< Obadiah 1 >

1 Ìran ti Obadiah. Èyí ni Olúwa Olódùmarè wí nípa Edomu. Àwa ti gbọ́ ohùn kan láti ọ̀dọ̀ Olúwa wá, a sì ti rán ikọ̀ kan sí gbogbo kèfèrí láti sọ pé, “Ẹ dìde, ẹ jẹ́ kí a dìde ogun sí i.”
Obadiah ni a hmu e kamnuenae: Bawipa Jehovah ni Edom ram hanelah a dei e lawk teh, BAWIPA e hram lawk teh maimouh ni thai awh toe. Nangmouh thaw awh nateh Edom ram tuk hanelah cet awh leih titeh Jentelnaw koe laicei a patoun toe.
2 “Kíyèsi i, Èmi yóò sọ ọ́ di kékeré láàrín àwọn kèfèrí; ìwọ yóò sì di gígàn lọ́pọ̀lọ́pọ̀.
Nang teh Jentelnaw e hmalah kathoengca lah na ta, Jentelnaw ni na hnephnap awh han.
3 Ìgbéraga àyà rẹ ti tàn ọ́ jẹ, ìwọ tí ń gbé inú pálapàla àpáta, tí o sì kọ́ ibùgbé rẹ sí ibi gíga, ìwọ wí nínú ọkàn rẹ pé, ‘Ta ni yóò mú mi sọ̀kalẹ̀?’
Talungnaw rahak vah na o teh, kai hah apini nama talai na ka pabawt thai han vâ na ti dawkvah na kâoupnae ni na dum toe.
4 Bí ìwọ tilẹ̀ gbé ara rẹ ga bí ẹyẹ idì, bí ìwọ tilẹ̀ tẹ́ ìtẹ́ rẹ sí àárín àwọn ìràwọ̀, láti ibẹ̀ ni èmi yóò ti sọ̀ ọ kalẹ̀,” ni Olúwa wí.
Nang teh langta patetlah na kâtawm teh âsinaw dawk tabu na ka tuk nakunghai, hote hmuen koehoi kai ni nang hah na pabo han telah BAWIPA ni a ti.
5 “Bí àwọn olè tọ̀ ọ́ wá, bí àwọn ọlọ́ṣà ní òru, Háà! Irú ìparun wo ló dúró dè ọ́, wọn kò ha jalè tó bí wọ́n ti fẹ́? Bí àwọn tí ń ká èso àjàrà tọ̀ ọ́ wá, wọn kò ha ni fi èso àjàrà díẹ̀ sílẹ̀?
Tamrunaw hoi dingcanaw ni karum vah tho awh pawiteh, amamouh ngai e duengdoeh parawt awh tih. Misur paw ka khi e ni hai youn touh teh ouk a pâhma nahoehmaw.
6 Báwo ni a ṣe ṣe àwárí nǹkan Esau, tí a sì wá ohun ìní ìkọ̀kọ̀ rẹ̀ jáde.
Nang teh puenghoi na kamko toe. Esaw teh puenghoi akungkhei awh toe. A hro e hnonaw teh ngit a pâphue awh toe.
7 Gbogbo àwọn ẹni ìmùlẹ̀ rẹ ti mú ọ dé ìpẹ̀kun ilẹ̀ rẹ, àwọn ọ̀rẹ́ rẹ ti tàn ọ́ jẹ, wọ́n sì ti borí rẹ; àwọn tó jẹ oúnjẹ rẹ dẹ pàkúté dè ọ́, ṣùgbọ́n ìwọ kò ní ní òye rẹ̀.”
Nang hoi kamyawng e naw pueng teh ram alawilah pâlei lah ao awh toe. Na huinaw pueng ni na dum awh toe. Nang hoi rei kacatnetnaw ni, nang hanelah tangkam a patung awh toe. Na thoumnae abaw toe.
8 Olúwa wí pé, “Ní ọjọ́ náà, Èmi kì yóò ha pa àwọn ọlọ́gbọ́n Edomu run, àti àwọn amòye run kúrò ní òkè Esau?
BAWIPA ni a dei e teh hatnae hnin dawkvah Edom ram thung e lungkaangnaw thoseh, Esaw e mon dawk hoi a ratho kahawinaw thoseh ka takhoe han.
9 A ó ṣe ẹ̀rù ba àwọn jagunjagun rẹ, ìwọ Temani, gbogbo àwọn tó wà ní orí òkè Esau ní a ó gé kúrò nínú ìpànìyàn náà.
Oe Teman kho, na ransanaw ni a taki awh han. Esaw e mon dawk tami pueng a thei awh han.
10 Nítorí ìwà ipá sí Jakọbu arákùnrin rẹ, ìtìjú yóò bò ọ, a ó sì pa ọ run títí láé.
Nang teh na nawngha Jakop na theinae, thama lah na sak e yon kecu dawkvah, yeirai na phawt vaiteh nang teh khoeroe takhoe lah na o han.
11 Ní ọjọ́ tí ìwọ dúró ní apá kan, ní ọjọ́ tí àlejò kó ogún rẹ lọ, tí àwọn àjèjì sì wọ ibodè rẹ, tí wọ́n sì sẹ́ kèké lórí Jerusalẹmu, ìwọ náà wà bí ọ̀kan nínú wọn.
Nang teh avanglah na onae hnin, ramlouknaw ni nange thaw katawkkungnaw mannae hnin, alouke miphunnaw ni ahnie khopui longkha thung a kâen teh Jerusalem khopui hah cungpam rayunae hnin nah nang teh dâw e tami lah na o.
12 Ìwọ kì bá tí fi ojú kéré arákùnrin rẹ, ní àkókò ìbànújẹ́ rẹ̀ ìwọ kì bá tí yọ̀ lórí àwọn ọmọ Juda, ní ọjọ́ ìparun wọn ìwọ kì bá tí gbéraga púpọ̀ ní ọjọ́ wàhálà wọn.
Na nawngha teh ramlouk e tami lah a onae tueng nah laplap na khet kawi na hoeh. Judahnaw rawknae a kâhmo nah na kâoup sin mahoeh. Runae a kâhmo navah, dudamnae lawk na dei kawi nahoeh.
13 Ìwọ kì bá tí wọ inú ibodè àwọn ènìyàn mi lọ, ní ọjọ́ àjálù wọn. Ìwọ kì bá tí fojú kó wọn mọ́lẹ̀ nínú ìdààmú wọn, ní ọjọ́ àjálù wọn. Ìwọ kì bá tí jí ẹrù wọn kó, ní ọjọ́ ìpọ́njú wọn.
Ka taminaw runae a kâhmo nah, a longkha thung kâen kawi na hoeh, a roedeng nah laplap khet kawi na hoeh, a hnopai hai lawp kawi na hoeh.
14 Ìwọ kì bá tí dúró ní ìkóríta ọ̀nà láti ké àwọn tirẹ̀ tó ti sálà kúrò. Ìwọ kì bá tí fa àwọn tó ṣẹ́kù nínú wọn lélẹ̀ ní ọjọ́ wàhálà wọn.
Kahlout e taminaw ngang hanlah lamkâcunae koe kangdue kawi na hoeh. Runae a kâhmo nah a tarannaw kut dawk thak kawi na hoeh.
15 “Nítorí ọjọ́ Olúwa súnmọ́ etílé lórí gbogbo àwọn kèfèrí. Bí ìwọ ti ṣe, bẹ́ẹ̀ ni a ó ṣe sí ìwọ náà; ẹ̀san rẹ yóò sì yípadà sí orí ara rẹ.
Bangkongtetpawiteh, BAWIPA e hnin teh miphun pueng hoi a hnai toe. Na sak e patetlah ayâ ni nang koe a sak van han. Na sak e hno na lû van a pha han.
16 Gẹ́gẹ́ bí ìwọ̀ ṣe mu lórí òkè mímọ́ mi, bẹ́ẹ̀ ni gbogbo kèfèrí yóò máa mu títí; wọn yóò mu ún ní àmutẹ́rùn wọn yóò sì wà bí ẹni pé wọn kò mu ún rí.
Judah miphunnaw ni, kaie mon kathoung dawk a canei e patetlah tengpam kaawm e miphunnaw pueng ni a canei awh han. A canei awh vaiteh a padoun awh toteh kaawm boihoeh e tami patetlah ao han.
17 Ṣùgbọ́n ìgbàlà yóò wà lórí òkè Sioni, wọn yóò sì jẹ́ mímọ́, àti ilé Jakọbu yóò sì ní ìní wọn.
Zion mon dawk ka hlout e youn touh ao han. Thoungnae hmuen lah ao han. Jakop miphun ni a coe han kamcu e talai bout a coe awh han.
18 Ilé Jakọbu yóò sì jẹ́ iná àti ilé Josẹfu ọwọ́ iná ilé Esau yóò jẹ àgékù koríko wọn yóò fi iná sí i, wọn yóò jo run. Kì yóò sí ẹni tí yóò kù ní ilé Esau.” Nítorí Olúwa ti sọ̀rọ̀.
Jakop miphun teh hmai, Joseph miphun teh hmaito, Esaw miphun teh songnawng lah ao. Hmai hoi sawi toteh be a kak awh han. Esaw miphun hlout awh mahoeh telah BAWIPA ni a dei toe.
19 Àwọn ará gúúsù yóò ni òkè Esau, àwọn ará ẹsẹ̀ òkè yóò ni ilẹ̀ àwọn ará Filistini ní ìní. Wọn yóò sì ni oko Efraimu àti Samaria; Benjamini yóò ní Gileadi ní ìní.
Akalah kaawm e naw ni Esaw e mon hai thoseh, tanghling dawk kaawm e naw ni Filistin ram hai thoseh, Ephraim yawn hoi samaria ram hai thoseh, Benjamin miphun ni Gilead ram hai thoseh a tuk han.
20 Àwọn ìgbèkùn Israẹli tí ó wà ní Kenaani yóò ni ilẹ̀ títí dé Sarefati; àwọn ìgbèkùn láti Jerusalẹmu tí ó wà ní Sefaredi yóò ni àwọn ìlú gúúsù ní ìní.
Kanaannaw koe kaawm e, man e Isarel miphunnaw ni Zarephath totouh a coe awh han. Jerusalem hoi san lah a man awh teh Sepharad ram kaawm e naw ni akalae ram totouh a coe awh han.
21 Àwọn tó ń gba ni là yóò sì gòkè Sioni wá láti jẹ ọba lé orí àwọn òkè Esau. Ìjọba náà yóò sì jẹ́ ti Olúwa.
Esaw e mon lawkceng hanelah rungngangkungnaw teh, Zion mon dawk a luen awh han. A uknaeram haiyah BAWIPA e ram lah ao han.

< Obadiah 1 >