia kĩhooto, na kanua ka mũndũ mwaganu kameragia o ũũru.
29 A ti pèsè ìjìyà sílẹ̀ fún ẹlẹ́gàn; àti pàṣán fún ẹ̀yìn àwọn aṣiwèrè.
Maherithia maigĩirwo anyũrũrania, nacio iboko ikaigĩrwo mĩgongo ya andũ arĩa akĩĩgu.

< Proverbs 19 >