< Numbers 34 >
OLELO mai la o Iehova ia Mose, i mai la,
2 “Pàṣẹ fún àwọn ọmọ Israẹli, kí o sì sọ fún wọn pé, ‘Tí ẹ bá wọ Kenaani, ilẹ̀ tí a ó fi fún yín, gẹ́gẹ́ bí ogún yín yóò ní ààlà wọn yí:
E kauoha aku oe i na mamo a Iseraela, a e i aku ia lakou, Aia hiki aku oukou iloko o ka aina o Kanaana; (oia ka aina e lilo ana no oukou i noho ana, o ka aina o Kanaana, a me kona mau mokuna: )
3 “‘Ìhà gúúsù yín yóò bọ́ sí ara aginjù Sini lẹ́bàá Edomu, àti ìlà-oòrùn, ààlà ìhà gúúsù yóò bẹ̀rẹ̀ láti òpin Òkun Iyọ̀,
Alaila, o ko oukou aoao hema, aia no ia mai ka waonahele o Zina, e pili ana i ka palena o Edoma: a o ko oukou mokuna hema ma ke kihi loa o ka moanakai, a moe aku i ka hikina:
4 kọjá lọ sí gúúsù Akrabbimu, tẹ̀síwájú lọ si Sini, kó bọ́ si gúúsù Kadeṣi-Barnea, kí o sì dé Hasari-Addari, kí o sì kọjá sí Asmoni.
A e huli ae ko oukou palena mai ka aoao hema ae i ka puu o Akerabima, a hele aku i Zina: a o ka hele ana aku oia mai ka aoao hema aku a Kadesa-banea, a e hele hou aku ia i Hazaradara, a hiki aku i Azemona:
5 Kí òpin ilẹ̀ rẹ̀ kí ó sì yíká láti Asmoni lọ dé odò Ejibiti, Òkun Ńlá ni yóò sì jẹ òpin rẹ.
A hele poai aku no ka palena mai Azemona aku a ke kahawai o Aigupita, a e puka aku no ia i ke kai.
6 Ìhà ìwọ̀-oòrùn yín yóò jẹ́ òpin lórí Òkun Ńlá. Èyí yóò jẹ́ ààlà yín lórí ìhà ìwọ̀-oòrùn.
A o ka palena komohana, o ke kai nui ko oukou palena: oia ko oukou palena komohana.
7 Fún ààlà ìhà àríwá, fa ìlà láti Òkun Ńlá lọ sí orí òkè Hori,
Eia hoi ko oukou palena akau: mai ke kai nui aku, e hoailona oukou i ka mauna Hora no oukou.
8 àti láti orí òkè Hori sí Lebo-Hamati. Nígbà náà ààlà náà yóò lọ sí Sedadi,
Mai ka mauna Hora aku, e hoailona oukou a hiki i ke komo ana o Hamata: a e hele aku no ka palena a hiki i Zedada.
9 tẹ̀síwájú lọ sí Sifroni, kí o sì fò pín si ní Hasari-Enani, èyí yóò jẹ́ ààlà tìrẹ ní ìhà àríwá.
A e hele hou aku no ka palena i Ziperona, a e puka aku no ia i Hazarenana: oia ko oukou palena akau.
10 Kí ẹ sì sàmì sí ilẹ̀ tiyín ní ìhà ìlà-oòrùn láti Hasari-Enani lọ dé Ṣefamu.
A e hoailona oukou i ko oukou palena hikina, mai Hazarenana a Sepama.
11 Ààlà náà yóò ti Ṣefamu sọ̀kalẹ̀ wá lọ sí Ribla ní ìhà ìlà-oòrùn Aini, kí o sì sọ̀kalẹ̀ lọ dé ìhà Òkun Kinnereti ní ìhà ìlà-oòrùn.
A e hele aku ka palena mai Sepama a Ribela, ma ka aoao hikina o Aina: a e iho aku ka palena, a hiki aku ma ka aoao o ka loko o Kinerota ma ka hikina.
12 Nígbà náà, ààlà náà yóò sọ̀kalẹ̀ lọ sí apá Jordani, yóò sì dópin nínú Òkun Iyọ̀. “‘Èyí yóò jẹ́ ilẹ̀ yín, pẹ̀lú ààlà tirẹ̀ ní gbogbo ọ̀nà.’”
A e iho aku ka palena i Ioredane, a o kona puka ana aku ma ka moana paakai: oia ko oukou aina me na mokuna a puni.
13 Mose pa á láṣẹ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, “Yan ilẹ̀ yìí pẹ̀lú kèké gẹ́gẹ́ bí ìní ogún: Olúwa ti pàṣẹ láti fi fún ẹ̀yà mẹ́sàn-án, àti ààbọ̀.
Kauoha aku la o Mose i na mamo a Iseraela, i aku la, Eia no ka aina e ili mai ana na oukou ma ka hailona ana, ka aina a Iehova i kauoha mai ai e haawi aku no na ohana eiwa, a no ka ohana hapa.
14 Nítorí ará ilẹ̀ ẹ̀yà ti Reubeni, ẹ̀yà Gadi àti ẹ̀yà ààbọ̀ ti Manase ti gba ogún tiwọn.
No ka mea, ua loaa i ka ohana mamo a Reubena ma ka hale o ko lakou poe makua, a i ka ohana mamo a Gada, ma ka hale o ko lakou poe makua, a i ka ohana hapa a Manase, ko lakou aina hooili.
15 Ẹ̀yà méjèèjì àti ààbọ̀ yìí ti gba ogún tiwọn ní ìhà ìhín Jordani létí i Jeriko, ní ìhà ìlà-oòrùn, ní ìdojúkọ Jordani.”
Ua loaa i na ohana elua a me ka ohana hapa ko lakou aina hooili ma keia aoao o Ioredane, ma Ieriko a ka hikina aku, ma ka puka ana o ka la.
Olelo mai la o Iehova ia Mose, i mai la,
17 “Èyí ni orúkọ àwọn ọkùnrin náà tí yóò pín ilẹ̀, náà fún yín gẹ́gẹ́ bí ogún: Eleasari àlùfáà àti Joṣua ọmọ Nuni.
Eia na inoa o na kanaka nana e puunaue i ka aina no oukou: o Eleazara ke kahuna, a me Iosua ke keiki a Nuna.
18 Kí o sì yan olórí kan nínú ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan láti pín ilẹ̀ náà.
A e lawe hoi oukou i kekahi luna o kela ohana o keia ohana e puunaue i ka aina, ma na puu e ili ana.
19 “Èyí ni orúkọ wọn: “Kalebu ọmọ Jefunne, láti ẹ̀yà Juda;
Eia hoi na inoa o na kanaka: no ka ohana a Iuda, o Kaleba ke keiki a Iepune.
20 Ṣemueli ọmọ Ammihudu, láti ẹ̀yà Simeoni;
A no ka ohana mamo a Simeona, o Semuela ke keiki a Amihuda.
21 Elidadi ọmọ Kisloni, láti ẹ̀yà Benjamini;
No ka ohana a Beniamina, o Elidada ke keiki a Kiselona.
22 Bukki ọmọ Jogli, láti ẹ̀yà olórí àwọn ọmọ Dani;
A o ka luna ohana o na mamo a Dana, o Buki ke keiki a Iogeli.
23 Hannieli ọmọ Efodu, láti ẹ̀yà Manase, olórí àwọn ọmọ Josẹfu,
O ka luna o na mamo a Iosepa, no ka ohana mamo a Manase, o Haniela ke keiki a Epoda.
24 Kemueli ọmọ Ṣiftani, olórí ẹ̀yà àwọn ọmọ, Efraimu, ọmọ Josẹfu;
A o ka luna ohana o na mamo a Eperaima, o Kemuela ke keiki a Sipetana.
25 Elisafani ọmọ Parnaki, olórí ẹ̀yà àwọn ọmọ Sebuluni;
A o ka luna ohana o na mamo a Zebuluna, o Elizapana ke keiki a Parenaka.
26 Paltieli ọmọ Assani, olórí ẹ̀yà àwọn ọmọ Isakari;
A o ka luna ohana o na mamo a Isakara, o Paletiela ke keiki a Azana.
27 Ahihudu ọmọ Ṣelomi, olórí ẹ̀yà àwọn ọmọ Aṣeri;
A o ka luna ohana o na mamo a Asera, o Ahihuda ke keiki a Selomi.
28 Pedaheli ọmọ Ammihudu, olórí ẹ̀yà àwọn ọmọ Naftali.”
A o ka luna ohana o na mamo a Napetali, o Pedahela ke keiki a Amihuda.
29 Èyí ni àwọn ẹni tí Olúwa yàn láti pín ogún náà fún àwọn ọmọ Israẹli ní ilẹ̀ Kenaani.
O lakou ka poe a Iehova i kauoha mai ai e puunaue i ka aina e ili mai ana maluna o na mamo a Iseraela ma ka aina o Kanaana.