< Numbers 32 >

1 Àwọn ọmọ Reubeni àti àwọn ọmọ Gadi, tí wọ́n ní ẹran ọ̀sìn àti ohun ọ̀sìn rí wí pé ilẹ̀ Jaseri àti Gileadi dára fún ohun ọ̀sìn.
HE nui loa na holoholona a na mamo a Reubena, a me na mamo a Gada: a i ka manawa i ike ai lakou i ka aina o Iazera a me ka aina o Gileada, aia hoi, he wahi pono ia no na holoholona;
2 Àwọn ọmọ Gadi àti àwọn ọmọ Reubeni sì wá, wọ́n wá sí ọ̀dọ̀ Mose àti Eleasari àlùfáà àti sí olórí gbogbo ìlú, wọ́n sì wí pé,
Hele mai la na mamo a Gada a me na mamo a Reubena, a olelo mai la ia Mose, a ia Eleazara ke kahuna, a i na luna o ke anainakanaka, i mai la,
3 “Atarotu, Diboni, Jaseri, Nimra, Heṣboni, Eleale, Sebamu, Nebo, àti Beoni.
O Atarota, o Dibona, o Iazera, o Nimera, o Hesebona, o Eleale, o Sebama, o Nebo, a o Beona,
4 Ni ilẹ̀ tí Olúwa ti ṣẹ́gun níwájú ìjọ Israẹli tí ó sì dára fún ohun ọ̀sìn, ṣáwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ sì ní ohun ọ̀sìn.”
O ka aina a Iehova i luku ai imua o ke anainakanaka o ka Iseraela, he aina ia no na holoholona; a he holoholona ia makou o kau poe kauwa.
5 Wọ́n wí pé, “Tí a bá rí ojúrere rẹ, jẹ́ kí a fi ilẹ̀ yìí fún ìránṣẹ́ rẹ gẹ́gẹ́ bí ìní. Má ṣe jẹ́ kí a rékọjá odò Jordani.”
I mai la lakou, No keia mea, a i loaa ia makou ke aloha imua o kou maka, e ae mai oe e haawiia mai keia aina i wahi e noho ai no kau mau kauwa, aole no e kai aku ia makou ma kela aoao o Ioredane.
6 Mose sọ fún àwọn ọmọ Gadi àti fún ọmọ Reubeni pé, “Ṣé kí àwọn arákùnrin yín lọ sí ogun, kí ẹ̀yin kí ó sì jókòó sí bí?
Ninau aku la o Mose i na mamo a Gada, a i na mamo a Reubena, E hele no anei ko oukou poe hoahanau i ke kaua, a e noho no oukou manei?
7 Kí ni ó dé tí o fi mú ìrẹ̀wẹ̀sì bá àwọn ọmọ Israẹli láti lọ sí ibi ilẹ̀ tí Olúwa ti fi fún wọn?
No ke aha la hoi e hoonawaliwali ai oukou i na naau o na mamo a Iseraela, i hele ole ai lakou i ka aina a Iehova i haawi mai ai no lakou?
8 Èyí ni nǹkan tí baba yín ṣe nígbà tí mo rán wọn láti Kadeṣi-Barnea láti lọ wo ilẹ̀ náà.
Pela no i hana'i ko oukou poe makua, ia'u i hoouna aku ai ia lakou mai Kadesabanea aku e makaikai i ka aina.
9 Lẹ́yìn ìgbà tí wọ́n lọ sí àfonífojì Eṣkolu tí wọ́n rí ilẹ̀ náà, wọ́n mú ìrẹ̀wẹ̀sì bá àwọn ọmọ Israẹli láti wọ ilẹ̀ tí Olúwa ti fi fún wọn.
No ka mea, i ka manawa i pii aku ai lakou ma ke awawa o Esekola, a ike aku la i ka aina, hoonawaliwali lakou i ka naau o na mamo a Iseraela, i hele ole aku ai lakou i ka aina a Iehova i haawi mai ai no lakou.
10 Ìbínú Olúwa sì dìde sí wọn ní ọjọ́ náà, ó sì búra, wí pé,
A ua hoaia ka inaina o Iehova ia la, a hoohiki iho la ia, i ka i ana mai,
11 ‘Nítorí wọn kò tẹ̀lé mi tọkàntọkàn, kì í ṣe ọ̀kan nínú àwọn ọkùnrin náà tí ó jẹ́ ogún ọdún tàbí jù bẹ́ẹ̀ lọ tí ó gòkè láti Ejibiti ni yóò rí ilẹ̀ tí mo pinnu gẹ́gẹ́ bí ìbúra fún Abrahamu, fún Isaaki àti fún Jakọbu:
He oiaio, aole kekahi o na kanaka i hele mai nei mai Aigupita mai, na mea o na makahiki he iwakalua a keu aku, e ike aku i ka aina a'u i hoohiki ai no Aberahama, no Isaaka a no Iakoba; no ka mea, aole lakou i hahai pono mamuli o'u:
12 kò sí ẹnìkankan àyàfi Kalebu ọmọ Jefunne ti Kenissiti àti Joṣua ọmọ Nuni, nítorí wọ́n tẹ̀lé Olúwa tọkàntọkàn.’
O Kaleba wale no o ke keiki a Iepune ka Kenezi, laua o Iosua ke keiki a Nuna: no ka mea, ua hahai pono no laua ia Iehova.
13 Ìbínú Olúwa ru sí àwọn ọmọ Israẹli ó sì mú wọn rìn ní aginjù fún ogójì ọdún, títí tí àwọn ìran tí wọ́n ṣe búburú ní ojú rẹ̀ fi lọ.
A hoaia ka inaina o Iehova i ka Iseraela, a hoauwana ae la oia ia lakou ma ka waonahele i na makahiki he kanaha, a pau loa ae la ka hanauna a pau i hana hewa imua o Iehova.
14 “Níbí ni ẹ̀yin wà, ẹ̀yin ẹlẹ́ṣẹ̀, ẹ̀yin dìde ní ipò baba yín, ẹ sì jẹ́ kí ìbínú gbígbóná Olúwa ru sí Israẹli.
Aia hoi, ua ku ae nei oukou i pani no ka hakahaka o ko oukou poe makua, he hanauna kanaka hewa, e hoomahuahua aku i ka inaina nui o Iehova i ka Iseraela.
15 Tí ẹ̀yin bá yípadà ní ẹ̀yìn rẹ̀ yóò sì fi àwọn ènìyàn wọ̀nyí sílẹ̀ ní aginjù, ìwọ yóò sì mú un ṣe ìparun.”
No ka mea, a i huli aku oukou maimuli ona aku, e haalele hou mai auanei oia ia lakou iloko o ka waonahele, a e make keia poe kanaka a pau ia oukou.
16 Nígbà náà wọ́n wá sí òkè ní ọ̀dọ̀ rẹ̀, “Àwa yóò fẹ́ láti kọ́ ilé ẹran níhìn-ín yìí fún ohun ọ̀sìn wa, àti ìlú fún àwọn obìnrin àti ọmọ wẹ́wẹ́ wa.
Hele mai lakou a kokoke io na la, i mai la, E hana no makou i na pahipa no ko makou holoholona, a me na kulanakauhale no na keiki a makou:
17 Ṣùgbọ́n àwa ṣetán láti dira ogun ṣáájú àwọn ọmọ Israẹli títí tí a yóò fi mú wọn dé ọ̀dọ̀ wọn lákokò yìí, àwọn obìnrin àti ọmọ wẹ́wẹ́ wa yóò gbé inú ìlú tí a mọ odi sí fún ìdáàbòbò wọn lọ́wọ́ olùgbé ilẹ̀ náà.
Aka, e hele makaukau no makou i ke kaua imua o na mamo a Iseraela a alakai makou ia lakou i ko lakou wahi: a e noho na keiki a makou i na kulanakauhale i paa i ka pa, no na kanaka o ka aina.
18 A kì yóò padà sí ilẹ̀ wa láìṣe pé gbogbo àwọn ọmọ Israẹli ti gba ogún wọn.
Aole no makou e hoi hou i na hale o makou, a loaa i kela kanaka i keia kanaka o na mamo a Iseraela kona ainahooili.
19 A kì yóò gba ogún kankan pẹ̀lú wọn ní òdìkejì Jordani, nítorí ogún ti wa, ti wá sí ọ̀dọ̀ wa ní ìhà ìlà-oòrùn Jordani.”
No ka mea, aole makou e ai aina me lakou ma kela aoao o Ioredane; a ma o aku; no ka mea, ua loaa ia makou ko makou ainahooili ma keia aoao o Ioredane ma ka hikina.
20 Nígbà náà ni Mose sọ fún wọn pé, “Tí ẹ̀yin yóò bá pa ara yín lára, níwájú Olúwa fún ogún.
I aku la o Mose ia lakou, Ina paha oukou e hana ia mea, a e hele me ka makaukau i ke kaua imua o Iehova,
21 Bí gbogbo yín yóò bá lọ sí Jordani ní ìhámọ́ra níwájú Olúwa, títí yóò fi lé àwọn ọ̀tá rẹ̀ kúrò níwájú rẹ̀.
A e hele oukou a pau me ka makaukau ma kela aoao o Ioredane imua o Iehova, a pau kona poe enemi i ka hookukeia'ku e ia mai kona alo aku,
22 Tí a ó sì fi ṣe ilẹ̀ náà níwájú Olúwa; ẹ̀yin lè padà tí yóò sì di òmìnira lọ́wọ́ ìdè níwájú Olúwa àti Israẹli. Ilẹ̀ yìí yóò sì jẹ́ tiyín níwájú Olúwa.
A pio ka aina imua o Iehova; a mahope iho e hoi hou auanei oukou, me ka hala ole imua o Iehova, imua hoi o ka Iseraela: a e lilo keia aina no oukou imua o Iehova.
23 “Ṣùgbọ́n tí ẹ̀yin bá kọ̀ láti ṣe èyí, ẹ̀yin yóò máa dẹ́ṣẹ̀ sí Olúwa; kí ẹ̀yin kí ó sì mọ̀ dájú pé ẹ̀ṣẹ̀ yín yóò fi yín hàn.
Aka, i hana ole oukou pela, aia hoi, ua hana hewa aku oukou ia Iehova; a e ike pono oukou e pili auanei ko oukou hewa ia oukou iho.
24 Ẹ kọ́ ilé fún àwọn obìnrin yín àti ọmọ wẹ́wẹ́ yín, àti ilé fún agbo ẹran yín, ṣùgbọ́n kí ẹ̀yin kí ó ṣe ohun tí ẹ ti pinnu.”
E hana oukou i na kulanakauhale no na keiki a oukou, a me na pa no na hipa a oukou; a e hana oukou i ka mea a ko oukou waha i olelo mai ai.
25 Àwọn ọmọ Gadi àti ọmọ Reubeni sọ fún Mose pé, “Àwa ìránṣẹ́ rẹ yóò ṣe gẹ́gẹ́ bí olúwa wa ti pàṣẹ.
Olelo mai la na mamo a Gada, a me na mamo a Reubena, i mai la, E hana no na kauwa au e like me kuu haku i olelo mai nei.
26 Àwọn ọmọ wa àti ìyàwó wa, àwọn agbo ẹran àti ohun ọ̀sìn wa yóò dúró ní ìlú Gileadi.
O ka makou poe kamalii, o na wahine a makou, o ko makou holoholona uuku, a me ko makou holoholona nui a pan, e waihoia ilaila maloko o na kulanakauhale o Gileada:
27 Ṣùgbọ́n àwọn ìránṣẹ́ rẹ, gbogbo ọkùnrin tí ó wọ ìhámọ́ra ogun, yóò rékọjá lọ láti jà níwájú Olúwa; gẹ́gẹ́ bí olúwa wa ti sọ.”
Aka, a kau poe kauwa, o kela mea keia mea e hele makaukau imua o Iehova i ke kaua, e like me ka olelo ana mai a kuu haku.
28 Nígbà náà ni Mose pàṣẹ nípa wọn fún Eleasari àlùfáà àti Joṣua ọmọ Nuni àti sí gbogbo olórí ìdílé ẹ̀yà Israẹli.
A kauoha aku la o Mose no lakou ia Eleazara ke kahuna, a me Iosua ke keiki a Nuna, a me na lunakahiko o na ohana mamo a Iseraela:
29 Mose sì wí fún wọn pé, “Tí àwọn ọmọ Gadi àti ọmọ Reubeni, gbogbo ọkùnrin tí ó wọ ìhámọ́ra fún ogun rékọjá odò Jordani pẹ̀lú níwájú Olúwa, nígbà tí ẹ ṣẹ́gun ilẹ̀ náà níwájú yín, fún wọn ní ilẹ̀ Gileadi gẹ́gẹ́ bí ìní wọn.
I aku la o Mose ia lakou, Ina e hele pu aku me oukou na mamo a Gada, a me na mamo a Reubena ma kela aoao o Ioredane, o kela kanaka o keia kanaka me ka makaukau i ke kaua imua o Iehova, a e hoopioia ka aina imua o oukou; alaila e haawi oukou i ka aina o Gileada i kuleana no lakou:
30 Ṣùgbọ́n tí wọn kò bá fẹ́ bá yín rékọjá pẹ̀lú ìhámọ́ra, wọn gbọdọ̀ gba ìní wọn pẹ̀lú yín ní Kenaani.”
A i ole lakou e hele makaukau aku me oukou ma kela aoao, alaila e loaa ia lakou ko lakou kuleana iwaena o oukou ma ka aina o Kanaana.
31 Àwọn ọmọ Gadi àti ọmọ Reubeni dáhùn pé, “Ìránṣẹ́ rẹ yóò ṣe ohun tí Olúwa ti sọ.
Olelo mai la na mamo a Gada a me na mamo a Reubena, i mai la, E like me ka Iehova i olelo mai ai i kau poe kauwa, pela no makou e hana aku ai.
32 A máa rékọjá níwájú Olúwa lọ sí Kenaani pẹ̀lú ìhámọ́ra, ṣùgbọ́n ẹrù tí a jogún yóò wà ní ẹ̀bá Jordani.”
E hele makaukau aku no makou imua o Iehova iloko o ka aina o Kanaana, i lilo ai no makou ka aina o ko makou kuleana ma keia aoao o Ioredane.
33 Nígbà náà Mose fún àwọn ọmọ Gadi àti àwọn ọmọ Reubeni àti ààbọ̀ ẹ̀yà Manase ọmọ Josẹfu ní ilẹ̀ ọba Sihoni ọba àwọn ọmọ Amori àti ilẹ̀ ọba Ogu ọba Baṣani ní gbogbo ilẹ̀ náà pẹ̀lú ìlú rẹ̀ àti agbègbè tí ó yí i ka.
A haawi aku la o Mose no lakou, no na mamo a Gada a me na mamo a Reubena, a me ka ohana hapa a Manase a ke keiki a Iosepa, i ke aupuni o Sihona ke alii o ka Amora, a me ke aupuni o Oga ke alii o Basana, i ka aina me na kulanakauhale ona, ma ua palena, na kulanakauhale o ia aina a puni.
34 Àwọn ará Gadi wọ́n kọ́ Diboni, Atarotu, Aroeri;
A kukulu aku la na mamo a Gada ia Dibona, me Atarota, me Aroera,
35 pẹ̀lú Atrotu Ṣofani, Jaseri, àti Jogbeha,
Me Aterota, me Sopana, me Iazera, a me Iogebeha,
36 pẹ̀lú Beti-Nimra, àti Beti-Harani ìlú olódi, àti agbo fún àgùntàn.
Me Betenimera a me Beteharana, na kulanakauhale i puni i ka pa, a me na pahipa.
37 Àwọn ọmọ Reubeni sì kọ́ Heṣboni, Eleale, Kiriataimu,
A kukulu aku la na mamo a Reubena ia Hesebona, me Eleale, a me Kiriataima,
38 pẹ̀lú Nebo pẹ̀lú Baali-Meoni (wọ́n pàrọ̀ orúkọ wọn) àti Sibma. Wọ́n sì sọ ìlú tí wọ́n tún kọ́ ní orúkọ mìíràn.
A me Nebo, me Baalameona, (ua hoololiia ko lakou mau inoa, ) a me Sibema: a mamuli o ua inoa, kapa aku lakou i na inoa o na kulanakauhale a lakou i kukulu ai.
39 Àwọn ọmọ Makiri ọmọ Manase lọ sí Gileadi, wọ́n sì lé àwọn ọmọ Amori tí ó wà níbẹ̀.
A hele aku la na keiki a Makira ke keiki a Manase i Gileada, a lawe pio iho la ia wahi, a hookuke aku la i ka Amora e noho ana iloko olaila.
40 Mose sì fi àwọn ọmọ Gileadi fún àwọn ọmọ Makiri àwọn ìran Manase, wọ́n sì tẹ̀dó síbẹ̀.
A haawi aku la o Mose ia Gileada ia Makira ke keiki a Manase, a noho iho la ia ilaila.
41 Jairi, ọmọ Manase gba ibùjókòó wọn, ó sì pè wọ́n ní Haffotu Jairi.
Hele aku la hoi o Iaira ke keiki a Manase, a lawe pio aku la i na kauhale o ia wahi, a kapa aku la i ko lakou inoa, o Havota-iaira.
42 Noba gba Kenati àti àwọn ìtẹ̀dó rẹ̀, ó sì pè é ní Noba lẹ́yìn orúkọ ara rẹ̀.
A hele aku la o Noba a lawe pio aku la ia Kenata, a me na kauhale ona, a kapa aku ia wahi, o Noba, mamuli o kona inoa iho.

< Numbers 32 >