< Philippians 3 >

1 Ní àkótán ará, ẹ máa yọ̀ nínú Olúwa wa. Kì í ṣe ìnira fún mi láti kọ̀wé ohun kan náà sí yín, ṣùgbọ́n fún yín ó jẹ́ ohun ààbò.
ⲁ̅ⲦⲞ ⲖⲞⲒⲠⲞⲚ ⲚⲀⲤⲚⲎⲞⲨ ⲢⲀϢⲒ ϦⲈⲚⲠϬⲞⲒⲤ ⲚⲀⲒ ⲞⲚ ⲈⲤϦⲎⲦⲞⲨ ⲚⲰⲦⲈⲚ ⲚⲞⲨϬⲚⲀⲨ ⲘⲈⲚ ⲚⲎⲒ ⲀⲚ ⲠⲈ ⲞⲨⲦⲀϪⲢⲞ ⲚⲰⲦⲈⲚ ⲠⲈ.
2 Ẹ kíyèsára lọ́dọ̀ àwọn ajá, ẹ kíyèsára lọ́dọ̀ àwọn oníṣẹ́ búburú, ẹ sì kíyèsára lọ́dọ̀ àwọn onílà.
ⲃ̅ⲀⲚⲀⲨ ⲈⲚⲒⲞⲨϨⲰⲢ ⲀⲚⲀⲨ ⲈⲚⲒⲈⲢⲄⲀⲦⲎⲤ ⲈⲦϨⲰⲞⲨ ⲀⲚⲀⲨ ⲈⲠⲒϢⲰⲦ ⲚⲤⲈⲂⲒ.
3 Nítorí àwa ni onílà, tí ń sin Ọlọ́run nípa ti Ẹ̀mí, àwa sì ń ṣògo nínú Kristi Jesu, àwa kò sí ní ìgbẹ́kẹ̀lé nínú ẹran-ara.
ⲅ̅ⲀⲚⲞⲚ ⲄⲀⲢ ⲠⲈ ⲠⲒⲤⲈⲂⲒ ϦⲀ ⲚⲎ ⲈⲦϢⲈⲘϢⲒ ⲘⲠⲒⲠⲚⲈⲨⲘⲀⲚⲦⲈⲪⲚⲞⲨϮ ⲞⲨⲞϨ ⲈⲚϢⲞⲨϢⲞⲨ ⲘⲘⲞⲚ ϦⲈⲚⲠⲬⲢⲒⲤⲦⲞⲤ ⲒⲎⲤⲞⲨⲤ ⲞⲨⲞϨ ⲚⲀⲢⲈ ϨⲐⲎⲚ ⲬⲎ ϦⲈⲚⲦⲤⲀⲢⲜ ⲀⲚ.
4 Bí èmi tìkára mi pẹ̀lú ti ní ìgbẹ́kẹ̀lé nínú ara. Bí ẹnikẹ́ni bá rò pé òun ni ìgbẹ́kẹ̀lé nínú ara, tèmi tilẹ̀ pọ̀,
ⲇ̅ⲔⲈⲠⲈⲢ ⲀⲚⲞⲔ ⲞⲨⲞⲚ ⲚⲦⲎⲒ ⲘⲘⲀⲨ ⲚⲞⲨⲐⲰⲦ ⲚϨⲎⲦ ϦⲈⲚⲦⲤⲀⲢⲜ ⲞⲚ ⲒⲤϪⲈ ⲞⲨⲞⲚ ⲔⲈⲞⲨⲀⲒ ⲘⲈⲨⲒ ⲈⲬⲀϨⲐⲎϤ ϦⲈⲚⲦⲤⲀⲢⲜ ⲀⲚⲞⲔ ⲚϨⲞⲨⲞ ⲀⲚⲞⲔ
5 ẹni tí a kọ nílà ní ọjọ́ kẹjọ, láti inú kùkùté Israẹli wá, láti inú ẹ̀yà Benjamini, Heberu láti inú Heberu wá; nítorí, ní ti òfin Farisi ni èmi;
ⲉ̅ⲞⲨⲤⲈⲂⲒ ϦⲈⲚⲪⲘⲀϨⲎ ⲚⲈϨⲞⲞⲨ ⲈⲂⲞⲖ ϦⲈⲚⲠⲄⲈⲚⲞⲤ ⲘⲠⲒⲤⲖ ⲦⲪⲨⲖⲎ ⲘⲂⲈⲚⲒⲀⲘⲒⲚ ⲞⲨϨⲈⲂⲢⲈⲞⲤ ⲈⲂⲞⲖ ϦⲈⲚϨⲀⲚϨⲈⲂⲢⲈⲞⲤ ⲔⲀⲦⲀ ⲠⲒⲚⲞⲘⲞⲤ ⲀⲚⲞⲔ ⲞⲨⲪⲀⲢⲒⲤⲈⲞⲤ.
6 ní ti ìtara, èmi ń ṣe inúnibíni sí ìjọ; ní ti òdodo tí ó wà nínú òfin, mo jẹ́ aláìlẹ́gàn.
ⲋ̅ⲔⲀⲦⲀ ⲞⲨⲬⲞϨ ⲀⲒϬⲞϪⲒ ⲚⲤⲀϮⲈⲔⲔⲖⲎⲤⲒⲀ ⲔⲀⲦⲀ ϮⲘⲈⲐⲘⲎⲒ ⲈⲦϦⲈⲚ ⲠⲒⲚⲞⲘⲞⲤ ⲀⲒϢⲰⲠⲒ ⲈⲒⲞⲒ ⲚⲀⲦⲀⲢⲒⲔⲒ.
7 Ṣùgbọ́n ohunkóhun tí ó ti jásí èrè fún mi, àwọn ni mo ti kà sí òfo nítorí Kristi.
ⲍ̅ⲀⲖⲖⲀ ⲚⲎ ⲈⲚⲀⲨϢⲞⲠ ⲚⲎⲒ ⲈϨⲀⲚϨⲎⲞⲨ ⲚⲀⲒ ⲀⲒⲞⲠⲞⲨ ⲈⲢⲞⲒ ⲚⲞⲨⲞⲤⲒ ⲈⲐⲂⲈ ⲠⲬⲢⲒⲤⲦⲞⲤ.
8 Nítòótọ́ láìṣe àní àní mo sì ka ohun gbogbo sí òfo nítorí ìtayọ ìmọ̀ Kristi Jesu Olúwa mi; nítorí ẹni ti mo ti ṣòfò ohun gbogbo, mo si kà wọn sí ohun tí kò ní èrè, kí èmi lè jèrè Kristi,
ⲏ̅ⲀⲖⲖⲀ ⲘⲈⲚⲞⲨⲚⲄⲈ ϮⲰⲠ ⲘⲘⲰⲞⲨ ⲦⲎⲢⲞⲨ ⲈϨⲀⲚⲞⲤⲒ ⲈⲐⲂⲈ ⲠⲒϨⲞⲨⲞ ⲚⲦⲈⲠⲈⲘⲒ ⲚⲦⲈⲠⲬⲢⲒⲤⲦⲞⲤ ⲒⲎⲤⲞⲨⲤ ⲠⲀϬⲞⲒⲤ ⲪⲀⲒ ⲈⲦⲀⲒϮⲞⲤⲒ ⲚϨⲰⲂ ⲚⲒⲂⲈⲚ ⲈⲐⲂⲎⲦϤ ⲞⲨⲞϨ ϮⲰⲠ ⲘⲘⲰⲞⲨ ⲦⲎⲢⲞⲨ ⲈϨⲀⲚⲖⲈⲂϢ ϨⲒⲚⲀ ⲚⲦⲀϪⲈⲘϨⲎⲞⲨ ⲘⲠⲬⲢⲒⲤⲦⲞⲤ.
9 kí a sì lè bá mi nínú rẹ̀, láìní òdodo tí èmi tìkára mi, tí ó ti inú òfin wá, ṣùgbọ́n èyí tí ó ti inú ìgbàgbọ́ wá nínú Kristi, òdodo láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run nípasẹ̀ ìgbàgbọ́.
ⲑ̅ⲞⲨⲞϨ ⲚⲤⲈϪⲈⲘⲦ ⲚϦⲎⲦϤ ⲈⲤⲈⲚⲦⲞⲦ ⲀⲚ ⲚϪⲈⲦⲀⲘⲈⲐⲘⲎⲒ ϮⲈⲂⲞⲖ ϦⲈⲚⲠⲒⲚⲞⲘⲞⲤ ⲀⲖⲖⲀ ϮⲈⲂⲞⲖ ϦⲈⲚⲪⲚⲀϨϮ ⲘⲠⲬⲢⲒⲤⲦⲞⲤ ϮⲘⲈⲐⲘⲎⲒ ⲆⲈ ϮⲈⲂⲞⲖ ϦⲈⲚⲪⲚⲞⲨϮ ⲈϨⲢⲎⲒ ⲈϪⲈⲚ ⲪⲚⲀϨϮ
10 Èmi mọ̀ ọ́n, àti agbára àjíǹde rẹ̀, àti láti jẹ́ alábápín nínú ìyà rẹ̀ nígbà tí mo bá fi ara mọ́ ọn nínú ikú rẹ̀;
ⲓ̅ⲈⲐⲢⲒⲤⲞⲨⲰⲚϤ ⲚⲈⲘ ϮϪⲞⲘ ⲚⲦⲈⲦⲈϤⲀⲚⲀⲤⲦⲀⲤⲒⲤ ⲚⲈⲘ ϮⲘⲈⲦϢⲪⲎⲢ ⲚⲦⲈⲚⲈϤⲘⲔⲀϨ ⲈⲒϢⲒⲂϮ ⲘⲘⲞⲒ ⲚⲤⲘⲞⲦ ⲚⲈⲘ ⲠⲈϤⲘⲞⲨ.
11 nípasẹ̀ bẹ́ẹ̀ kí èmi lè ní àjíǹde kúrò nínú òkú.
ⲓ̅ⲁ̅ϪⲈ ⲀⲢⲎⲞⲨ ⲚⲦⲀϮⲘⲀϮ ⲈⲠⲦⲰⲚϤ ⲚⲚⲒⲢⲈϤⲘⲰⲞⲨⲦ
12 Kì í ṣe pé ọwọ́ mi ti tẹ̀ ẹ́ ná, tàbí mo ti di pípé, ṣùgbọ́n èmi ń lépa sí i, bí ọwọ́ mi yóò lè tẹ èrè náà nítorí èyí tí a ti dì mímú pẹ̀lú, láti ọ̀dọ̀ Kristi Jesu wá.
ⲓ̅ⲃ̅ⲞⲨⲬ ⲞⲦⲒ ϪⲈ ⲀⲒⲞⲨⲞ ⲈⲒϬⲒ ⲒⲈ ϨⲎⲆⲎ ⲀⲒϪⲰⲔ ⲈⲂⲞⲖ ϮϬⲞϪⲒ ⲆⲈ ϪⲈ ⲀⲢⲎⲞⲨ ⲚⲦⲀⲦⲀϨⲞ ϦⲈⲚⲪⲀⲒ ⲈⲦⲀⲨⲦⲀϨⲞⲒ ⲚϦⲎⲦϤ ⲈⲂⲞⲖ ϨⲒⲦⲈⲚ ⲒⲎⲤⲞⲨⲤ ⲠⲬⲢⲒⲤⲦⲞⲤ.
13 Ará, èmi kò kara mi sí ẹni ti ọwọ́ rẹ̀ ti tẹ̀ ẹ́ ná, ṣùgbọ́n ohun kan yìí ni èmi ń ṣe, èmi ń gbàgbé àwọn nǹkan tí ó ti kọjá. Lẹ́yìn náà mo ń nàgà wo àwọn nǹkan tí ó wà níwájú.
ⲓ̅ⲅ̅ⲚⲀⲤⲚⲎⲞⲨ ⲀⲚⲞⲔ ϮⲘⲈⲨⲒ ⲈⲢⲞⲒ ⲀⲚ ϪⲈ ⲀⲒⲞⲨⲰ ⲀⲒⲦⲀϨⲞ ⲞⲨⲀⲒ ⲆⲈ ⲈⲒⲒⲢⲒ ⲘⲈⲚ ⲘⲠⲰⲂϢ ⲚⲚⲀⲪⲀϨⲞⲨ ⲈⲒⲤⲰⲞⲨⲦⲈⲚ ⲆⲈ ⲘⲘⲞⲒ ⲈⲚⲀⲦϨⲎ.
14 Èmi ń lépa láti dé òpin eré ìje náà fún èrè ìpè gíga Ọlọ́run nínú Kristi Jesu.
ⲓ̅ⲇ̅ⲔⲀⲦⲀ ⲞⲨⲤⲞⲘⲤ ⲈⲂⲞⲖ ⲈⲒϬⲞϪⲒ ⲚⲤⲀⲠⲒⲂⲀⲒ ⲚⲦⲈⲠⲒⲐⲰϨⲈⲘ ⲈⲦⲈⲘⲠϢⲰⲒ ⲚⲦⲈⲪⲚⲞⲨϮ ⲈⲦϦⲈⲚ ⲠⲬⲢⲒⲤⲦⲞⲤ ⲒⲎⲤⲞⲨⲤ.
15 Nítorí náà, ẹ jẹ́ kí àwa tí a dàgbà nípa ti ẹ̀mí ni èrò yìí; bí ẹ̀yin bá sì ní èrò mìíràn nínú ohunkóhun, èyí náà pẹ̀lú ni Ọlọ́run yóò fihàn yín.
ⲓ̅ⲉ̅ⲞⲨⲞⲚ ⲚⲒⲂⲈⲚ ⲈⲦϪⲎⲔ ⲈⲂⲞⲖ ⲪⲀⲒ ⲘⲀⲢⲈϤⲘⲈⲨⲒ ⲈⲢⲞϤ ⲞⲨⲞϨ ⲒⲤϪⲈ ⲦⲈⲦⲈⲚⲘⲈⲨⲒ ⲈⲔⲈϨⲰⲂ ⲚⲔⲈⲢⲎϮ ⲠⲀⲒⲬⲈⲦ ⲈⲢⲈ ⲪⲚⲞⲨϮ ϬⲰⲢⲠϤ ⲚⲰⲦⲈⲚ ⲈⲂⲞⲖ.
16 Kìkì pé, ki a ma gbe ìgbé ayé gẹ́gẹ́ bi èyí ti a ri gba.
ⲓ̅ⲋ̅ⲠⲖⲎⲚ ⲪⲎ ⲈⲦⲀⲚⲪⲞϨ ϢⲀⲢⲞϤ ⲪⲀⲒ ⲘⲀⲢⲈⲚϮⲘⲀϮ ⲚϦⲎⲦϤ.
17 Ará, ẹ jùmọ̀ ṣe àfarawé mi, ẹ ṣe àkíyèsí àwọn tí ń rìn bẹ́ẹ̀, àní bí ẹ ti ní wa fún àpẹẹrẹ.
ⲓ̅ⲍ̅ϢⲰⲠⲒ ⲈⲢⲈⲦⲈⲚⲞⲒ ⲚϢⲪⲎⲢ ⲚⲒⲚⲒ ⲘⲘⲞⲒ ⲚⲀⲤⲚⲎⲞⲨ ⲞⲨⲞϨ ϪⲞⲨϢⲦ ⲈⲚⲎ ⲈⲐⲘⲞϢⲒ ⲘⲠⲀⲒⲢⲎϮ ⲔⲀⲦⲀ ⲪⲢⲎϮ ⲈⲦⲈⲚϢⲞⲠ ⲚⲰⲦⲈⲚ ⲚⲦⲨⲠⲞⲤ.
18 Nítorí ọ̀pọ̀lọpọ̀ ní ń rìn, nípasẹ̀ àwọn ẹni tí mo ti ń wí fún yín nígbàkígbà, àní, tí mo sì ń sọkún bí mo ti ń wí fún yín nísinsin yìí, pé, ọ̀tá àgbélébùú Kristi ni wọ́n.
ⲓ̅ⲏ̅ⲞⲨⲞⲚ ⲞⲨⲘⲎϢ ⲄⲀⲢ ⲀⲨⲘⲞϢⲒ ⲚⲀⲒ ⲈⲦⲀⲒϪⲞⲤ ⲚⲰⲦⲈⲚ ⲈⲐⲂⲎⲦⲞⲨ ⲚⲞⲨⲘⲎϢ ⲚⲤⲞⲠ ⲞⲨⲞϨ ϮⲚⲞⲨ ⲞⲚ ⲈⲒⲢⲒⲘⲒ ϮϪⲰ ⲘⲘⲞⲤ ⲚⲒϪⲀϪⲒ ⲚⲦⲈⲠⲒⲤⲦⲀⲨⲢⲞⲤ ⲚⲦⲈⲠⲬⲢⲒⲤⲦⲞⲤ.
19 Ìgbẹ̀yìn wọn ni ìparun, ikùn wọn sì ni Ọlọ́run wọn, wọ́n sì ń ṣògo nínú ìtìjú wọn, àwọn ẹni tí ń tọ́jú ohun ti ayé.
ⲓ̅ⲑ̅ⲚⲀⲒ ⲈⲦⲈ ⲦⲞⲨϦⲀⲈ ⲠⲈ ⲠⲦⲀⲔⲞ ⲚⲀⲒ ⲈⲦⲈ ⲠⲞⲨⲚⲞⲨϮ ⲠⲈ ⲦⲞⲨⲚⲈϪⲒ ⲞⲨⲞϨ ⲠⲞⲨⲰⲞⲨ ⲀϤϦⲈⲚ ⲞⲨϢⲒⲠⲒ ⲚⲀⲒ ⲈⲐⲘⲈⲨⲒ ⲈⲚⲀ ⲠⲔⲀϨⲒ.
20 Nítorí ìlú ìbílẹ̀ wá ń bẹ̀ ní ọ̀run, láti ibi ti àwa pẹ̀lú gbé ń fojúsọ́nà fún Olùgbàlà, Jesu Kristi Olúwa.
ⲕ̅ⲦⲈⲚⲘⲈⲦⲢⲈⲘⲘⲂⲀⲔⲒ ⲄⲀⲢ ⲀⲚⲞⲚ ⲀⲤϢⲞⲠ ϦⲈⲚⲚⲒⲪⲎⲞⲨⲒ ⲞⲨⲞϨ ⲈⲂⲞⲖ ⲘⲘⲀⲨ ⲦⲈⲚϪⲞⲨϢⲦ ϦⲀⲦϨⲎ ⲘⲠⲈⲚⲤⲰⲦⲎⲢ ⲠⲈⲚϬⲞⲒⲤ ⲒⲎⲤⲞⲨⲤ ⲠⲬⲢⲒⲤⲦⲞⲤ.
21 Ẹni tí yóò sọ ara ìrẹ̀lẹ̀ wa di ọ̀tún kí ó lè bá ara ògo rẹ̀ mu, nípa agbára tí ó mú kí ó ṣe é ṣe fún un láti tẹ orí ohun gbogbo bá fún ara rẹ̀.
ⲕ̅ⲁ̅ⲪⲎ ⲈⲐⲚⲀϢⲒⲂϮ ⲘⲠⲤⲰⲘⲀ ⲚⲦⲈⲠⲈⲚⲐⲈⲂⲒⲞ ⲚϢⲪⲎⲢ ⲘⲘⲞⲢⲪⲎ ⲚⲦⲈⲠⲤⲰⲘⲀ ⲚⲦⲈⲠⲈϤⲰⲞⲨ ⲔⲀⲦⲀ ⲠⲒⲈⲢϨⲰⲂ ⲈⲐⲢⲈϤϪⲈⲘϪⲞⲘ ⲞⲨⲞϨ ⲈⲐⲢⲈϤⲈⲢ ϨⲰⲂ ⲚⲒⲂⲈⲚ ϬⲚⲈϪⲰⲞⲨ ⲚⲀϤ.

< Philippians 3 >