< Numbers 5 >

1 Olúwa sọ fún Mose pé,
Nake Jehova akĩĩra Musa atĩrĩ,
2 “Pàṣẹ fún àwọn ọmọ Israẹli pé kí wọn ó lé ẹnikẹ́ni tó bá ní ẹ̀tẹ̀, ìtújáde ara ní oríṣìíríṣìí tàbí ẹni tó jẹ́ aláìmọ́ nípa fífọwọ́ kan òkú.
“Atha andũ a Isiraeli maingate kuuma kambĩ-inĩ yao mũndũ o wothe ũrũarĩte mũrimũ wa ngoothi ũrĩa ũngĩgwatanio, kana mũndũ ũrĩ na handũ o na ha he kuura, kana mũndũ ũrĩ na thaahu nĩ ũndũ wa kũhutia kĩimba.
3 Irú ẹni bẹ́ẹ̀ yálà ọkùnrin tàbí obìnrin, ẹ lé wọn jáde kúrò nínú ibùdó kí wọn má ba à ba ibùdó wọn jẹ́ níbi tí èmi ń gbé láàrín wọn.”
Ingata arũme o na andũ-a-nja; ũmaingate nja ya kambĩ nĩguo matigathaahie kambĩ yao kũrĩa niĩ ndũũranagia na inyuĩ.”
4 Àwọn ọmọ Israẹli sì ṣe bẹ́ẹ̀; wọ́n lé wọn jáde kúrò nínú ibùdó. Wọn ṣe gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti sọ fún Mose.
Ũguo noguo andũ a Isiraeli meekire; makĩruta andũ acio nja ya kambĩ. Magĩĩka o ũrĩa Jehova aathĩte Musa gwĩkwo.
5 Olúwa sọ fún Mose pé,
Ningĩ Jehova akĩĩra Musa atĩrĩ,
6 “Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli: ‘Nígbà tí ọkùnrin kan tàbí obìnrin kan bá ṣẹ̀ ara wọn lọ́nà kan tàbí òmíràn, tí wọ́n sì ṣe àìṣòótọ́ sí Olúwa, ẹni náà jẹ̀bi.
“Ĩra andũ a Isiraeli atĩrĩ, ‘Rĩrĩa mũndũ mũrũme kana mũndũ-wa-nja angĩhĩtĩria mũndũ ũrĩa ũngĩ na njĩra o yothe, na nĩ ũndũ ũcio aage kwĩhokeka harĩ Jehova-rĩ, mũndũ ũcio nĩ mũhĩtia,
7 Ó gbọdọ̀ jẹ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ tí ó sẹ̀. Ó gbọdọ̀ san ẹ̀san rẹ̀ ní ojú owó, kí ó sì fi ìdámárùn-ún rẹ̀ lé e, kí ó sì fi fún ẹni tí òun jẹ̀bi rẹ̀.
na no nginya oimbũre mehia marĩa ekĩte. No nginya arute irĩhi rĩothe nĩ ũndũ wa mahĩtia macio make, na ongerere gĩcunjĩ gĩa ithano kũrĩ irĩhi rĩu, anengere mũndũ ũcio ahĩtĩirie.
8 Ṣùgbọ́n bí irú ẹni bẹ́ẹ̀ kò bá ní ìbátan tí ó súnmọ́ ọn tí ó lè ṣe àtúnṣe àṣìṣe rẹ̀ náà fún, àtúnṣe náà jẹ́ ti Olúwa, ẹ sì gbọdọ̀ ko fún àlùfáà pẹ̀lú àgbò tí a fi ṣe ètùtù fún ẹni náà.
No mũndũ ũcio angĩkorwo ndarĩ na mũndũ wa nyũmba yao ũrĩa ũngĩrĩhwo nĩ ũndũ wa ihĩtia rĩu, irĩhi rĩu rĩrĩtuĩkaga rĩa Jehova, na no nginya rĩnengerwo mũthĩnjĩri-Ngai rĩrĩ hamwe na ndũrũme ya kũrutwo igongona rĩa horohio nĩ ũndũ wake.
9 Gbogbo ọrẹ ohun mímọ́ tí àwọn ọmọ Israẹli bá mú wá fún àlùfáà jẹ́ tirẹ̀.
Maruta mothe maamũre marĩa andũ a Isiraeli marĩrehagĩra mũthĩnjĩri-Ngai-rĩ, marĩtuĩkaga make.
10 Ọrẹ ohun mímọ́ ẹnìkọ̀ọ̀kan jẹ́ ti òun nìkan, ṣùgbọ́n ohunkóhun tó bá fún àlùfáà yóò jẹ́ ti àlùfáà.’”
Iheo cia o mũndũ iria nyamũre nĩ ciake we mwene, no kĩrĩa angĩhe mũthĩnjĩri-Ngai, gĩgaatuĩka kĩa mũthĩnjĩri-Ngai ũcio.’”
11 Olúwa sọ fún Mose wí pé,
Ningĩ Jehova akĩĩra Musa atĩrĩ,
12 “Bá àwọn ọmọ Israẹli sọ̀rọ̀ kí o sọ fún wọn pé, ‘Bí ìyàwó ọkùnrin kan bá yapa tó sì ṣe àìṣòótọ́ sí i,
“Arĩria andũ a Isiraeli, ũmeere atĩrĩ: ‘Mũtumia wa mũndũ angĩhĩngĩcania mĩthiĩre yake, atuĩke ti mwĩhokeku harĩ we
13 nípa mímú kí ọkùnrin mìíràn bá a lòpọ̀ tí ó sì fi èyí pamọ́ fún ọkọ rẹ̀, tí a kò si gbá a mú nínú ìwà àìmọ́ rẹ̀ (nítorí pé kò sí ẹlẹ́rìí àti pé wọn kò ká a mọ́ nígbà tí ó ń dẹ́ṣẹ̀ náà).
na ũndũ wa gũkoma na mũndũ ũngĩ, na ũndũ ũcio ũhithwo mũthuuriwe na thaahu wake wage kũmenyeka (tondũ hatirĩ mũira wa kũmuumbũra, na ndaakorereirwo agĩĩka ũndũ ũcio-rĩ),
14 Ṣùgbọ́n tí ẹ̀mí owú jíjẹ bá bà lé ọkọ rẹ̀ dé bi pé ó ń funra sí ìyàwó rẹ̀ yìí tí ìyàwó rẹ̀ sì wà ní àìmọ́ nítòótọ́, tàbí tí ẹ̀mí owú bá bà lé ọkùnrin kan tó sì ń jowú ìyàwó rẹ̀ bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé ó wà ní mímọ́,
na mũthuuriwe aiguĩre mũtumia wake ũiru na amwĩkũũĩre atĩ nĩethaahĩtie, kana amũiguĩre ũiru na amwĩkũũĩre o na akorwo atethaahĩtie,
15 nígbà náà ni ọkùnrin yìí yóò mú ìyàwó rẹ̀ lọ sọ́dọ̀ àlùfáà. Ọkùnrin náà yóò sì mú ọrẹ tí a yàn fún obìnrin náà, ìdámẹ́wàá òsùwọ̀n efa ìyẹ̀fun barle. Kò gbọdọ̀ da òróró sí i, bẹ́ẹ̀ ni kò gbọdọ̀ fi tùràrí dídùn sí i nítorí pé ẹbọ ohun jíjẹ fún owú ni, èyí ti n mú ẹ̀ṣẹ̀ wá sí ìrántí.
hĩndĩ ĩyo nĩatware mũtumia wake harĩ mũthĩnjĩri-Ngai. Ningĩ no nginya atware gĩcunjĩ gĩa ikũmi kĩa eba ĩmwe ya mũtu wa cairi nĩ ũndũ wa mũtumia wake. Ndagaitĩrĩrie mũtu ũcio maguta kana awĩkĩre ũbumba, nĩ ũndũ rĩu nĩ iruta rĩa mũtu rĩrutagwo nĩ ũndũ wa ũiru, iruta rĩa mũtu rĩa kĩririkano, rĩa kũririkanania ihĩtia rĩu.
16 “‘Àlùfáà yóò sì mú un wá síwájú Olúwa.
“‘Mũthĩnjĩri-Ngai nĩagatwara mũtumia ũcio amũrũgamie mbere ya Jehova.
17 Àlùfáà yóò sì bu erùpẹ̀ ilẹ̀ àgọ́ sínú omi mímọ́ tó bù láti ìkòkò amọ̀.
Acooke oe maaĩ maamũre marĩ ndigithũ-inĩ ya rĩũmba, na ahakũre rũkũngũ hau thĩ ya Hema-ĩrĩa-Nyamũre arwĩkĩre maaĩ-inĩ macio.
18 Lẹ́yìn èyí, àlùfáà yóò mú obìnrin náà dúró níwájú Olúwa yóò sì tú irun orí obìnrin náà lé e lọ́wọ́, èyí ni ẹbọ ohun jíjẹ ti owú, àlùfáà fúnra rẹ̀ yóò sì gbé omi kíkorò tí ń mú ègún lọ́wọ́.
Mũthĩnjĩri-Ngai aarĩkia kũrũgamia mũtumia ũcio mbere ya Jehova, nĩakamuohora njuĩrĩ yake, acooke amũnengere iruta rĩu rĩa kĩririkano rĩa mũtu nĩ ũndũ wa ũiru arĩnyiite na moko, nake mũthĩnjĩri-Ngai we mwene akorwo anyiitĩte maaĩ macio marũrũ marĩa marehaga kĩrumi.
19 Àlùfáà yóò sì mú obìnrin náà búra, yóò wí pé, “Bí ọkùnrin mìíràn kò bá bá ọ lòpọ̀, tí ó kò sì yapa, tí o kò sì di aláìmọ́ níwọ̀n ìgbà tí ó wà lábẹ́ àṣẹ ọkọ rẹ̀, a jẹ́ pé omi kíkorò tí ń mú ègún wá yìí kò ní ṣe ọ́ níbi.
Mũthĩnjĩri-Ngai acooke ehĩtithie mũtumia ũcio, amwĩre atĩrĩ, “Angĩkorwo hatirĩ mũndũ ũngĩ ũkomete nawe, na ndũhĩngĩcanĩtie mĩthiĩre yaku ũgethaahia hĩndĩ ĩrĩa ũrĩ na mũthuuri-rĩ, maaĩ maya marũrũ marĩa marehaga kĩrumi maroaga gũgwĩka ũũru.
20 Ṣùgbọ́n tí ìwọ bá ti yapa kúrò lọ́dọ̀ ọkọ rẹ, tí o bá ti ba ara rẹ jẹ́ nípa jíjẹ́ kí ọkùnrin tí kì í ṣe ọkọ rẹ bá ọ lòpọ̀,”
No angĩkorwo nĩũhĩngĩcanĩtie mĩthiĩre yaku ũrĩ na mũthuuri na ũgethaahia nĩ ũndũ wa gũkoma na mũndũ ũngĩ tiga mũthuuriguo-rĩ,”
21 nígbà náà ni àlùfáà yóò mú obìnrin náà búra, yóò sọ fún obìnrin náà pé, “Kí Olúwa sọ ọ́ di ẹni ègún àti ẹni ìbáwí láàrín àwọn ènìyàn rẹ nípa mímú kí itan rẹ jẹrà, kí ikùn rẹ̀ sì wú.
hĩndĩ ĩyo mũthĩnjĩri-Ngai nĩakehĩtithia mũtumia ũcio na mwĩhĩtwa ũyũ ũrehanagĩra kĩrumi, oige atĩrĩ, “Jehova arotũma andũ anyu makũrume na magũkaane, rĩrĩa agaatũma kĩero gĩaku kĩhinyare na nda yaku ĩimbe.
22 Ǹjẹ́ kí omi yìí tí ń mú ègún wá wọ inú ara rẹ, kí ó mú ikùn rẹ̀ wú, kí ó sì mú itan rẹ̀ jẹrà dànù.” “‘Obìnrin náà yóò sì wí pé, “Àmín. Bẹ́ẹ̀ ni kó rí.”
Namo maaĩ maya marehaga kĩrumi marotoonya mwĩrĩ waku, nayo nda yaku ĩimbe na kĩero gĩaku kĩhinyare.” “‘Nake mũtumia ũcio acooke oige atĩrĩ, “Ameni, nĩgũtuĩke ũguo.”
23 “‘Nígbà náà ni àlùfáà yóò kọ ègún yìí sínú ìwé kíká, yóò sì sìn ín sínú omi kíkorò náà.
“‘Mũthĩnjĩri-Ngai nĩakandĩka irumi icio ibuku-inĩ rĩa gĩkũnjo, acooke acithambĩrie maaĩ-inĩ macio marũrũ.
24 Àlùfáà yóò sì mú kí obìnrin náà mu omi kíkorò tí ń mú ègún wá yìí, omi náà yóò wọ inú rẹ̀ yóò sì fa ìrora kíkorò fún obìnrin náà bí ó bá jẹ̀bi.
Nĩagatũma mũtumia ũcio anyue maaĩ macio marũrũ marehaga kĩrumi, namo maaĩ macio mamũtoonye na matũme aigue ruo rũnene mũno.
25 Àlùfáà yóò gba ọrẹ ohun jíjẹ owú náà lọ́wọ́ rẹ̀, yóò fì í síwájú Olúwa, yóò sì mú iná sórí pẹpẹ.
Mũthĩnjĩri-Ngai acooke oe iruta rĩu rĩa mũtu nĩ ũndũ wa ũiru kuuma moko-inĩ ma mũtumia ũcio, arĩthũngũthie mbere ya Jehova, na acooke arĩrehe kĩgongona-inĩ.
26 Àlùfáà yóò bu ẹ̀kúnwọ́ kan nínú ọrẹ ohun jíjẹ náà, yóò sun ún lórí pẹpẹ gẹ́gẹ́ bí ẹbọ ìrántí lẹ́yìn tí ó ti mú kí obìnrin náà mu omi.
Ningĩ mũthĩnjĩri-Ngai ũcio arũme ngundi ĩmwe ya mũtu ũcio ũrutĩtwo ũrĩ wa kĩririkano na aũcinĩre igũrũ rĩa kĩgongona; thuutha ũcio atũme mũtumia ũcio anyue maaĩ macio.
27 Bí ó bá ti mú obìnrin yìí mu omi náà, bí ó bá sì jẹ́ pé obìnrin náà ti ba ara rẹ̀ jẹ́, tí ó sì ṣe àìṣòótọ́ sí ọkọ rẹ̀, omi tí ń mú ègún wá, yóò wọ ara rẹ̀, yóò fa ìrora kíkorò fún un, ikùn rẹ̀ yóò wú, itan rẹ̀ yóò sì jẹrà dànù, yóò sì di ẹni ègún láàrín àwọn ènìyàn rẹ̀.
Angĩkorwo nĩethaahĩtie na ti mwĩhokeku harĩ mũthuuriwe-rĩ, rĩrĩa akaanyuithio maaĩ macio marehaga kĩrumi, nĩ makaamũtoonya matũme aigue ruo rũnene mũno, na nda yake ĩimbe na kĩero gĩake kĩhinyare, nake atuĩke thaahu kũrĩ andũ ao.
28 Ṣùgbọ́n tó bá jẹ́ pé obìnrin náà kò ba ara rẹ̀ jẹ́, tó sì jẹ́ mímọ́, yóò bọ́ nínú ẹ̀bi, yóò sì le bímọ.
No rĩrĩ, angĩkorwo mũtumia ũcio ndethaahĩtie na akorwo nĩ mũthingu-rĩ, ndagatuuo mũhĩtia, na nĩakahota kũgĩa na ciana.
29 “‘Èyí ni òfin owú jíjẹ nígbà tí obìnrin tó wà lábẹ́ ọkọ bá ṣe a ṣe má ṣe, tí ó bá ba ara rẹ̀ jẹ́,
“‘Ũyũ nĩguo watho wa ũiru rĩrĩa mũtumia angĩhĩngĩcania mĩthiĩre yake, ethaahie o arĩ na mũthuuri,
30 tàbí nígbà tí ẹ̀mí owú jíjẹ bá bà lé ọkùnrin kan nítorí pé ó funra sí ìyàwó rẹ̀. Àlùfáà yóò mú obìnrin náà dúró níwájú Olúwa yóò sì ṣe gẹ́gẹ́ bí òfin ti wí fún un.
kana rĩrĩa mũndũ mũrũme angĩnyiitwo nĩ ũiru nĩ ũndũ nĩegwĩkũũa mũtumia ũcio wake. Mũthĩnjĩri-Ngai arĩmũrũgamagia mbere ya Jehova na arũmĩrĩre watho ũcio wothe.
31 Ara ọkọ rẹ̀ mọ́ nínú ẹ̀ṣẹ̀ yìí ṣùgbọ́n obìnrin náà yóò ru ẹ̀bi ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀.’”
Mũthuuriwe nĩagatuuo ndarĩ na ihĩtia o na rĩrĩkũ, no mũtumia ũcio nĩwe ũgaacookererwo nĩ mehia make.’”

< Numbers 5 >