< Numbers 6 >

1 Olúwa sọ fún Mose pé,
Nake Jehova akĩĩra Musa atĩrĩ,
2 “Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, ‘Bí ọkùnrin tàbí obìnrin kan bá jẹ́ ẹ̀jẹ́ pàtàkì, ẹ̀jẹ́ ìyara-ẹni-sọ́tọ̀ sí Olúwa nípa àìgé irun orí (Nasiri),
“Arĩria andũ a Isiraeli, ũmeere atĩrĩ: ‘Mũndũ mũrũme kana mũndũ-wa-nja angĩenda kwĩhĩta mwĩhĩtwa wa mwanya, ũrĩ mwĩhĩtwa wa kwĩyamũrĩra Jehova atuĩke Mũnaziri,
3 irú ẹni bẹ́ẹ̀ gbọdọ̀ yàgò fún wáìnì tàbí ọtí líle, ọtí wáìnì kíkan àti àwọn ohun mímu mìíràn tó bá kan. Kò gbọdọ̀ mu èso àjàrà tàbí kí ó jẹ èso àjàrà tútù tàbí gbígbẹ.
no nginya atige kũnyua ndibei o na indo iria ingĩ ngagatu cia kũnyua, na ndakananyue thiki ĩthondeketwo kuuma kũrĩ ndibei kana kĩndũ kĩngĩ kĩgagatu gĩa kũnyua. Ndakananyue maaĩ ma thabibũ, kana arĩe thabibũ, kana thabibũ iria nyũmithie.
4 Níwọ́n ìgbà tí ó sì jẹ́ Nasiri, ní kò gbọdọ̀ jẹ ohunkóhun tí a fi èso àjàrà ṣe, ìbá à ṣe kóró tàbí èèpo rẹ̀.
Hĩndĩ ĩrĩa yothe arĩkoragwo arĩ Mũnaziri, ndakanarĩe kĩndũ gĩa kuuma he mũthabibũ, irĩ mbegũ kana makoni.
5 “‘Ní gbogbo ìgbà ẹ̀jẹ́ ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ yìí, kí abẹ kankan má ṣe kàn án ní orí. Ó gbọdọ̀ jẹ́ mímọ́ títí tí àkókò ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ sí Olúwa yóò fi pé; ó gbọdọ̀ jẹ́ kí irun orí rẹ̀ gùn.
“‘Ihinda rĩothe rĩa mwĩhĩtwa ũcio wa kwĩyamũra, ndakanenjwo mũtwe. No nginya aikarage arĩ mũtheru o nginya ihinda rĩake rĩa kwĩyamũrĩra Jehova rĩthire; no nginya areke njuĩrĩ cia mũtwe wake ikũre iraihe.
6 “‘Ní gbogbo àkókò ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ sí Olúwa kò gbọdọ̀ súnmọ́ òkú ènìyàn.
Ihinda rĩu rĩothe eyamũrĩire Jehova ndakanakuhĩrĩrie kĩimba.
7 Ìbá à ṣe òkú baba, àti ìyá rẹ̀, ẹ̀gbọ́n rẹ̀ ọkùnrin tàbí obìnrin tàbí àbúrò rẹ̀, kò gbọdọ̀ sọ ara rẹ̀ di aláìmọ́ nítorí wọn, nítorí pé àmì ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ sí Ọlọ́run wà ní orí rẹ̀.
O na ithe, kana nyina, kana mũrũ wa nyina, kana mwarĩ wa nyina angĩkua, ndakanethaahie nĩ ũndũ wao, tondũ arĩ na rũũri rwa kwĩyamũrĩra Ngai mũtwe.
8 Ní gbogbo àsìkò ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ yìí, ó jẹ́ mímọ́ sí Olúwa.
Ihinda rĩothe rĩa kwĩyamũra gwake arĩkoragwo aamũrĩirwo Jehova.
9 “‘Bí ẹnìkan bá kú ní ọ̀dọ̀ rẹ̀ ní òjijì, tí ó sì ba irun rẹ̀ tó yà sọ́tọ̀ jẹ́; ó gbọdọ̀ gé irun rẹ̀ ní ọjọ́ ìwẹ̀nùmọ́ rẹ̀ èyí tí í ṣe ọjọ́ keje.
“‘Mũndũ angĩkua gĩkuũ kĩa narua arĩ ho, naguo ũndũ ũcio ũthaahie njuĩrĩ ĩrĩa aamũrĩte, no nginya enjwo mũtwe mũthenya wake wa gũtherio, na nĩguo wa mũgwanja.
10 Ní ọjọ́ kẹjọ, yóò mú àdàbà méjì àti ọmọ ẹyẹlé méjì wá sọ́dọ̀ àlùfáà ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́ ìpàdé.
Ningĩ mũthenya wa ĩnana no nginya atware ndirahũgĩ igĩrĩ kana tũtutuura twĩrĩ harĩ mũthĩnjĩri-Ngai hau itoonyero-inĩ rĩa Hema-ya-Gũtũnganwo.
11 Àlùfáà yóò fi ọ̀kan rú ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ àti èkejì fún ẹbọ sísun láti fi ṣe ètùtù fún un nítorí pé ó ti ṣẹ̀ nípa wíwà níbi tí òkú ènìyàn wà. Yóò sì ya orí rẹ̀ sí mímọ́ ní ọjọ́ náà gan an.
Nake mũthĩnjĩri-Ngai arute ĩmwe ĩtuĩke igongona rĩa kũhoroherio mehia, nayo ĩyo ĩngĩ ĩtuĩke nĩ iruta rĩa njino nĩguo ahoroherio, nĩ ũndũ nĩehĩtie nĩgũkorwo arĩ hamwe na kĩimba. Mũthenya o ro ũcio no nginya aamũrĩre Jehova mũtwe wake rĩngĩ.
12 Ó gbọdọ̀ ya ara rẹ̀ sọ́tọ̀ sí Olúwa fún àkókò ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀, ó sì gbọdọ̀ mú akọ ọ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan wá gẹ́gẹ́ bí ọrẹ ẹ̀bi. Kò sì ní í ka àwọn ọjọ́ ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ ti tẹ́lẹ̀ nítorí pé ó tí ba ara rẹ̀ jẹ́ ní àkókò ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀.
No nginya eyamũrĩre Jehova ihinda rĩu rĩa kwĩyamũra, na no nginya arute gatũrũme ka mwaka ũmwe gatuĩke ka igongona rĩa mahĩtia. Mĩthenya ĩrĩa mĩhĩtũku ndĩgũtarwo, tondũ nĩathaahirio ihinda rĩrĩa eyaamũrĩte.
13 “‘Èyí ni òfin fún Nasiri nígbà tí àkókò ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ bá pé. Wọn ó mu wá sí ẹnu-ọ̀nà àgọ́ ìpàdé.
“‘Na rĩrĩ, ũyũ nĩguo watho wa Mũnaziri ihinda rĩake rĩa kwĩyamũrĩra Ngai rĩathira. Nĩakarehwo itoonyero-inĩ rĩa Hema-ya-Gũtũnganwo.
14 Níbẹ̀ ni yóò ti mú ọrẹ wá fún Olúwa, akọ ọ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan tí kò ní àbùkù fún ẹbọ sísun àti ẹgbọrọ-àgùntàn ọlọ́dún kan, tí kò ní àbùkù fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀, àgbò kan tí kò ní àbùkù fún ọrẹ àlàáfíà,
Hau nĩho akaarehe maruta make harĩ Jehova, namo nĩ: gatũrũme ka mwaka ũmwe gatarĩ na kaũũgũ gatuĩke ka iruta rĩa njino, na kamwatĩ ka mwaka ũmwe karĩ igongona rĩa kũhoroheria mehia, na ndũrũme ĩmwe ĩtarĩ na kaũũgũ ĩrĩ iruta rĩa ũiguano,
15 pẹ̀lú ọrẹ ohun jíjẹ àti ọrẹ ohun mímu, apẹ̀rẹ̀ àkàrà tí a kò fi ìwúkàrà ṣe, àkàrà tí a fi ìyẹ̀fun dáradára pò mọ́ òróró àti àkàrà fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ tí a fi òróró sọjọ̀ lé lórí.
hamwe na maruta ma mũtu na maruta ma kũnyuuo, na gĩkabũ kĩa mĩgate ĩtarĩ na ndawa ya kũimbia, na keki cia mũtu ũrĩa mũhinyu mũno ũtukanĩtio na maguta, na tũmĩgate tũhũthũ tũhakĩtwo maguta.
16 “‘Àlùfáà yóò gbé gbogbo rẹ̀ wá síwájú Olúwa, yóò sì rú ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ àti ẹbọ sísun.
“‘Mũthĩnjĩri-Ngai nĩakaiga indo icio mbere ya Jehova, na acooke arute igongona rĩa kũhoroheria mehia o na iruta rĩa njino.
17 Àlùfáà yóò fi àgbò náà rú ẹbọ àlàáfíà sí Olúwa, pẹ̀lú apẹ̀rẹ̀ àkàrà tí kò ní ìwúkàrà; yóò rú ẹbọ ohun jíjẹ àti ọrẹ ohun mímu.
Nĩakarehe gĩkabũ kĩu kĩa mĩgate ĩtarĩ mĩimbie na arute ndũrũme ĩyo ĩrĩ igongona rĩa ũiguano kũrĩ Jehova, hamwe na igongona rĩayo rĩa mũtu na rĩa indo cia kũnyuuo.
18 “‘Nígbà náà ni Nasiri náà yóò fá irun ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́ ìpàdé. Yóò fi irun náà sínú iná tó wà lábẹ́ ẹbọ àlàáfíà.
“‘Ningĩ hau itoonyero-inĩ rĩa Hema-ya-Gũtũnganwo, Mũnaziri no nginya enjwo njuĩrĩ ĩrĩa aamũrĩte. Nĩakoya njuĩrĩ ĩyo na amĩikie mwaki-inĩ ũrĩa ũrĩ rungu rwa igongona rĩu rĩa ũiguano.
19 “‘Lẹ́yìn tí Nasiri bá ti fá irun ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ tan, àlùfáà yóò mú apá àgbò bíbọ̀, àkàrà aláìwú kan àti àkàrà fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ tí kò ní ìwúkàrà láti inú apẹ̀rẹ̀ yóò sì kó gbogbo rẹ̀ lé e lọ́wọ́.
“‘Thuutha wa Mũnaziri ũcio kwenjwo njuĩrĩ yake ya kwĩyamũra, mũthĩnjĩri-Ngai nĩ akoya kĩande gĩtherũkĩtio kĩa ndũrũme ĩyo, na keki na tũmĩgate tũrĩa tũhũthũ kuuma gĩkabũ-inĩ kĩu, cierĩ itarĩ ndawa ya kũimbia.
20 Àlùfáà yóò fi gbogbo rẹ̀ níwájú Olúwa gẹ́gẹ́ bí ẹbọ fífì, wọ́n jẹ́ mímọ́, wọ́n sì jẹ́ ti àlùfáà pẹ̀lú igẹ̀ tí a fì àti itan tí wọ́n mú wá. Lẹ́yìn èyí, Nasiri náà lè mu wáìnì.
Mũthĩnjĩri-Ngai acooke acithũngũthie mbere ya Jehova, ituĩke igongona rĩa gũthũngũthio; nĩ nyamũre, na nĩ cia mũthĩnjĩri-Ngai, hamwe na gĩthũri kĩrĩa gĩthũngũthĩtio, o na kĩero kĩrĩa kĩrutĩtwo. Thuutha ũcio Mũnaziri no anyue ndibei.
21 “‘Èyí ni òfin Nasiri tó jẹ́ ẹ̀jẹ́, ọrẹ rẹ̀ sí Olúwa, yóò wà ní ìbámu pẹ̀lú ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí Nasiri, ní àfikún sí àwọn ohun mìíràn tó lágbára láti mú wá. Ó gbọdọ̀ mú ẹ̀jẹ́ tó jẹ́ ṣe gẹ́gẹ́ bí òfin Nasiri.’”
“‘Ũcio nĩguo watho wa Mũnaziri ũrĩa wĩhĩtaga kũrutĩra Jehova indo kũringana na ũrĩa eyaamũrĩte, hamwe na kĩrĩa kĩngĩ gĩothe angĩhota kũruta. No nginya ahingie mwĩhĩtwa ũrĩa ehĩtĩte, kũringana na watho wa Mũnaziri.’”
22 Olúwa sọ fún Mose pé,
Ningĩ Jehova akĩĩra Musa atĩrĩ,
23 “Sọ fún Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ pé, ‘Báyìí ni kí ẹ ṣe máa súre fún àwọn ọmọ Israẹli. Ẹ sọ fún wọn pé,
“Ĩra Harũni na ariũ ake atĩrĩ, ‘Ũũ nĩguo mũrĩrathimaga andũ a Isiraeli. Meragei atĩrĩ:
24 “‘“Kí Olúwa bùkún un yín, kí ó sì pa yín mọ́.
“‘“Jehova arokũrathima, na akũmenyagĩrĩre;
25 Kí Olúwa kí o mú ojú rẹ̀ kí ó mọ́lẹ̀ sí i yín lára. Kí ó sì ṣàánú fún un yín.
Jehova arotũma ũthiũ wake ũkwarĩre, na agũkinyagĩrie wega wake;
26 Kí Olúwa bojú wò yín, kí ó sì fún un yín ní àlàáfíà.”’
Jehova arogũtiirĩra gĩthiithi gĩake, na akũhe thayũ.”’
27 “Báyìí ni wọn ó ṣe fi orúkọ mi sára àwọn ọmọ Israẹli, Èmi ó sì bùkún wọn.”
“Nĩ ũndũ ũcio athĩnjĩri-Ngai nĩmarĩgwetaga rĩĩtwa rĩakwa kũrĩ andũ a Isiraeli, na niĩ nĩndĩĩmarathimaga.”

< Numbers 6 >