< Numbers 36 >

1 Àwọn olórí ìdílé Gileadi, ọmọkùnrin Makiri ọmọ Manase tí ó wá láti ara ìdílé ìran Josẹfu wá, wọ́n sì sọ̀rọ̀ níwájú Mose àti àwọn olórí, àwọn ìdílé Israẹli.
Atongoria a nyũmba cia mbarĩ ya Gileadi mũrũ wa Makiru, mũrũ wa Manase, arĩa maarĩ a mbarĩ cia njiaro cia Jusufu, nĩmathiire na makĩaria marĩ mbere ya Musa na atongoria arĩa matongoragia nyũmba cia andũ a Isiraeli.
2 Wọ́n sọ pé, “Nígbà tí Olúwa pàṣẹ fún olúwa mi láti fi ilẹ̀ yìí fún àwọn ọmọ Israẹli gẹ́gẹ́ bí ogún nípa kèké ṣíṣẹ́. Ó pa á láṣẹ fún ọ láti fi ogún Selofehadi arákùnrin wa fún àwọn ọmọbìnrin rẹ̀.
Makiuga atĩrĩ, “Rĩrĩa Jehova aathire mwathi wakwa aheane bũrũri ũtuĩke igai rĩa andũ a Isiraeli na ũndũ wa gũcuukĩra mĩtĩ-rĩ, Jehova nĩagwathire ũheane igai rĩa mũrũ wa ithe witũ Zelofehadi kũrĩ airĩtu ake.
3 Wàyí, tí wọn bá fẹ́ ọkùnrin láti ẹ̀yà Israẹli mìíràn; nígbà náà a ó gba ogún un wọn kúrò nínú ogún ìran wa, a ó sì fi kún ogún ẹ̀yà tí a fẹ́ wọn sí. Bẹ́ẹ̀ ni a ó sì gbà á kúrò nínú ìpín ilẹ̀ ogún ti wa.
Na rĩrĩ, mangĩkaahikio nĩ andũ a mĩhĩrĩga ĩyo ĩngĩ ya andũ a Isiraeli, hĩndĩ ĩyo igai rĩao nĩrĩkeherio igai-inĩ rĩa maithe maitũ rĩonganĩrĩrio na igai rĩa mũhĩrĩga ũrĩa makaahikĩra. Nĩ ũndũ ũcio-rĩ, gĩcunjĩ kĩa igai rĩrĩa twagaĩirwo nĩrĩkeherio.
4 Nígbà tí ọdún ìdásílẹ̀ àwọn ọmọ Israẹli bá dé, a ó pa ogún wọn pọ̀ mọ́ ẹ̀yà tí wọ́n fẹ́ wọn sí, a ó sì gba ogún ẹ̀yà wọn kúrò lọ́wọ́ baba ńlá wọn.”
Rĩrĩa mwaka wa Jubilii wa andũ a Isiraeli ũgaakinya-rĩ, igai rĩao nĩrĩkonganĩrĩrio na igai rĩa mũhĩrĩga ũrĩa makaahikĩra, narĩo igai rĩao rĩeherio kuuma kũrĩ igai rĩa mũhĩrĩga wa maithe maitũ.”
5 Gẹ́gẹ́ bí àṣẹ Olúwa, Mose pàṣẹ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, “Ohun ti ẹ̀yà àwọn ìran Josẹfu ń sọ tọ̀nà.
Nake Musa, kũringana na watho wa Jehova, agĩatha andũ a Isiraeli, akĩmeera atĩrĩ, “Ũguo mũhĩrĩga wa njiaro cia Jusufu ũroiga nĩ ũndũ wa kĩhooto.
6 Èyí ni ohun tí Olúwa pàṣẹ fún àwọn ọmọbìnrin Selofehadi: wọ́n lè fẹ́ ẹni tí ọkàn wọn fẹ́, kìkì pé wọ́n fẹ́ nínú ẹ̀yà ìdílé baba wọn.
Ũũ nĩguo Jehova athanĩte nĩ ũndũ wa airĩtu a Zelofehadi: No mahikĩre mũndũ o wothe ũrĩa mangĩĩendera, angĩkorwo mekũhika thĩinĩ wa mũhĩrĩga wa ithe wao.
7 Kò sí ogún kan ní Israẹli tí ó gbọdọ̀ kọjá láti ẹ̀yà kan sí ẹ̀yà mìíràn, nítorí gbogbo ọmọ Israẹli ni yóò fi ilẹ̀ ogún ẹ̀yà tí wọ́n jogún láti ọ̀dọ̀ baba ńlá wọn pamọ́.
Gũtirĩ igai thĩinĩ wa Isiraeli rĩkoima mũhĩrĩga ũmwe rĩtuĩke rĩa mũhĩrĩga ũngĩ, nĩgũkorwo Mũisiraeli o wothe nĩagatũũria gĩthaka kĩa mũhĩrĩga kĩrĩa maagaire kuuma kũrĩ maithe mao ma tene.
8 Gbogbo ọmọbìnrin tí ó bá jogún ilẹ̀ nínú ẹ̀yà Israẹli kọ̀ọ̀kan gbọdọ̀ fẹ́ ènìyàn nínú ẹ̀yà ìdílé baba rẹ̀, kí gbogbo ọmọ Israẹli lè ní ìpín nínú ogún baba wọn.
Mũirĩtu o wothe ũkaagaya gĩthaka mũhĩrĩga-inĩ o wothe wa Isiraeli, no nginya ahikĩre mũndũ wa nyũmba ya mũhĩrĩga wa ithe, nĩgeetha Mũisiraeli o wothe atũũre enyiitĩire igai rĩa maithe.
9 Kò sí ogún kankan tí ó gbọdọ̀ kọjá láti ẹ̀yà kan sí ẹ̀yà òmíràn, nítorí olúkúlùkù ẹ̀yà ọmọ Israẹli gbọdọ̀ tọ́jú ilẹ̀ tí ó jogún.”
Gũtirĩ igai rĩkoima mũhĩrĩga ũmwe rĩtuĩke rĩa mũhĩrĩga ũngĩ, nĩgũkorwo o mũhĩrĩga wa andũ a Isiraeli ũrĩtũũragia gĩthaka kĩrĩa ũgaĩte.”
10 Nígbà náà, àwọn ọmọbìnrin Selofehadi ṣe gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti pa á láṣẹ fún Mose.
Nĩ ũndũ ũcio airĩtu acio a Zelofehadi magĩĩka o ta ũrĩa Jehova aathĩte Musa.
11 Nítorí pé a gbé Mahila, Tirsa, Hogla, Milka, àti Noa, àwọn ọmọbìnrin Selofehadi ní ìyàwó fún àwọn ọmọ arákùnrin baba wọn.
Airĩtu a Zelofehadi, nĩo Mahala, na Tiriza, na Hogila, na Milika, na Noa, maahikirio nĩ ariũ a mũrũ wa nyina na ithe wao.
12 Wọ́n fẹ́ ọkọ nínú ìdílé ìran Manase, ọmọ Josẹfu ogún wọn kù nínú ìdílé àti ẹ̀yà baba wọn.
Maahikire thĩinĩ wa mbarĩ cia njiaro cia Manase mũrũ wa Jusufu, narĩo igai rĩao rĩgĩikara mbarĩ-inĩ na mũhĩrĩga-inĩ wa ithe wao.
13 Wọ̀nyí ni àṣẹ àti ìdájọ́ tí Olúwa ti ipasẹ̀ Mose fún àwọn ọmọ Israẹli ní pẹ̀tẹ́lẹ̀ Moabu lẹ́bàá Jordani létí Jeriko.
Macio nĩmo mawatho na matuĩro ma kũrũmĩrĩrwo marĩa Jehova aathire Musa eere andũ a Isiraeli marĩ kũu werũ wa Moabi hũgũrũrũ-inĩ cia Rũũĩ rwa Jorodani mũrĩmo ũrĩa ũngĩ wa Jeriko.

< Numbers 36 >