< Numbers 6 >

1 Olúwa sọ fún Mose pé,
Mago'ene Ra Anumzamo'a Mosesena anage huno asami'ne,
2 “Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, ‘Bí ọkùnrin tàbí obìnrin kan bá jẹ́ ẹ̀jẹ́ pàtàkì, ẹ̀jẹ́ ìyara-ẹni-sọ́tọ̀ sí Olúwa nípa àìgé irun orí (Nasiri),
Israeli vahera amanage hunka zamasmio, mago vemo'o, a'mo'o mani ruotge huno Ra Anumzamo'nare huvempa huno ruotge hu'na Nazareti vene a'ene manisue hanuno'a,
3 irú ẹni bẹ́ẹ̀ gbọdọ̀ yàgò fún wáìnì tàbí ọtí líle, ọtí wáìnì kíkan àti àwọn ohun mímu mìíràn tó bá kan. Kò gbọdọ̀ mu èso àjàrà tàbí kí ó jẹ èso àjàrà tútù tàbí gbígbẹ.
waini tine, hankave tine aka tine, waini reratiza hankave ti tro hunte'nesazo, grepimofo tima'o, nena raga'o, hagege hune'sia raga'anena onegahie.
4 Níwọ́n ìgbà tí ó sì jẹ́ Nasiri, ní kò gbọdọ̀ jẹ ohunkóhun tí a fi èso àjàrà ṣe, ìbá à ṣe kóró tàbí èèpo rẹ̀.
Mani ruotge hugahue huno'ma hu'nesia kna'afina, krepiretima tro hu'nesia wainine, avima'ane ukri'anena onegahie.
5 “‘Ní gbogbo ìgbà ẹ̀jẹ́ ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ yìí, kí abẹ kankan má ṣe kàn án ní orí. Ó gbọdọ̀ jẹ́ mímọ́ títí tí àkókò ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ sí Olúwa yóò fi pé; ó gbọdọ̀ jẹ́ kí irun orí rẹ̀ gùn.
Huvempama hu'nesia kna'afina maka zupa resanura anu azokara oharegahie. Ra Anumzamofonte huvempa hunte'nenia kna'afina ruotge huno mani'neno, anu azokara atrenkeno metoku aseno zaza hino.
6 “‘Ní gbogbo àkókò ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ sí Olúwa kò gbọdọ̀ súnmọ́ òkú ènìyàn.
Ra Anumzamofonte mani ruotge huno mani'nesia kna'afina, agra fri vahe tvaontera ovugahie.
7 Ìbá à ṣe òkú baba, àti ìyá rẹ̀, ẹ̀gbọ́n rẹ̀ ọkùnrin tàbí obìnrin tàbí àbúrò rẹ̀, kò gbọdọ̀ sọ ara rẹ̀ di aláìmọ́ nítorí wọn, nítorí pé àmì ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ sí Ọlọ́run wà ní orí rẹ̀.
Hagi nefa'o, nerera'o, nefu'o, nesaro'o frisigeno'a agrira azeri pehena hugahianki avakora osino. Na'ankure Anumzamofonku huno mani ruotge hu'nea avame'zana agri anunte me'ne.
8 Ní gbogbo àsìkò ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ yìí, ó jẹ́ mímọ́ sí Olúwa.
Mani ruotge huno mani'nia kna'afina maka'a zupa, Ra Anumzamo'nare mani ruotge hugahie.
9 “‘Bí ẹnìkan bá kú ní ọ̀dọ̀ rẹ̀ ní òjijì, tí ó sì ba irun rẹ̀ tó yà sọ́tọ̀ jẹ́; ó gbọdọ̀ gé irun rẹ̀ ní ọjọ́ ìwẹ̀nùmọ́ rẹ̀ èyí tí í ṣe ọjọ́ keje.
Hianagi mago vahe'ma tvaoma'are mani'neno antrima haniaza huno frino, huvempama hu'nea azokama eri pehanama hinkeno'a, 7ni'a zagegna maniteno azeri agruma huknarera anu azokara haregahie. E'inama hanuno azeri agru huno manigahie.
10 Ní ọjọ́ kẹjọ, yóò mú àdàbà méjì àti ọmọ ẹyẹlé méjì wá sọ́dọ̀ àlùfáà ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́ ìpàdé.
Hagi anante nanterana 8 zage knarera tare hohopa namao, tare maho namo azerino pristi ne' avuga seli mono nomofo kahante vugahie.
11 Àlùfáà yóò fi ọ̀kan rú ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ àti èkejì fún ẹbọ sísun láti fi ṣe ètùtù fún un nítorí pé ó ti ṣẹ̀ nípa wíwà níbi tí òkú ènìyàn wà. Yóò sì ya orí rẹ̀ sí mímọ́ ní ọjọ́ náà gan an.
Pristi ne'mo'a mago nama kumi'ma apasente ofa nehuno, mago nama kre fanene hu ofa hugahie. Na'ankure fri vahe tva'onte mani'neno kumi' hu'negu mizaneseno, ana zupa anunte azokara eri ruotge hanigeno hagegahie.
12 Ó gbọdọ̀ ya ara rẹ̀ sọ́tọ̀ sí Olúwa fún àkókò ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀, ó sì gbọdọ̀ mú akọ ọ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan wá gẹ́gẹ́ bí ọrẹ ẹ̀bi. Kò sì ní í ka àwọn ọjọ́ ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ ti tẹ́lẹ̀ nítorí pé ó tí ba ara rẹ̀ jẹ́ ní àkókò ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀.
Ana nehuno Ra Anumzamofonte ete agu'a nenteno, mani ruotge huno Nazareti ne'ma manisuema hanuno'a, mago kafu hu'nesia ve sipisipi anenta avreno kumi'mofo ofa hino. Na'ankure ko'ma mani ruotge hu'nea zama fri'zamo eri haviza hunte'negu, eteno mago'ene huvempa kea eri agafa hugahie.
13 “‘Èyí ni òfin fún Nasiri nígbà tí àkókò ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ bá pé. Wọn ó mu wá sí ẹnu-ọ̀nà àgọ́ ìpàdé.
Hagi mani ruotge huno Nazareti vahe tro huno mani'nea kna'ama vagare'na, agra seli mono nomofo kafante eno,
14 Níbẹ̀ ni yóò ti mú ọrẹ wá fún Olúwa, akọ ọ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan tí kò ní àbùkù fún ẹbọ sísun àti ẹgbọrọ-àgùntàn ọlọ́dún kan, tí kò ní àbùkù fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀, àgbò kan tí kò ní àbùkù fún ọrẹ àlàáfíà,
Ra Anumzamo'nare kre fanenema hu ofama eri'noma esiana, mago kafu hu'nesia ve sipisipi afuhe afuhe osu'nesia su'a avreno ne-eno, kumi'ma apasente ofama haniana, mago a' sipisipi mago kafu huno afuhe afahe osu'nesia avreno ne-eno, rimpa fru ofama haniana, mago kafu huno afuhe afahe osu'nesia sipisipine avre'no eme ofa hugahie.
15 pẹ̀lú ọrẹ ohun jíjẹ àti ọrẹ ohun mímu, apẹ̀rẹ̀ àkàrà tí a kò fi ìwúkàrà ṣe, àkàrà tí a fi ìyẹ̀fun dáradára pò mọ́ òróró àti àkàrà fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ tí a fi òróró sọjọ̀ lé lórí.
Hagi witi ofama hu'zana, mago eka eka kupi, zo-ore breti krenenaza eri'za ne-eza kaneza eri knare hu'naza flaua masavene eri havia huza kre'naza kekine, waini ofanena hugahaze.
16 “‘Àlùfáà yóò gbé gbogbo rẹ̀ wá síwájú Olúwa, yóò sì rú ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ àti ẹbọ sísun.
Hagi ana ofama pristi ne'mo'ma Ra Anumzamofo avuga erino eme haniana, esera kumi' apasente ofa huteno, anantera tevefi kre fanene hu ofa hugahie.
17 Àlùfáà yóò fi àgbò náà rú ẹbọ àlàáfíà sí Olúwa, pẹ̀lú apẹ̀rẹ̀ àkàrà tí kò ní ìwúkàrà; yóò rú ẹbọ ohun jíjẹ àti ọrẹ ohun mímu.
Ana nehuno rimpa fru ofa ve sipisipi Ra Anumzamofonte kresramna nevuno, zo-ore bretia eka eka kupi ante'nea ofa nehuno, pristi ne'mo'a anazanke huno witi ofane, waini ti ofanena hugahie.
18 “‘Nígbà náà ni Nasiri náà yóò fá irun ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́ ìpàdé. Yóò fi irun náà sínú iná tó wà lábẹ́ ẹbọ àlàáfíà.
Ana hutena Nazareti vahe manisuema huno'ma mani ruotagema hu'nea ne'mo anuntetira azokara seli mono nomofo kahante ome hareteno, ana azokara rimpa fru ofama kre'nenifi fenka kaziga krenkeno tegahie.
19 “‘Lẹ́yìn tí Nasiri bá ti fá irun ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ tan, àlùfáà yóò mú apá àgbò bíbọ̀, àkàrà aláìwú kan àti àkàrà fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ tí kò ní ìwúkàrà láti inú apẹ̀rẹ̀ yóò sì kó gbogbo rẹ̀ lé e lọ́wọ́.
Hagi ana'ma hute'na pristi ne'mo'a ve sipisipimofo azona'a kavoma krenenafinti e'nerino, ekaeka kupinti zo-ore bretia mago e'nerino, mago zo-ore ta'ori kekine erino, azokama hare'nea ne'mofo azampi antegahie.
20 Àlùfáà yóò fi gbogbo rẹ̀ níwájú Olúwa gẹ́gẹ́ bí ẹbọ fífì, wọ́n jẹ́ mímọ́, wọ́n sì jẹ́ ti àlùfáà pẹ̀lú igẹ̀ tí a fì àti itan tí wọ́n mú wá. Lẹ́yìn èyí, Nasiri náà lè mu wáìnì.
Anante pristi ne'mo'a erisga huno Ra Anumzamonare eri veravema hu ofa hugahie. Hagi eri veravema hia ofane ve sipisipi ahihizane agianena ruotge hugahiankino pristi vahe'mo'zage eri'za negahaze. Pristi ne'mo'ma ana'ma hutena azokama hare'nea ne'mo'a waini tina negahie.
21 “‘Èyí ni òfin Nasiri tó jẹ́ ẹ̀jẹ́, ọrẹ rẹ̀ sí Olúwa, yóò wà ní ìbámu pẹ̀lú ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí Nasiri, ní àfikún sí àwọn ohun mìíràn tó lágbára láti mú wá. Ó gbọdọ̀ mú ẹ̀jẹ́ tó jẹ́ ṣe gẹ́gẹ́ bí òfin Nasiri.’”
Ama'i Nazareti vahe mani ruotge hu'na Ra Anumzamofo avufi manikurema huno'ma huvempama hania vahe'mofo kasege. Hagi anampima mago'a ofama eri agofetuma huza eriza ega'ma hanige'za amne eri'za egahaze. Nazareti vahe mani ruotge hugahune hu'za huvempama hu'nesaza kemofo amage ante'za anazana hugahaze. Ana'ma hanageno'a, Pristi vahe'mo'za asomu kea huramantegahaze.
22 Olúwa sọ fún Mose pé,
Ra Anumzamo'a anage huno Mosesena asami'ne,
23 “Sọ fún Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ pé, ‘Báyìí ni kí ẹ ṣe máa súre fún àwọn ọmọ Israẹli. Ẹ sọ fún wọn pé,
Aronine, ne'mofavre naga'anena amanage hunka zamasmio, Israeli vahe'ma asomu kema huzmantekura, amanage hunka asomu kea huzmanto.
24 “‘“Kí Olúwa bùkún un yín, kí ó sì pa yín mọ́.
Ra Anumzamo'a asomu huneramanteno, kegava huramantegahie.
25 Kí Olúwa kí o mú ojú rẹ̀ kí ó mọ́lẹ̀ sí i yín lára. Kí ó sì ṣàánú fún un yín.
Ra Anumzamo muse huneramanteno, tamazeri knare hugahie.
26 Kí Olúwa bojú wò yín, kí ó sì fún un yín ní àlàáfíà.”’
Ra Anumzamo'a rukrahe huno avugosa huramino tamazeri knare nehuno, Agra'a rimpa fruzana tamigahie.
27 “Báyìí ni wọn ó ṣe fi orúkọ mi sára àwọn ọmọ Israẹli, Èmi ó sì bùkún wọn.”
Hagi Nagri nagifi Israeli vahera asomu kea hu'zmantenkena, Nagra'nia asomura huzmantegahue.

< Numbers 6 >