< Philippians 4 >

1 Nítorí náà ẹ̀yin ará mi olùfẹ́, ti mo sì ń ṣàfẹ́rí gidigidi, ayọ̀ àti adé mi, ẹ dúró ṣinṣin bẹ́ẹ̀ nínú Olúwa, ẹ̀yin olùfẹ́ mi.
Bhaya bhatikondenebhane, amwe nembagene, mshiyenetaji yane. Emeleli sawasawa Hwagosi, enyi bhamanyanibhembagena.
2 Èmi ń bẹ̀ Euodia, mo sì ń bẹ Sintike, kí wọn ní inú kan náà nínú Olúwa.
Ehubhozya Eudia, nantele ehubhozya awe Sintike, muwezye olwovwana olwinza kati yenyu. Afataneje amwe mwentibhabhele mwagenenogosi.
3 Mo sì bẹ̀ yin pẹ̀lú bí alájọru àjàgà mi tòótọ́, ran àwọn obìnrin wọ̀nyí lọ́wọ́, nítorí wọn bá mi ṣiṣẹ́ pọ̀ ní ìfẹ̀gbẹ́-kẹ̀gbẹ́ nínú ìyìnrere, àti Klementi pẹ̀lú, àti àwọn olùbáṣiṣẹ́ mi yòókù pẹ̀lú, orúkọ àwọn tí ń bẹ nínú ìwé ìyè.
Nantele embabhozye nantele amwemwabhomba mbombo bhamwetu mbhavwe ebha abhashe afataneje bhatumishe pandwemo nane. Ayanje izu lya Gosi natili no Kelementi, pandwemo na atumwa abhamwabho abhagosi abhene, amatawagao gandiwhemshitabu eshewhomi.
4 Ẹ máa yọ̀ nínú Olúwa nígbà gbogbo: mo sì tún wí pé. Ẹ máa yọ̀.
Whangosi ensiku zyonti. nantele embayanje, olusongwo.
5 Ẹ jẹ́ ki ìpamọ́ra yín di mímọ́ fún gbogbo ènìyàn, Olúwa ń bẹ nítòsí.
Ohogowenyu bhubhonehaja hwa bhantu bhonti Ogosi alipepe.
6 Ẹ má ṣe ṣe àníyàn ohunkóhun; ṣùgbọ́n nínú ohun gbogbo, nípa àdúrà àti ẹ̀bẹ̀ pẹ̀lú ìdúpẹ́, ẹ máa fi ìbéèrè yín hàn fún Ọlọ́run.
Ogande whianzye whijambo lyolyonti. Gamwhanza agenyu gabhonehanaje bha Ngolobhe.
7 Àti àlàáfíà Ọlọ́run, tí ó ju ìmòye gbogbo lọ, yóò pa ọkàn àti èrò yín mọ nínú Kristi Jesu.
Olweteho lwa Gosi, lwalulilugosi ashile enjele zyonti ebhazije amoyo nensebho zyenyu olwa lwa Kristi o Yesu.
8 Ní àkótán, ará, ohunkóhun tí í ṣe òtítọ́, ohunkóhun tí í ṣe ọ̀wọ̀, ohunkóhun tí í ṣe títọ́ ohunkóhun tí í ṣe mímọ́, ohunkóhun tí í ṣe fífẹ́, ohunkóhun tí ó ni ìròyìn rere, bí ìwà títọ́ kan bá wà, bí ìyìn kan bá sì wà, ẹ máa gba nǹkan wọ̀nyí rò.
Bhayu bhaholo bhane gasebhelelaji amambo gonti egelyoli, olwiho, ehaki, nowinza, uligano, nagala, aminza, gonti, galiminza, nagala, gagawanziwa, asalifye.
9 Àwọn nǹkan tí ẹ̀yin ti kọ́, tí ẹ̀yin sì ti gbà, tí ẹ̀yin sì ti gbọ́, tí ẹ̀yin sì ti rí lọ́wọ́ mi, ẹ máa ṣe wọ́n: Ọlọ́run àlàáfíà yóò sì wà pẹ̀lú yín.
Gabhombelelaji embombo gala gamwamanjilaga gamwaposheyega mwahovwaganagalagamwa wetu oweminza abhabhenamwe.
10 Èmi yọ̀ gidigidi nínú Olúwa pé, nísinsin yìí, ẹ̀yin tún ti sọjí nínú àníyàn ọkàn yín sí mi, nítòótọ́ ọkàn yín ń fàmọ́ mi ṣùgbọ́n ẹ kò ní àǹfààní tó.
Endinoluseshelo ogosi sana hulimwe na wagosi afwataneje amwe mbhonesezye eniya yahwihusizye hulimwe eyemahitaji gane. Lioli epoimande mwagene ansajile humaitajigane engawa semwayajile enafasi eyansaidile.
11 Kì í ṣe pé èmi ń sọ nítorí àìní: nítorí pé ni ipòkípò tí mo bá wà, mo tí kọ́ láti ní ìtẹ́lọ́rùn nínú rẹ̀.
Seyanga eshoaje ehwipe ahantu wavilavye hwanzaane ehwimazizye ayeehaliyonti.
12 Mo mọ̀ ohun tí o jẹ láti wa nínú àìní, mo sì mọ ohun tí ó jẹ láti ni lọ́pọ̀lọ́pọ̀. Nínú ohunkóhun àti nínú ohun gbogbo mo ti kọ́ àṣírí láti máa jẹ́ àjẹyó tàbí láti wà ni àìjẹun, láti máa ni ànító àti láti ṣe aláìní.
Emenye eshakhale nehali eyapongeshelwe naehali ya bhene vintu, humazingila gonti ega ane emanyie wakati owakute no wakatiowahweshe, yani vinji vyehwanziwa.
13 Èmi le ṣe ohun gbogbo nínú Kristi ẹni ti ń fi agbára fún mi.
Embwezizye abhombe ega ahwaviliwe nomwene yampela enguvu.
14 Ṣùgbọ́n ẹ̀yin ṣeun gidigidi ní ti pé ẹ̀yin ṣe alábápín nínú ìpọ́njú mi.
Hata esho, mwabhombile shinza ashilikiane nane amalabhagane.
15 Ẹ̀yin pàápàá sì mọ̀ pẹ̀lú, ẹ̀yin ará Filipi, pé ni ìbẹ̀rẹ̀ ìyìnrere, nígbà tí mo kúrò ni Makedonia, kò sí ìjọ kan ti ó bá mi ń ṣe alábápín ní ti gbígbà àti fífún ni, bí kò ṣe ẹ̀yin nìkan ṣoṣo.
Amwe mwa Filipi mmenye aje ahwandilekwizu nehasogoye hu Makedonia, nalimo ikanisa lyalya navwizye humambo gagahusu apeli inaposhele, amwe mbhene.
16 Nítorí ní Tẹsalonika ẹ̀yin fi nǹkan ránṣẹ́, lẹ́ẹ̀kan fún àìní mi.
Hata nehali hu thesolanike amwe mwantumie awavwohahinji humahitaji gane.
17 Kì í ṣe nítorí ti èmi ń fẹ́ ẹ̀bùn náà, ṣùgbọ́n èmi ń fẹ́ èso ti yóò máa di púpọ̀ nítorí yín.
Seyangaje ehwanza evyewene eyanga aji enyinza zyazileta efaida hulimwe.
18 Ṣùgbọ́n mo ní ohun gbogbo, mo sì ti di púpọ̀, mo sì tún ni lọ́pọ̀lọ́pọ̀ nígbà ti mo tí gba nǹkan wọ̀nyí lọ́wọ́ Epafiroditu tí a ti rán wá láti lọ́dọ̀ yín, ọrẹ olóòórùn dídùn, ẹbọ ìtẹ́wọ́gbà, tì í ṣe inú dídùn gidigidi sí Ọlọ́run.
Eposheye evintu vyonti, neshi ememezewe ne vintu evyenje eviji. Emposheye evintu vyenyu afume wa Epafradito. Vintu vinza vyavinurishila shinza vyonti vihweteshelwa vyonti vye sadaka yehukhondela Ongolobhe.
19 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run mi yóò pèsè ní kíkún fún gbogbo àìní yín, gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ rẹ̀ nínú ògo nínú Kristi Jesu.
Kwesho Ongolobhe wane abhabha memie gamuwanza agenyu utajiri wautuntumi wakwe O Yesu Kristi.
20 Ṣùgbọ́n ògo ni fún Ọlọ́run àti Baba wa láé àti láéláé. Àmín. (aiōn g165)
Eshi hwa Ngolobhe nahwa Baba wetu obhenotuntumowawilana wila. Amina. (aiōn g165)
21 Ẹ kí olúkúlùkù ènìyàn mímọ́ nínú Kristi Jesu. Àwọn ará tí ó wà pẹ̀lú mi kí yín.
Endamhozyau zifishile kila yaputa wa Kristi o Yesu aganwe bhendi nabho epa bhabhalamha.
22 Gbogbo àwọn ènìyàn mímọ́ kí yín, pàápàá àwọn tí ń ṣe ti agbo ilé Kesari.
Nantele bhabhaputa bhontiepa bhabhalamha. Hasabhala ebheshikholo sha Kaisari.
23 Oore-ọ̀fẹ́ Jesu Kristi Olúwa wa, kí ó wà pẹ̀lú ẹ̀mí yín. Àmín.
Neshi eneema eyagosi wetu O Yesu Kristi ebhene na moyo genyu.

< Philippians 4 >