< Philippians 2 >
1 Bí ìwọ bá ní ìmúlọ́kànle nítorí pé ìwọ wà ní ìṣọ̀kan pẹ̀lú Kristi, bi ìtùnú kan bá wà nínú ìfẹ́ rẹ̀, bí ìdàpọ̀ Ẹ̀mí kan bá wà, bí ìyọ́nú àti ìṣeun bá wà,
Nkashile huheli apewe umwoyo nu Kristu. Nkashile luweli olusobhezyo lufuma mlugano lwakwe. Nkashile uhweli ulubhongano lwa Opepo.
2 síbẹ̀ ẹ mú ayọ̀ mi kún nínú ìṣọ̀kan yín, nípa ìfẹ́ kan náà, wíwà ní ẹ̀mí kan náà àti ète kan náà.
Malelezi ulusovyo lwane mbhaje pandwemo mbhanje nulugano lumo, nkambha pandwemo opepo, nabhenembombo emo.
3 Ẹ má ṣe ohunkóhun nínú ìlépa ara tàbí ògo asán, ṣùgbọ́n ní ìrẹ̀lẹ̀ ọkàn kí olúkúlùkù ro àwọn ẹlòmíràn sí ẹni ti ó sàn ju òun lọ.
Ugaje owombe umwene nahwilole. Mubhanje bhahwiyisye nkawabhalola abhanje huje bhinza ashile awe.
4 Kí olúkúlùkù yín má ṣe ro ohun ti ara rẹ̀ nìkan, ṣùgbọ́n ti ẹlòmíràn pẹ̀lú.
Omtu aagje wenye amambo gakwe yuyo ayenyaje na aga bhanje.
5 Nínú ìbáṣepọ̀ yin pẹ̀lú àwọn ẹlòmíràn, ẹ ni irú ìlépa ọkàn náà bí ti Kristi Jesu.
Mubhaje numwoyo nashi Kristi u Yesu.
6 Ẹni tí, bí o tilẹ̀ jẹ́ ìrísí Ọlọ́run, kò kà á sí ohun tí ìbá fi ìwọra gbámú láti bá Ọlọ́run dọ́gba.
Umwene alisawa nu Ngolobhe sagahwibheshele huje sawa nu Ngolobhe hatu ahakhatane naho.
7 Ṣùgbọ́n ó bọ́ ògo rẹ̀ sílẹ̀, ó sì mú àwọ̀ ìránṣẹ́, a sì ṣe é ni àwòrán ènìyàn.
Lakini umwene abhiyisizye yuyo. Ahejile ubeleogwa hwitume ahwibhonesezye pamaso gabhantu. Abhoneshe mwanadamu.
8 Ó sì wà ní àwòrán ènìyàn, ó rẹ ara rẹ̀ sílẹ̀, o sì tẹríba títí de ojú ikú, àní ikú lórí àgbélébùú.
Umwene abhiyisizye nashi ikwii abhale afye afye pashihobhehanyo.
9 Nítorí náà, Ọlọ́run ti gbé e ga sí ipele tí ó ga jùlọ, ó sì ti fi orúkọ kan ti ó borí gbogbo orúkọ fún un,
Pepo Ungolobhe asukyezye haanu. Apiye itawa igosi ashile amatawa goti.
10 pé ni orúkọ Jesu ni kí gbogbo eékún máa wólẹ̀, ní ọ̀run, àti ní orí ilẹ̀ ayé àti ní ìsàlẹ̀ ilẹ̀ ayé,
Abhombile goti hwitawa ilya Yesu kila lifugamo lifungamile. Amafugamo gabhantu abha humwanya na bhabhali pamwanya pansi na bhabhali bhilongo pasi.
11 àti pé kí gbogbo ahọ́n jẹ́wọ́ pé, Jesu Kristi ni Olúwa, fún ògo Ọlọ́run Baba.
Abhombile engo huje umele guyaje U Yesu Kilisti yugonsi nusisya owa Ngolobhe nu daada.
12 Nítorí náà ẹ̀yin ará mi, gẹ́gẹ́ bí ẹ̀yin ti ń gbọ́rọ̀ nígbà gbogbo, kì í ṣe nígbà ti mo wà lọ́dọ̀ yín nìkan, ṣùgbọ́n pàápàá nísinsin yìí tí èmi kò sí ni àárín yín, ẹ máa ṣiṣẹ́ ìgbàlà yín yọrí pẹ̀lú ìbẹ̀rù àti ìwárìrì,
Hwahuje bhamwetu bhane nashisamhwina esinku zyosagahuje pewendi hata pendinomo bhombaji owaule wenyu mwemwe uwoga nayinganishe.
13 nítorí pé Ọlọ́run ni ó n ṣiṣẹ́ nínú yín, láti fẹ́ àti láti ṣiṣẹ́ fún ète rere rẹ̀.
Hwahuje Ongolobhe abhomba embombo mhati yenyu abhapela amaha agabhombele imbombo gala gasongwa umwene.
14 Ẹ máa ṣe ohun gbogbo láìsí ìkùnsínú àti ìjiyàn.
Hwombaji embombo zyonti wala mgaje munjunishe wala abwazanye.
15 Kí ẹ̀yin lè jẹ́ aláìlẹ́gàn àti oníwà mímọ́, ọmọ Ọlọ́run, aláìlábàwọ́n, láàrín oníwà wíwọ́ àti alárékérekè orílẹ̀-èdè láàrín àwọn ẹni tí a ń rí yín bí ìmọ́lẹ̀ ní ayé.
Hwombaji shesho huje mgajeligwe na mlibhana bha Ngolobhe. Usengerusu wasagali ni mbibhi bhombaji ego mubhanje lukhozwo pansi epapo eyamabhibhi na mabhibhi.
16 Bí ẹ sì ṣe di ọ̀rọ̀ ìyè mú gírígírí, kí èmi lè ṣògo ni ọjọ́ Kristi pé èmi kò sáré lásán, bẹ́ẹ̀ ni èmi kò sì ṣe làálàá lásán.
Khataji sana amazyi ega agewomi hujeembe wazo bhezewe isiku elya Kilisti embamanye huje sagananyilile wene saga na bhombile embombo wenu.
17 Ṣùgbọ́n, bí a tilẹ̀ ń dà mí bí ọtí-ìrúbọ sórí ẹbọ iṣẹ́ ìsìn ìgbàgbọ́ yín, inú mi dùn, mo sì ń bá gbogbo yín yọ̀ pẹ̀lú.
Mmenye huje bhantufya nashi esadaka pamwanya ye dhabihu nembombo eye lweteho esogwa naesogwele pandwemo namwe mwenti.
18 Bákan náà ni kí ẹ̀yin máa yọ̀, kí ẹ sì máa bá mi yọ̀ pẹ̀lú.
Pepapepa namwe msogwelwe natele msogwele pandwemo nane.
19 Mo ni ìrètí nínú Jesu Olúwa, láti rán Timotiu sí yín ni àìpẹ́ yìí, kí èmi pẹ̀lú lè ni ìfọ̀kànbalẹ̀ nígbà tí mo bá gbúròó yín.
Ane itegemela hwa Gosi uYesu ehulanyizya hwa Timotheo hulimwi sheshi apepepe ewazahuje mpelee nane umwoyo nanaiaamanya amambo genyu.
20 Nítorí èmi kò ni ẹlòmíràn tí ó dàbí rẹ̀, tí yóò máa fi tinútinú ṣe àníyàn yín.
Hwa huje sendinuwamwabho uwawenye nashi umwene walinilyoli sababu yenyu.
21 Nítorí gbogbo wọn ni ó tọ́jú nǹkan ti ara wọn, kì í ṣe àwọn nǹkan ti Jesu Kristi.
Abhanje bhonti bhanagaga embatume abhene bhahwanza embombo zyabho ezyavene wene, nasagazyahuje zya abhombe embombo eye Yesu Kilisti.
22 Ṣùgbọ́n ẹ̀yin mọ̀ pé Timotiu pegedé, gẹ́gẹ́ bí ọmọ lọ́dọ̀ baba rẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni ó sì ti ń bá mi ṣiṣẹ́ pọ̀, nínú iṣẹ́ ìyìnrere.
Hwa huje mmenye egharama zyakwe, nashu umwana walelwa nuishe wakwe papepo pahwombile embombo pandwemo nane alumbelele.
23 Nítorí náà, mo ní ìrètí láti rán sí yín ní àìpẹ́ tí mo bá wòye bí yóò ti rí fún mi.
Hwahuje esobheye hutume halaka hulimwi ilikemanye henu habhafumile hulini.
24 Ṣùgbọ́n mo ní gbẹ́kẹ̀lé nínú Olúwa, pé èmi tìkára mi pẹ̀lú yóò wá ní àìpẹ́.
Hwahuje endinuhakika hwitawa lya Gosi huje embahweze nene naihweza papapepe.
25 Mo kà á sí pé n kò lè ṣàìrán Epafiroditu arákùnrin mi sí yín, àti olùbáṣiṣẹ́ pọ̀ mi, àti ọmọ-ogun ẹlẹgbẹ́ mi, ìránṣẹ́ yín pẹ̀lú, tí ẹ rán láti ṣè ránṣẹ́ fún mi nínú àìní mi.
Endihwendala ewaziwa hugalusije hulimwi Epafradito. Umwene holo wane nantele bhomba mbombo tenti nane, naskari wamwetu umwene tumwa nantele puti wenyu kwajili ya vintu evyalini.
26 Nítorí tí ọkàn rẹ̀ fà sí gbogbo yín, ó sì kún fún ìbànújẹ́, nítorí tí ẹ̀yin gbọ́ pé ó ṣe àìsàn.
Alinowoga agene huje abhepandwemo namwe mweti hwahuje ahovyezye wamwabho huje bhinu.
27 Nítòótọ́ ni ó ti ṣe àìsàn títí dé ojú ikú, ṣùgbọ́n Ọlọ́run ti ṣàánú fún un; kì í sì í ṣe fún òun nìkan, ṣùgbọ́n fún èmi pẹ̀lú kí èmi má ṣe ni ìbànújẹ́ lórí ìbànújẹ́.
Maana lyoli alibhinu shesho apululie afye. Lakini Ongolobhe asanjile ni pwana lyakwe hagali pamwanya yakwe. Umwene alipamwanya yane hwahuje ansibhe nahwisanje na hwisanje.
28 Nítorí náà ni mo ṣe ní ìtara láti rán an, pé nígbà tí ẹ̀yin bá sì tún rí i, kí ẹ̀yin lè yọ̀ àti kí ìkáyà sókè mi lè dínkù.
Hwa huje hehugalusya ninali amwenye lyaliwezeha na huje pamvahulele mwasogwe nana embave enefizye esebho.
29 Nítorí náà, ẹ fi ayọ̀ púpọ̀ gbà á nínú Olúwa; kí ẹ sì máa bu ọlá fún irú àwọn ẹni bẹ́ẹ̀.
Zobhelaji u Epafradito hwidal lya Gosi sogwanji huwiza woti muhwiyishaje hwa mtu nashioyo.
30 Nítorí iṣẹ́ Kristi ni ó ṣe súnmọ́ ẹnu-ọ̀nà ikú, tí ó sì fi ẹ̀mí ara rẹ̀ wéwu, láti mu àìtó iṣẹ́ ìsìn yín sí mi kún.
Hwa huje alimbombo ezya Kristi apalamiye aafye apululilye amaisha gakwe sababu yawamwabha avombele amambo asaga waile ahwombe mmbombo nashieyo numo wowoti wahwombile nashioyo hutali nane.