< Obadiah 1 >

1 Ìran ti Obadiah. Èyí ni Olúwa Olódùmarè wí nípa Edomu. Àwa ti gbọ́ ohùn kan láti ọ̀dọ̀ Olúwa wá, a sì ti rán ikọ̀ kan sí gbogbo kèfèrí láti sọ pé, “Ẹ dìde, ẹ jẹ́ kí a dìde ogun sí i.”
Ty aroñaro’ i Obadià: Hoe ty nafè’ Iehovà, Talè amy Edome: Nahajanjiñe entañe boak’ amy Iehovà zahay, le fa nampihitrifeñe amo kilakila’ ondatio ty sorotà, nanao ty hoe: Miongaha, antao hitroatse hihotakotake.
2 “Kíyèsi i, Èmi yóò sọ ọ́ di kékeré láàrín àwọn kèfèrí; ìwọ yóò sì di gígàn lọ́pọ̀lọ́pọ̀.
Inao te hafotsako ho kede amo fifeheañeo irehe; ho vata’e mavoeñe.
3 Ìgbéraga àyà rẹ ti tàn ọ́ jẹ, ìwọ tí ń gbé inú pálapàla àpáta, tí o sì kọ́ ibùgbé rẹ sí ibi gíga, ìwọ wí nínú ọkàn rẹ pé, ‘Ta ni yóò mú mi sọ̀kalẹ̀?’
Fa namañahy azo ty firengevohan’arofo’o, ihe mpimoneñe an-tseratseram-bato ao; an-kaboañe ey ty fimoneña’o ihe mitsakore ty hoe añ’arofo ao: Ia ty hanjotso ahy mb’an-tane mb’eo?
4 Bí ìwọ tilẹ̀ gbé ara rẹ ga bí ẹyẹ idì, bí ìwọ tilẹ̀ tẹ́ ìtẹ́ rẹ sí àárín àwọn ìràwọ̀, láti ibẹ̀ ni èmi yóò ti sọ̀ ọ kalẹ̀,” ni Olúwa wí.
Aa ndra t’ie mizonjoñe mb’añ’abo ey hirae’o am-bantio, naho ajado’o amo vasiañeo eñe ty akiba’o, mbe hazotsoko boak’ ey, hoe t’Iehovà.
5 “Bí àwọn olè tọ̀ ọ́ wá, bí àwọn ọlọ́ṣà ní òru, Háà! Irú ìparun wo ló dúró dè ọ́, wọn kò ha jalè tó bí wọ́n ti fẹ́? Bí àwọn tí ń ká èso àjàrà tọ̀ ọ́ wá, wọn kò ha ni fi èso àjàrà díẹ̀ sílẹ̀?
Ie nivotraha’ ty mpampikametse, naho ty malaso an-kaleñe — akore ty fandrotsahañe anahareo— tsy ho nampikametse am-para’ t’ie nietsake hao? Aa naho nivotrak’ ama’o ty mpanontoñe valoboke, tsy ho nenga’e hao ty ho tsindroheñe?
6 Báwo ni a ṣe ṣe àwárí nǹkan Esau, tí a sì wá ohun ìní ìkọ̀kọ̀ rẹ̀ jáde.
Akore ty fivolosañe i Esave, ty fikodebeañe o vara nakafi’eo.
7 Gbogbo àwọn ẹni ìmùlẹ̀ rẹ ti mú ọ dé ìpẹ̀kun ilẹ̀ rẹ, àwọn ọ̀rẹ́ rẹ ti tàn ọ́ jẹ, wọ́n sì ti borí rẹ; àwọn tó jẹ oúnjẹ rẹ dẹ pàkúté dè ọ́, ṣùgbọ́n ìwọ kò ní ní òye rẹ̀.”
Fa nanese azo pak’ añ’efe-tane eo o mpirimboñ’ ama’oo; nifañahie’ o nifampilongo ama’oo vaho nahagioke; fa nampipoke fandrik’ ambane’o ao o mpitrao-pikama ama’oo; (tsy ama’e ty hilala!)
8 Olúwa wí pé, “Ní ọjọ́ náà, Èmi kì yóò ha pa àwọn ọlọ́gbọ́n Edomu run, àti àwọn amòye run kúrò ní òkè Esau?
Ie amy andro zay, hoe t’Iehovà, tsy ho mongoreko Edome ao hao o mahihitseo naho am-bohi’ Esave ty faharendrehañe?
9 A ó ṣe ẹ̀rù ba àwọn jagunjagun rẹ, ìwọ Temani, gbogbo àwọn tó wà ní orí òkè Esau ní a ó gé kúrò nínú ìpànìyàn náà.
Hiroreke o fanalolahi’oo ry Temane, amy te ho fonga haitoañe am-pizamanañe am-bohi’ i Esave eo ondatio.
10 Nítorí ìwà ipá sí Jakọbu arákùnrin rẹ, ìtìjú yóò bò ọ, a ó sì pa ọ run títí láé.
Hañoloñe azo ty fisalarañe ty amy nampisoaña’o an-drahalahi’o Iakobey, vaho haitoañe zafe-zanake irehe.
11 Ní ọjọ́ tí ìwọ dúró ní apá kan, ní ọjọ́ tí àlejò kó ogún rẹ lọ, tí àwọn àjèjì sì wọ ibodè rẹ, tí wọ́n sì sẹ́ kèké lórí Jerusalẹmu, ìwọ náà wà bí ọ̀kan nínú wọn.
Ihe nijagarodoñe eo amy andro zay, amy andro nendese’ o ambahinio mb’eo o vara’eoy naho nizilike an-dalambei’e mb’eo o alik’ama’oo, vaho nanoe’ iereo tsatopiso t’Ierosalaime —ihe nimpiama’ iareo.
12 Ìwọ kì bá tí fi ojú kéré arákùnrin rẹ, ní àkókò ìbànújẹ́ rẹ̀ ìwọ kì bá tí yọ̀ lórí àwọn ọmọ Juda, ní ọjọ́ ìparun wọn ìwọ kì bá tí gbéraga púpọ̀ ní ọjọ́ wàhálà wọn.
Ho nisoa t’ie tsy nisamba an-drahalahi’o amy andron-kekoheko’ey, tsy ho nirebeke amy andro naha-rotsake o ana’ Iehodaoy; mbore tsy nimete ty nisaontsie’o añ’ebotsebotse amy andron-kankàñey.
13 Ìwọ kì bá tí wọ inú ibodè àwọn ènìyàn mi lọ, ní ọjọ́ àjálù wọn. Ìwọ kì bá tí fojú kó wọn mọ́lẹ̀ nínú ìdààmú wọn, ní ọjọ́ àjálù wọn. Ìwọ kì bá tí jí ẹrù wọn kó, ní ọjọ́ ìpọ́njú wọn.
Tsy nimete ty nimoaha’o an-dalambei’ ondatikoo amy andron-kekoheko’ iareoy; Eka, tsy ho nisambà’o ty fisotria’e amy andron-kankà’ iareoy, ndra nampipao-pitàñe amo fanaña’ iareoo amy andro nitarañen-doza’ iareoy.
14 Ìwọ kì bá tí dúró ní ìkóríta ọ̀nà láti ké àwọn tirẹ̀ tó ti sálà kúrò. Ìwọ kì bá tí fa àwọn tó ṣẹ́kù nínú wọn lélẹ̀ ní ọjọ́ wàhálà wọn.
Tsy nimete ty nijohaña’o am-pitsileañe eo hamonoa’o ze nipoliotse mb’eo; naho tsy ho nasese’o o sehanga’eo amy andron-kasotriañey.
15 “Nítorí ọjọ́ Olúwa súnmọ́ etílé lórí gbogbo àwọn kèfèrí. Bí ìwọ ti ṣe, bẹ́ẹ̀ ni a ó ṣe sí ìwọ náà; ẹ̀san rẹ yóò sì yípadà sí orí ara rẹ.
Fa mitotok’ amo kilakila’ ondatio ty andro’ Iehovà: hambañe amo sata’oo ty hanoeñe ama’o. habalik’ añ’ambone’o eo o fitoloña’oo
16 Gẹ́gẹ́ bí ìwọ̀ ṣe mu lórí òkè mímọ́ mi, bẹ́ẹ̀ ni gbogbo kèfèrí yóò máa mu títí; wọn yóò mu ún ní àmutẹ́rùn wọn yóò sì wà bí ẹni pé wọn kò mu ún rí.
Fa manahake ty ninoma’ areo amy vohiko miavakey, ty hinoma’ o ambahinio nainai’e; ie hinoñe naho higenoke, vaho hanahake te mbe lia’e tsy teo.
17 Ṣùgbọ́n ìgbàlà yóò wà lórí òkè Sioni, wọn yóò sì jẹ́ mímọ́, àti ilé Jakọbu yóò sì ní ìní wọn.
F’ie ambohi’ i Tsione ao ty nahapoliotse, ie ho miavake; vaho ho fanaña’ Iakobe o vara’ iareoo.
18 Ilé Jakọbu yóò sì jẹ́ iná àti ilé Josẹfu ọwọ́ iná ilé Esau yóò jẹ àgékù koríko wọn yóò fi iná sí i, wọn yóò jo run. Kì yóò sí ẹni tí yóò kù ní ilé Esau.” Nítorí Olúwa ti sọ̀rọ̀.
Le ho afo ty anjomba’ Iakobe, naho lel’afo ty anjomba’ Iosefe, naho ho ahetse ty anjomba’ i Esave, le ho viañe’ iereo ty ao, hamorototo iareo, vaho tsy hengañe honka’e ty añ’anjomba’ i Esave ao; fa nitsara t’Iehovà.
19 Àwọn ará gúúsù yóò ni òkè Esau, àwọn ará ẹsẹ̀ òkè yóò ni ilẹ̀ àwọn ará Filistini ní ìní. Wọn yóò sì ni oko Efraimu àti Samaria; Benjamini yóò ní Gileadi ní ìní.
Ho a o tatimoo ty vohi’ i Esave, naho i monto’ o nte-Pilisty ambane eio, ho fanaña’ iareo ty tete’ i Efraime, naho ty tonda’ i Somerone, vaho ho fanaña’ i Beniamine t’i Gilade.
20 Àwọn ìgbèkùn Israẹli tí ó wà ní Kenaani yóò ni ilẹ̀ títí dé Sarefati; àwọn ìgbèkùn láti Jerusalẹmu tí ó wà ní Sefaredi yóò ni àwọn ìlú gúúsù ní ìní.
Ho fanaña’ o nirohizañe amy valobohò’ o nte-­Israeleoy ty a o nte-Kenàneo, pak’e Tsakrefate añe; vaho ho fanaña’ o mpirohi’ Ierosalaime e Sefaradeo o rova atimoo.
21 Àwọn tó ń gba ni là yóò sì gòkè Sioni wá láti jẹ ọba lé orí àwọn òkè Esau. Ìjọba náà yóò sì jẹ́ ti Olúwa.
Homb’an-kaboa’ i Tsione mb’eo o mpandrombakeo hizaka ty vohi’ i Esave; vaho ho a Iehovà i fifeheañey.

< Obadiah 1 >