< Numbers 6 >
Hina Gode da Mousesema e da Isala: ili dunu ilima amane alofele sia: ma: ne sia: i, “Nowa dunu o uda da Na: salaide hamoma: ne amola Hina Godema fawane fa: no bobogema: ne dafawaneyale ilegesea, e da waini hano amola adini hamedafa manu. E da hano amo da waini fagega hamoi, waini fage amola hafoga: i waini fage huluane hamedafa manu.
2 “Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, ‘Bí ọkùnrin tàbí obìnrin kan bá jẹ́ ẹ̀jẹ́ pàtàkì, ẹ̀jẹ́ ìyara-ẹni-sọ́tọ̀ sí Olúwa nípa àìgé irun orí (Nasiri),
3 irú ẹni bẹ́ẹ̀ gbọdọ̀ yàgò fún wáìnì tàbí ọtí líle, ọtí wáìnì kíkan àti àwọn ohun mímu mìíràn tó bá kan. Kò gbọdọ̀ mu èso àjàrà tàbí kí ó jẹ èso àjàrà tútù tàbí gbígbẹ.
4 Níwọ́n ìgbà tí ó sì jẹ́ Nasiri, ní kò gbọdọ̀ jẹ ohunkóhun tí a fi èso àjàrà ṣe, ìbá à ṣe kóró tàbí èèpo rẹ̀.
E da Na: salaide ilegei hou amo ganodini esalea, e da waini fage liligi, oso amola gadofo huluanedafa hame manu. Amo da ema sema gala.
5 “‘Ní gbogbo ìgbà ẹ̀jẹ́ ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ yìí, kí abẹ kankan má ṣe kàn án ní orí. Ó gbọdọ̀ jẹ́ mímọ́ títí tí àkókò ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ sí Olúwa yóò fi pé; ó gbọdọ̀ jẹ́ kí irun orí rẹ̀ gùn.
E da Na: salaide ilegei hou amo ganodini esalea, e da ea dialuma hinabo luga hamedafa damumu amola ea maya: bo hame waga: mu. E da eso huluane Hina Godema ilegei esoga ea ilegesu amoga la: la: gi dagoi agoane ba: mu. Amola ea dialuma amola ea maya: bo da udigili agoane alemu.
6 “‘Ní gbogbo àkókò ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ sí Olúwa kò gbọdọ̀ súnmọ́ òkú ènìyàn.
Na: salaide dunu ea dialuma hinabo, e da Godema ilegei amo ilegesu olelesu agoane gala. Amaiba: le, e da ledo hamosa: besa: le, bogoi da: i hodo gadenene masunu da ema sema bagade. Dafawane! Amola ea ada o ame, yolalia o dalusilali bogosea, e da amo da: i hodo gadenene hamedafa masunu.
7 Ìbá à ṣe òkú baba, àti ìyá rẹ̀, ẹ̀gbọ́n rẹ̀ ọkùnrin tàbí obìnrin tàbí àbúrò rẹ̀, kò gbọdọ̀ sọ ara rẹ̀ di aláìmọ́ nítorí wọn, nítorí pé àmì ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ sí Ọlọ́run wà ní orí rẹ̀.
8 Ní gbogbo àsìkò ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ yìí, ó jẹ́ mímọ́ sí Olúwa.
E da Na: salaide dunu esalea, e da Hina Godema ilegele mogiligai dagoi ba: mu.
9 “‘Bí ẹnìkan bá kú ní ọ̀dọ̀ rẹ̀ ní òjijì, tí ó sì ba irun rẹ̀ tó yà sọ́tọ̀ jẹ́; ó gbọdọ̀ gé irun rẹ̀ ní ọjọ́ ìwẹ̀nùmọ́ rẹ̀ èyí tí í ṣe ọjọ́ keje.
Be Na: salaide dunu da dunu amo da hedolo bogosea, amo gadenene lelebeba: le, e da eso fesuale ouesalu, amasea dialuma hinabo amola ea maya: bo waga: ma: mu. Amasea, ea ledo hamoi da fadegai dagoi ba: mu.
10 Ní ọjọ́ kẹjọ, yóò mú àdàbà méjì àti ọmọ ẹyẹlé méjì wá sọ́dọ̀ àlùfáà ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́ ìpàdé.
Eso godo amoga, e da ‘dafe’ sio aduna o musuni aduna amo Hina Gode Ea Abula Diasu logo holeiga gaguli misini, gobele salasu dunu ema imunu.
11 Àlùfáà yóò fi ọ̀kan rú ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ àti èkejì fún ẹbọ sísun láti fi ṣe ètùtù fún un nítorí pé ó ti ṣẹ̀ nípa wíwà níbi tí òkú ènìyàn wà. Yóò sì ya orí rẹ̀ sí mímọ́ ní ọjọ́ náà gan an.
Gobele salasu dunu da sio afadafa amo Wadela: i Hou Gogolema: ne Olofoma: ne Iasu hamomu amola sio eno amo Wadela: i Hou Dabe Ima: ne Iasu agoane hamomu. Amo dunu da bogoi da: i hodo gadenene ahoabeba: le, ledo hamoi, amo dodofema: ne agoane hamosa. Amo esoga, amo dunu da ea dialuma hinabo bu Godema Na: salaide hou defele mogiligale ilegemu.
12 Ó gbọdọ̀ ya ara rẹ̀ sọ́tọ̀ sí Olúwa fún àkókò ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀, ó sì gbọdọ̀ mú akọ ọ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan wá gẹ́gẹ́ bí ọrẹ ẹ̀bi. Kò sì ní í ka àwọn ọjọ́ ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ ti tẹ́lẹ̀ nítorí pé ó tí ba ara rẹ̀ jẹ́ ní àkókò ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀.
E da Hina Godema ea Na: salaide eso hamosu bu mogiligale ilegemu. E da musa: eso hamoi amo da bu hame dawa: mu. Bai ea dialuma hinabo mogili gagale ilegei da ledo hamoi dagoi. E da Dabe Iasu hamoma: ne, sibi mano ode afae lalelegei, amo gaguli misunu.
13 “‘Èyí ni òfin fún Nasiri nígbà tí àkókò ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ bá pé. Wọn ó mu wá sí ẹnu-ọ̀nà àgọ́ ìpàdé.
Na: salaide dunu da ea ilegei eso huluane hamoi dagosea, e da agoane hamomu. E da Hina Gode Ea Abula Diasu logo holeiga asili,
14 Níbẹ̀ ni yóò ti mú ọrẹ wá fún Olúwa, akọ ọ̀dọ́-àgùntàn ọlọ́dún kan tí kò ní àbùkù fún ẹbọ sísun àti ẹgbọrọ-àgùntàn ọlọ́dún kan, tí kò ní àbùkù fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀, àgbò kan tí kò ní àbùkù fún ọrẹ àlàáfíà,
ohe udiana noga: i (ledo hamedei) amo Hina Godema imunu. Amo da ode afae lalelegele esala gawali sibi mano Wadela: i Hou Dabe Ima: ne Iasu hamoma: ne; amola ode afae lalelegei aseme sibi mano Wadela: i Hou Gogolema: ne Olofoma: ne Iasu hamoma: ne amola sibi gawali amo Hahawane Gilisili Olofole Iasu hamoma: ne.
15 pẹ̀lú ọrẹ ohun jíjẹ àti ọrẹ ohun mímu, apẹ̀rẹ̀ àkàrà tí a kò fi ìwúkàrà ṣe, àkàrà tí a fi ìyẹ̀fun dáradára pò mọ́ òróró àti àkàrà fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ tí a fi òróró sọjọ̀ lé lórí.
Amola e da daba amo ganodini da agi ga: gini gagai (yisidi hame gala) imunu. Amo agi da gadugagi ba: mu amola falaua amola olife susuligi gilisili bibiagoi amoga hamoi. Amola ga: gi abenai amoga olife susuligi da unasi amola e da gala: ine amola waini hano ilegei iasu gaguli misa: mu.
16 “‘Àlùfáà yóò gbé gbogbo rẹ̀ wá síwájú Olúwa, yóò sì rú ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ àti ẹbọ sísun.
Gobele salasu dunu da amo liligi huluane Hina Godema imunu. Amola e da Wadela: i Hou Gogolema: ne Olofoma: ne Iasu amola Wadela: i Hou Dabe Ima: ne Iasu amo gobele salimu.
17 Àlùfáà yóò fi àgbò náà rú ẹbọ àlàáfíà sí Olúwa, pẹ̀lú apẹ̀rẹ̀ àkàrà tí kò ní ìwúkàrà; yóò rú ẹbọ ohun jíjẹ àti ọrẹ ohun mímu.
E da Hahawane Gilisili Olofole Iasu hamoma: ne, sibi gawali amola agi sali daba amo gilisili imunu. Amola, e da gala: ine amola waini hano imunu.
18 “‘Nígbà náà ni Nasiri náà yóò fá irun ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́ ìpàdé. Yóò fi irun náà sínú iná tó wà lábẹ́ ẹbọ àlàáfíà.
Na: salaide dunu da Abula Diasu logo holeiga asili, ea dialuma hinabo waga: ne, lalu amoga Hahawane Gilisili Olofole Iasu da hamonanebe, amoga ligisima: mu.
19 “‘Lẹ́yìn tí Nasiri bá ti fá irun ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ tan, àlùfáà yóò mú apá àgbò bíbọ̀, àkàrà aláìwú kan àti àkàrà fẹ́lẹ́fẹ́lẹ́ tí kò ní ìwúkàrà láti inú apẹ̀rẹ̀ yóò sì kó gbogbo rẹ̀ lé e lọ́wọ́.
Amasea, sibi gawali ea bea dagai da gobei dagosea, gobele salasu dunu da amo amola gadugagi agi ga: gi afae amola belowagi dabaga lale, Na: salaide dunu amo ea lobo ganodini ligisimu.
20 Àlùfáà yóò fi gbogbo rẹ̀ níwájú Olúwa gẹ́gẹ́ bí ẹbọ fífì, wọ́n jẹ́ mímọ́, wọ́n sì jẹ́ ti àlùfáà pẹ̀lú igẹ̀ tí a fì àti itan tí wọ́n mú wá. Lẹ́yìn èyí, Nasiri náà lè mu wáìnì.
Amasea, gobele salasu dunu da amo liligi, Hina Godema imunu. Ilia da gobele salasu dunuma ima: ne, hadigi iasu agoane hamoi. E da amo liligi amola sibi gawali ea bidegi amola emo (Isala: ili sema ganodini, amo da gobele salasu dunu ea: ) amo lamu. Amo fa: no, Na: salaide dunu da waini manu defea.
21 “‘Èyí ni òfin Nasiri tó jẹ́ ẹ̀jẹ́, ọrẹ rẹ̀ sí Olúwa, yóò wà ní ìbámu pẹ̀lú ìyàsọ́tọ̀ rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí Nasiri, ní àfikún sí àwọn ohun mìíràn tó lágbára láti mú wá. Ó gbọdọ̀ mú ẹ̀jẹ́ tó jẹ́ ṣe gẹ́gẹ́ bí òfin Nasiri.’”
Amo dedei liligi da Na: salaide dunu ilia sema. Be Na: salaide dunu da Na: salaide sema amo baligimusa: ilegele sia: sea, amola baligili iasu imunusa: ilegesea, e da amo baligi ilegei defele noga: le hamoma: mu.
Hina Gode da Mousesema e da Elane amola egefelali ilima alofele sia: ma: ne sia: i, “Dilia da Isala: ili dunuma, ili hahawane esaloma: ne hahawane dogolegele sia: sea, amane sia: ma,
23 “Sọ fún Aaroni àti àwọn ọmọ rẹ̀ pé, ‘Báyìí ni kí ẹ ṣe máa súre fún àwọn ọmọ Israẹli. Ẹ sọ fún wọn pé,
24 “‘“Kí Olúwa bùkún un yín, kí ó sì pa yín mọ́.
‘Hina Gode da dilima hahawane dogolegele hamomu amola dili noga: le ouligimu da defea.
25 Kí Olúwa kí o mú ojú rẹ̀ kí ó mọ́lẹ̀ sí i yín lára. Kí ó sì ṣàánú fún un yín.
Hina Gode da dilima asigimu amola dilima gogolema: ne olofosu hou olelemu da defea.
26 Kí Olúwa bojú wò yín, kí ó sì fún un yín ní àlàáfíà.”’
Hina Gode da dili hahawane ba: mu amola dilima olofosu imunu da defea.’”
27 “Báyìí ni wọn ó ṣe fi orúkọ mi sára àwọn ọmọ Israẹli, Èmi ó sì bùkún wọn.”
Amola, Hina Gode da amane sia: i, “Elane amola ea mano da Na Dioba: le, Isala: ili dunuma hahawane dogolegele hamoma: ne sia: iasea, Na amola da ilima hahawane dogolegele hamomu.”