< Philippians 3 >

1 Ní àkótán ará, ẹ máa yọ̀ nínú Olúwa wa. Kì í ṣe ìnira fún mi láti kọ̀wé ohun kan náà sí yín, ṣùgbọ́n fún yín ó jẹ́ ohun ààbò.
Dalej mówiąc, bracia moi! radujcie się w Panu. Jedneż rzeczy wam pisać mnie nie mierzi, a wam jest bezpiecznie.
2 Ẹ kíyèsára lọ́dọ̀ àwọn ajá, ẹ kíyèsára lọ́dọ̀ àwọn oníṣẹ́ búburú, ẹ sì kíyèsára lọ́dọ̀ àwọn onílà.
Upatrujcie psy, upatrujcie złych robotników, upatrujcie rozerwanie.
3 Nítorí àwa ni onílà, tí ń sin Ọlọ́run nípa ti Ẹ̀mí, àwa sì ń ṣògo nínú Kristi Jesu, àwa kò sí ní ìgbẹ́kẹ̀lé nínú ẹran-ara.
Albowiem my jesteśmy obrzezaniem, którzy duchem służymy Bogu i chlubimy się w Chrystusie Jezusie, a w ciele nie ufamy.
4 Bí èmi tìkára mi pẹ̀lú ti ní ìgbẹ́kẹ̀lé nínú ara. Bí ẹnikẹ́ni bá rò pé òun ni ìgbẹ́kẹ̀lé nínú ara, tèmi tilẹ̀ pọ̀,
Aczci i ja w ciele mam ufanie; jeźli kto inszy zda się mieć ufanie w ciele, bardziej ja,
5 ẹni tí a kọ nílà ní ọjọ́ kẹjọ, láti inú kùkùté Israẹli wá, láti inú ẹ̀yà Benjamini, Heberu láti inú Heberu wá; nítorí, ní ti òfin Farisi ni èmi;
Obrzezany będąc ósmego dnia, z narodu Izraelskiego, z pokolenia Benjaminowego, Żyd z Żydów, według zakonu Faryzeusz;
6 ní ti ìtara, èmi ń ṣe inúnibíni sí ìjọ; ní ti òdodo tí ó wà nínú òfin, mo jẹ́ aláìlẹ́gàn.
Według gorliwości prześladowca kościoła, według sprawiedliwości onej, która jest z zakonu, będąc bez przygany.
7 Ṣùgbọ́n ohunkóhun tí ó ti jásí èrè fún mi, àwọn ni mo ti kà sí òfo nítorí Kristi.
Ale to, co mi było zyskiem, tom poczytał dla Chrystusa za szkodę.
8 Nítòótọ́ láìṣe àní àní mo sì ka ohun gbogbo sí òfo nítorí ìtayọ ìmọ̀ Kristi Jesu Olúwa mi; nítorí ẹni ti mo ti ṣòfò ohun gbogbo, mo si kà wọn sí ohun tí kò ní èrè, kí èmi lè jèrè Kristi,
Owszem i wszystko poczytam sobie za szkodę dla zacności znajomości Chrystusa Jezusa, Pana mojego, dla któregom wszystko utracił i mam to sobie za gnój, abym Chrystusa zyskał,
9 kí a sì lè bá mi nínú rẹ̀, láìní òdodo tí èmi tìkára mi, tí ó ti inú òfin wá, ṣùgbọ́n èyí tí ó ti inú ìgbàgbọ́ wá nínú Kristi, òdodo láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run nípasẹ̀ ìgbàgbọ́.
I był znaleziony w nim, nie mając sprawiedliwości mojej, tej która jest z zakonu, ale tę, która jest przez wiarę Chrystusową, to jest sprawiedliwość z Boga, która jest przez wiarę;
10 Èmi mọ̀ ọ́n, àti agbára àjíǹde rẹ̀, àti láti jẹ́ alábápín nínú ìyà rẹ̀ nígbà tí mo bá fi ara mọ́ ọn nínú ikú rẹ̀;
Żebym go poznał i moc zmartwychwstania jego, i społeczność ucierpienia jego, przykształtowany będąc śmierci jego,
11 nípasẹ̀ bẹ́ẹ̀ kí èmi lè ní àjíǹde kúrò nínú òkú.
Owabym jakimkolwiek sposobem doszedł do powstania z martwych.
12 Kì í ṣe pé ọwọ́ mi ti tẹ̀ ẹ́ ná, tàbí mo ti di pípé, ṣùgbọ́n èmi ń lépa sí i, bí ọwọ́ mi yóò lè tẹ èrè náà nítorí èyí tí a ti dì mímú pẹ̀lú, láti ọ̀dọ̀ Kristi Jesu wá.
Nie iżbym już uchwycił, albo już doskonałym był; ale ścigam, ażbym też uchwycił to, na com też od Chrystusa Jezusa uchwycony.
13 Ará, èmi kò kara mi sí ẹni ti ọwọ́ rẹ̀ ti tẹ̀ ẹ́ ná, ṣùgbọ́n ohun kan yìí ni èmi ń ṣe, èmi ń gbàgbé àwọn nǹkan tí ó ti kọjá. Lẹ́yìn náà mo ń nàgà wo àwọn nǹkan tí ó wà níwájú.
Bracia! jać o sobie nie rozumiem, żebym już uchwycił.
14 Èmi ń lépa láti dé òpin eré ìje náà fún èrè ìpè gíga Ọlọ́run nínú Kristi Jesu.
Ale jedno czynię, że tego, co za mną jest, zapamiętywając, a do tego się, co przede mną jest, spiesząc, bieżę do kresu ku zakładowi powołania onego Bożego, które jest z góry w Chrystusie Jezusie.
15 Nítorí náà, ẹ jẹ́ kí àwa tí a dàgbà nípa ti ẹ̀mí ni èrò yìí; bí ẹ̀yin bá sì ní èrò mìíràn nínú ohunkóhun, èyí náà pẹ̀lú ni Ọlọ́run yóò fihàn yín.
Ile tedy nas doskonałych, toż rozumiejmy; a jeźli co inaczej rozumiecie, i toć wam Bóg objawi.
16 Kìkì pé, ki a ma gbe ìgbé ayé gẹ́gẹ́ bi èyí ti a ri gba.
Wszakże w tem, czegośmy doszli, według jednegoż sznuru postępujmy i jednoż rozumiejmy.
17 Ará, ẹ jùmọ̀ ṣe àfarawé mi, ẹ ṣe àkíyèsí àwọn tí ń rìn bẹ́ẹ̀, àní bí ẹ ti ní wa fún àpẹẹrẹ.
Bądźcież wespół naśladowcami moimi, bracia! a upatrujcie tych, którzy tak chodzą, jako nas za wzór macie.
18 Nítorí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ní ń rìn, nípasẹ̀ àwọn ẹni tí mo ti ń wí fún yín nígbàkígbà, àní, tí mo sì ń sọkún bí mo ti ń wí fún yín nísinsin yìí, pé, ọ̀tá àgbélébùú Kristi ni wọ́n.
Albowiem wiele ich chodzi, o którychem wam często powiadał, a teraz i z płaczem mówię, iż są nieprzyjaciołmi krzyża Chrystusowego;
19 Ìgbẹ̀yìn wọn ni ìparun, ikùn wọn sì ni Ọlọ́run wọn, wọ́n sì ń ṣògo nínú ìtìjú wọn, àwọn ẹni tí ń tọ́jú ohun ti ayé.
Których koniec jest zatracenie, których Bóg jest brzuch, a chwała w hańbie ich, którzy się o rzeczy ziemskie starają.
20 Nítorí ìlú ìbílẹ̀ wá ń bẹ̀ ní ọ̀run, láti ibi ti àwa pẹ̀lú gbé ń fojúsọ́nà fún Olùgbàlà, Jesu Kristi Olúwa.
Aleć nasza rzeczpospolita jest w niebiesiech, skąd też zbawiciela oczekujemy, Pana Jezusa Chrystusa.
21 Ẹni tí yóò sọ ara ìrẹ̀lẹ̀ wa di ọ̀tún kí ó lè bá ara ògo rẹ̀ mu, nípa agbára tí ó mú kí ó ṣe é ṣe fún un láti tẹ orí ohun gbogbo bá fún ara rẹ̀.
Który przemieni ciało nasze podłe, aby się podobne stało chwalebnemu ciału jego, według skutecznej mocy, którą też wszystkie rzeczy sobie podbić może.

< Philippians 3 >