< Numbers 34 >

1 Olúwa sọ fún Mose pé,
Și DOMNUL i-a vorbit lui Moise, spunând:
2 “Pàṣẹ fún àwọn ọmọ Israẹli, kí o sì sọ fún wọn pé, ‘Tí ẹ bá wọ Kenaani, ilẹ̀ tí a ó fi fún yín, gẹ́gẹ́ bí ogún yín yóò ní ààlà wọn yí:
Poruncește copiilor lui Israel și spune-le: Când intrați în țara lui Canaan; (aceasta este țara care vă va cădea drept moștenire, țara lui Canaan cu granițele ei; )
3 “‘Ìhà gúúsù yín yóò bọ́ sí ara aginjù Sini lẹ́bàá Edomu, àti ìlà-oòrùn, ààlà ìhà gúúsù yóò bẹ̀rẹ̀ láti òpin Òkun Iyọ̀,
Atunci partea voastră de sud va fi de la pustiul Țin de-a lungul ținutului lui Edom și granița de sud va fi marginea cea mai depărtată a Mării Sărate spre est;
4 kọjá lọ sí gúúsù Akrabbimu, tẹ̀síwájú lọ si Sini, kó bọ́ si gúúsù Kadeṣi-Barnea, kí o sì dé Hasari-Addari, kí o sì kọjá sí Asmoni.
Și granița voastră se va întoarce de la sud la înălțimea Acrabim și va trece la Țin; și ieșirea lui va fi de la sud la Cades-Barnea și va merge la Hațar-Adar și va trece până la Ațmon;
5 Kí òpin ilẹ̀ rẹ̀ kí ó sì yíká láti Asmoni lọ dé odò Ejibiti, Òkun Ńlá ni yóò sì jẹ òpin rẹ.
Și granița să facă o rotire de la Ațmon până la râul Egiptului și ieșirile ei vor fi la mare.
6 Ìhà ìwọ̀-oòrùn yín yóò jẹ́ òpin lórí Òkun Ńlá. Èyí yóò jẹ́ ààlà yín lórí ìhà ìwọ̀-oòrùn.
Iar cât despre granița de vest, veți avea marea cea mare drept graniță; aceasta va fi granița voastră de vest.
7 Fún ààlà ìhà àríwá, fa ìlà láti Òkun Ńlá lọ sí orí òkè Hori,
Și aceasta va fi granița voastră de nord: de la marea cea mare vă veți însemna muntele Hor;
8 àti láti orí òkè Hori sí Lebo-Hamati. Nígbà náà ààlà náà yóò lọ sí Sedadi,
De la muntele Hor veți însemna granița voastră până la intrarea la Hamat; și ieșirile graniței vor fi la Țedad;
9 tẹ̀síwájú lọ sí Sifroni, kí o sì fò pín si ní Hasari-Enani, èyí yóò jẹ́ ààlà tìrẹ ní ìhà àríwá.
Și granița va merge la Zifron și ieșirile ei vor fi la Hațar-Enan, aceasta va fi granița voastră de nord.
10 Kí ẹ sì sàmì sí ilẹ̀ tiyín ní ìhà ìlà-oòrùn láti Hasari-Enani lọ dé Ṣefamu.
Și veți însemna granița voastră de est de la Hațar-Enan până la Șefam;
11 Ààlà náà yóò ti Ṣefamu sọ̀kalẹ̀ wá lọ sí Ribla ní ìhà ìlà-oòrùn Aini, kí o sì sọ̀kalẹ̀ lọ dé ìhà Òkun Kinnereti ní ìhà ìlà-oòrùn.
Și ținutul va merge în jos de la Șefam la Ribla, pe partea de est a Ainului; și granița va coborî și va ajunge până la țărmul mării Chineret spre est;
12 Nígbà náà, ààlà náà yóò sọ̀kalẹ̀ lọ sí apá Jordani, yóò sì dópin nínú Òkun Iyọ̀. “‘Èyí yóò jẹ́ ilẹ̀ yín, pẹ̀lú ààlà tirẹ̀ ní gbogbo ọ̀nà.’”
Și granița va coborî la Iordan și ieșirile ei vor fi la Marea Sărată, aceasta va fi țara voastră cu granițele ei de jur împrejurul ei.
13 Mose pa á láṣẹ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, “Yan ilẹ̀ yìí pẹ̀lú kèké gẹ́gẹ́ bí ìní ogún: Olúwa ti pàṣẹ láti fi fún ẹ̀yà mẹ́sàn-án, àti ààbọ̀.
Și Moise le-a poruncit copiilor lui Israel, spunând: Aceasta este țara pe care o veți moșteni prin sorț, despre care DOMNUL a poruncit să fie dată celor nouă seminții și la o jumătate de trib;
14 Nítorí ará ilẹ̀ ẹ̀yà ti Reubeni, ẹ̀yà Gadi àti ẹ̀yà ààbọ̀ ti Manase ti gba ogún tiwọn.
Pentru că tribul copiilor lui Ruben conform cu casa părinților lor și tribul copiilor lui Gad conform cu casa părinților lor, au primit moștenirea lor; și jumătate din tribul lui Manase au primit moștenirea lor;
15 Ẹ̀yà méjèèjì àti ààbọ̀ yìí ti gba ogún tiwọn ní ìhà ìhín Jordani létí i Jeriko, ní ìhà ìlà-oòrùn, ní ìdojúkọ Jordani.”
Cele două triburi și jumătatea de trib au primit moștenirea lor de această parte a Iordanului, lângă Ierihon spre est, spre răsăritul soarelui.
16 Olúwa sọ fún Mose pé,
Și DOMNUL i-a vorbit lui Moise, spunând:
17 “Èyí ni orúkọ àwọn ọkùnrin náà tí yóò pín ilẹ̀, náà fún yín gẹ́gẹ́ bí ogún: Eleasari àlùfáà àti Joṣua ọmọ Nuni.
Acestea sunt numele bărbaților care vă vor împărți țara: preotul Eleazar și Iosua, fiul lui Nun.
18 Kí o sì yan olórí kan nínú ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan láti pín ilẹ̀ náà.
Și să luați câte un prinț din fiecare trib, să împartă țara prin moștenire.
19 “Èyí ni orúkọ wọn: “Kalebu ọmọ Jefunne, láti ẹ̀yà Juda;
Și numele bărbaților sunt acestea: din tribul lui Iuda: Caleb, fiul lui Iefune.
20 Ṣemueli ọmọ Ammihudu, láti ẹ̀yà Simeoni;
Și din tribul copiilor lui Simeon: Șemuel, fiul lui Amihud.
21 Elidadi ọmọ Kisloni, láti ẹ̀yà Benjamini;
Din tribul lui Beniamin: Elidad, fiul lui Chislon.
22 Bukki ọmọ Jogli, láti ẹ̀yà olórí àwọn ọmọ Dani;
Și prințul tribului copiilor lui Dan: Buchi, fiul lui Iogli.
23 Hannieli ọmọ Efodu, láti ẹ̀yà Manase, olórí àwọn ọmọ Josẹfu,
Prințul copiilor lui Iosif, pentru tribul copiilor lui Manase: Haniel, fiul lui Efod.
24 Kemueli ọmọ Ṣiftani, olórí ẹ̀yà àwọn ọmọ, Efraimu, ọmọ Josẹfu;
Și prințul tribului copiilor lui Efraim: Chemuel, fiul lui Șiftan.
25 Elisafani ọmọ Parnaki, olórí ẹ̀yà àwọn ọmọ Sebuluni;
Și prințul tribului copiilor lui Zabulon: Elițafan, fiul lui Parnac.
26 Paltieli ọmọ Assani, olórí ẹ̀yà àwọn ọmọ Isakari;
Și prințul tribului copiilor lui Isahar: Paltiel, fiul lui Azan.
27 Ahihudu ọmọ Ṣelomi, olórí ẹ̀yà àwọn ọmọ Aṣeri;
Și prințul tribului copiilor lui Așer: Ahihud, fiul lui Șelomi.
28 Pedaheli ọmọ Ammihudu, olórí ẹ̀yà àwọn ọmọ Naftali.”
Și prințul tribului copiilor lui Neftali: Pedahel, fiul lui Amihud.
29 Èyí ni àwọn ẹni tí Olúwa yàn láti pín ogún náà fún àwọn ọmọ Israẹli ní ilẹ̀ Kenaani.
Aceștia sunt cei cărora DOMNUL le-a poruncit să împartă moștenirea copiilor lui Israel în țara lui Canaan.

< Numbers 34 >