< Numbers 6 >

1 Olúwa sọ fún Mose pé,
BAWIPA ni Mosi hah a pato teh,
2 “Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, ‘Bí ọkùnrin tàbí obìnrin kan bá jẹ́ ẹ̀jẹ́ pàtàkì, ẹ̀jẹ́ ìyara-ẹni-sọ́tọ̀ sí Olúwa nípa àìgé irun orí (Nasiri),
Isarel catounnaw koe dei pouh. Ahnimouh koe tongpa thoseh, napui thoseh BAWIPA koe ama Nazirite lawkkamnae la hanlah, a kâkapek teh a kâhmoun toteh,
3 irú ẹni bẹ́ẹ̀ gbọdọ̀ yàgò fún wáìnì tàbí ọtí líle, ọtí wáìnì kíkan àti àwọn ohun mímu mìíràn tó bá kan. Kò gbọdọ̀ mu èso àjàrà tàbí kí ó jẹ èso àjàrà tútù tàbí gbígbẹ.
misur hoi yamu tek mahoeh. Misurtui hoi yamucang hai net mahoeh. Misurtui nei e hoi misurpaw katha e khumbei dawk vaw teh kamyai e hai cat mahoeh.
4 Níwọ́n ìgbà tí ó sì jẹ́ Nasiri, ní kò gbọdọ̀ jẹ ohunkóhun tí a fi èso àjàrà ṣe, ìbá à ṣe kóró tàbí èèpo rẹ̀.
A kâkapek nah yunglam pueng teh misurkung dawk hoi a mu thoseh, atui thoseh cat awh mahoeh.
5 “‘Ní gbogbo ìgbà ẹ̀jẹ́ ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ yìí, kí abẹ kankan má ṣe kàn án ní orí. Ó gbọdọ̀ jẹ́ mímọ́ títí tí àkókò ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ sí Olúwa yóò fi pé; ó gbọdọ̀ jẹ́ kí irun orí rẹ̀ gùn.
A kâkapeknae lawk a kam nah thung pueng teh, a lû ngaw mahoeh. BAWIPA hmalah a kâpeknae hnin a pha hoehroukrak teh kathounge lah ao han. Hottelah a sam a hlung vaiteh, a sai sak han.
6 “‘Ní gbogbo àkókò ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ sí Olúwa kò gbọdọ̀ súnmọ́ òkú ènìyàn.
BAWIPA hanlah a kâkapeknae thung pueng teh, tami ro koe hnai mahoeh.
7 Ìbá à ṣe òkú baba, àti ìyá rẹ̀, ẹ̀gbọ́n rẹ̀ ọkùnrin tàbí obìnrin tàbí àbúrò rẹ̀, kò gbọdọ̀ sọ ara rẹ̀ di aláìmọ́ nítorí wọn, nítorí pé àmì ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ sí Ọlọ́run wà ní orí rẹ̀.
A na pa thoseh, a manu thoseh, a hmaunawngha thoseh, a tawncanu thoseh, a duenae kong dawk hai kâkhinsak hanh naseh. Bangkongtetpawiteh, Cathut hanlah a kâkapeknae a lû dawk ao.
8 Ní gbogbo àsìkò ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ yìí, ó jẹ́ mímọ́ sí Olúwa.
A kâkapek yunglam teh BAWIPA hanlah kathounge lah ao han.
9 “‘Bí ẹnìkan bá kú ní ọ̀dọ̀ rẹ̀ ní òjijì, tí ó sì ba irun rẹ̀ tó yà sọ́tọ̀ jẹ́; ó gbọdọ̀ gé irun rẹ̀ ní ọjọ́ ìwẹ̀nùmọ́ rẹ̀ èyí tí í ṣe ọjọ́ keje.
Ateng vah, pouk laipalah tami koe dout pawiteh, a kâkapeknae a lû dawk khin sak pawiteh, a kamthoung nah hnin vah, a lû a ngaw vaiteh, a hnin sari hnin vah a pâkhamuen a ngaw han.
10 Ní ọjọ́ kẹjọ, yóò mú àdàbà méjì àti ọmọ ẹyẹlé méjì wá sọ́dọ̀ àlùfáà ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́ ìpàdé.
A hnin taroe hnin vah, kamkhuengnae lukkareiim takhang koe e vaihma koe bakhu kahni touh thoseh, Âbakhu kahni touh thoseh a sin awh han.
11 Àlùfáà yóò fi ọ̀kan rú ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ àti èkejì fún ẹbọ sísun láti fi ṣe ètùtù fún un nítorí pé ó ti ṣẹ̀ nípa wíwà níbi tí òkú ènìyàn wà. Yóò sì ya orí rẹ̀ sí mímọ́ ní ọjọ́ náà gan an.
Vaihma ni buet touh teh yon thueng nahanlah a poe vaiteh, alouke buet touh teh hmaisawi thueng nahan, tami kadout kecu dawk a sakpayon e dawk a yontha nahanlah a sak pouh han. Hot hnin vah a lû hah a thoung sak han.
12 Ó gbọdọ̀ ya ara rẹ̀ sọ́tọ̀ sí Olúwa fún àkókò ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀, ó sì gbọdọ̀ mú akọ ọ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan wá gẹ́gẹ́ bí ọrẹ ẹ̀bi. Kò sì ní í ka àwọn ọjọ́ ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ ti tẹ́lẹ̀ nítorí pé ó tí ba ara rẹ̀ jẹ́ ní àkókò ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀.
Hahoi kâtapoe thuengnae dawkvah kum touh ka pha e tuca a tan a thokhai vaiteh, kâkapeknae hnin teh BAWIPA koe vah a katha lah a tâcokhai han. Bangkongtetpawiteh, kâkapeknae hah a khin sak toung dawkvah, ahmaloe e teh banglah tho mahoeh toe.
13 “‘Èyí ni òfin fún Nasiri nígbà tí àkókò ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ bá pé. Wọn ó mu wá sí ẹnu-ọ̀nà àgọ́ ìpàdé.
Hahoi Nazirite a kâkapeknae hnin a kuep toteh, a sak awh hane kâlawk doeh. Kamkhuengnae lukkareiim takhang koe na ceikhai awh han.
14 Níbẹ̀ ni yóò ti mú ọrẹ wá fún Olúwa, akọ ọ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan tí kò ní àbùkù fún ẹbọ sísun àti ẹgbọrọ-àgùntàn ọlọ́dún kan, tí kò ní àbùkù fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀, àgbò kan tí kò ní àbùkù fún ọrẹ àlàáfíà,
Hahoi BAWIPA koe thuengnae hah a poe han. Tutan kacueme hmaisawi thuengnae koe buet touh, yon thueng nahanelah tulaca kacueme buet touh, roum thueng nahanelah, kacueme tutanca buet touh,
15 pẹ̀lú ọrẹ ohun jíjẹ àti ọrẹ ohun mímu, apẹ̀rẹ̀ àkàrà tí a kò fi ìwúkàrà ṣe, àkàrà tí a fi ìyẹ̀fun dáradára pò mọ́ òróró àti àkàrà fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ tí a fi òróró sọjọ̀ lé lórí.
tonphuenhoehe tavai hah a kanui e tavai satui hoi kanawk e tavai tueng buet touh satui hluk e tavai ka rapamca e a tabu buet touh, tavai thuengnae hoi lannae thueng hoi na poe awh han.
16 “‘Àlùfáà yóò gbé gbogbo rẹ̀ wá síwájú Olúwa, yóò sì rú ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ àti ẹbọ sísun.
Hahoi vaihma ni tavai hah BAWIPA hmalah a thokhai vaiteh, yon thuengnae hoi hmaisawi thuengnae hah a poe han.
17 Àlùfáà yóò fi àgbò náà rú ẹbọ àlàáfíà sí Olúwa, pẹ̀lú apẹ̀rẹ̀ àkàrà tí kò ní ìwúkàrà; yóò rú ẹbọ ohun jíjẹ àti ọrẹ ohun mímu.
Hahoi tutan hah tonphuenhoehe tavai tabu dawk hoi roum thuengnae hah Bawipa koe a poe han. Vaihma ni tavai thuengnae, nei thuengnae hoi a poe sin han.
18 “‘Nígbà náà ni Nasiri náà yóò fá irun ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́ ìpàdé. Yóò fi irun náà sínú iná tó wà lábẹ́ ẹbọ àlàáfíà.
Nazirite tami ni, kamkhuengnae lukkareiim takhang koe a sam hah a ngaw vaiteh, roum thuengnae a saknae koe hmai hoi a sawi han.
19 “‘Lẹ́yìn tí Nasiri bá ti fá irun ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ tan, àlùfáà yóò mú apá àgbò bíbọ̀, àkàrà aláìwú kan àti àkàrà fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ tí kò ní ìwúkàrà láti inú apẹ̀rẹ̀ yóò sì kó gbogbo rẹ̀ lé e lọ́wọ́.
Hahoi vaihma ni tutan e a loung a thawng e hoi tonphuenhoehe a tabu dawk a ta e vaiyei buet touh, tonphuenhoehe vaiyei ka rapam e phen buet touh, a la vaiteh, Nazirite niyah a kâhmounnae a sam koung a ngaw hnukkhu hoi a kut dawk a ta han.
20 Àlùfáà yóò fi gbogbo rẹ̀ níwájú Olúwa gẹ́gẹ́ bí ẹbọ fífì, wọ́n jẹ́ mímọ́, wọ́n sì jẹ́ ti àlùfáà pẹ̀lú igẹ̀ tí a fì àti itan tí wọ́n mú wá. Lẹ́yìn èyí, Nasiri náà lè mu wáìnì.
Hahoi vaihma ni kahek thuengnae dawkvah, BAWIPA hmalah a kahek han. Hetheh vaihma hmang lah kaawm han. Hetheh vaihma e ham lah kaawm han. Kahek e a takuep hoi a kahek e a phai teh a thoung han, hahoi teh Nazirite tami ni misur a nei thai han toe, telah a ti.
21 “‘Èyí ni òfin Nasiri tó jẹ́ ẹ̀jẹ́, ọrẹ rẹ̀ sí Olúwa, yóò wà ní ìbámu pẹ̀lú ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí Nasiri, ní àfikún sí àwọn ohun mìíràn tó lágbára láti mú wá. Ó gbọdọ̀ mú ẹ̀jẹ́ tó jẹ́ ṣe gẹ́gẹ́ bí òfin Nasiri.’”
Hetheh Nazirite lawkkam a kâhmounnae hoi poehno e BAWIPA koe lawkkamnae kasakkung e kâlawk lah ao. Hothloilah a ma kut hoi ka dam sak e pueng hah lawkkamnae a sak e patetlah a kâhmounnae kâlawk patetlah a sak roeroe han.;
22 Olúwa sọ fún Mose pé,
BAWIPA ni Mosi hah a pato teh,
23 “Sọ fún Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ pé, ‘Báyìí ni kí ẹ ṣe máa súre fún àwọn ọmọ Israẹli. Ẹ sọ fún wọn pé,
Aron hoi a capanaw koevah, het patetlah Isarel catounnaw yawhawi na poe han, ahnimouh koe,
24 “‘“Kí Olúwa bùkún un yín, kí ó sì pa yín mọ́.
BAWIPA ni yawhawi na poe awh teh, na khenyawn awh naseh.
25 Kí Olúwa kí o mú ojú rẹ̀ kí ó mọ́lẹ̀ sí i yín lára. Kí ó sì ṣàánú fún un yín.
BAWIPA ni a minhmai nangmouh koe kho lah a sei vaiteh, na pahren awh naseh.
26 Kí Olúwa bojú wò yín, kí ó sì fún un yín ní àlàáfíà.”’
BAWIPA teh nangmouh koelah kangvawi seh, roumnae na poe awh han, telah dei pouh awh telah a dei.
27 “Báyìí ni wọn ó ṣe fi orúkọ mi sára àwọn ọmọ Israẹli, Èmi ó sì bùkún wọn.”
Hot patetlah sak e ni Isarel catounnaw koe ka min a kamnue sak awh han. Kai ni ahnimouh teh yawhawi ka poe han, telah a ti.

< Numbers 6 >