< Numbers 32 >
1 Àwọn ọmọ Reubeni àti àwọn ọmọ Gadi, tí wọ́n ní ẹran ọ̀sìn àti ohun ọ̀sìn rí wí pé ilẹ̀ Jaseri àti Gileadi dára fún ohun ọ̀sìn.
Na rĩrĩ, andũ a mĩhĩrĩga ya Rubeni na Gadi, arĩa maarĩ na ndũũru nene cia ngʼombe na cia mbũri, nĩmoonire atĩ mabũrũri ma Jazeri na Gileadi maarĩ mega na mahiũ mao.
2 Àwọn ọmọ Gadi àti àwọn ọmọ Reubeni sì wá, wọ́n wá sí ọ̀dọ̀ Mose àti Eleasari àlùfáà àti sí olórí gbogbo ìlú, wọ́n sì wí pé,
Nĩ ũndũ ũcio magĩthiĩ kũrĩ Musa na Eleazaru ũrĩa mũthĩnjĩri-Ngai, o na kũrĩ atongoria a kĩrĩndĩ, makiuga atĩrĩ,
3 “Atarotu, Diboni, Jaseri, Nimra, Heṣboni, Eleale, Sebamu, Nebo, àti Beoni.
“Atarothu, na Diboni, na Jazeri, na Nimura, na Heshiboni, na Eleale, na Sebamu, na Nebo, o na Beoni,
4 Ni ilẹ̀ tí Olúwa ti ṣẹ́gun níwájú ìjọ Israẹli tí ó sì dára fún ohun ọ̀sìn, ṣáwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ sì ní ohun ọ̀sìn.”
bũrũri ũyũ Jehova aatooririe andũ akuo mbere ya andũ a Isiraeli, nĩ kũndũ kwega kwa mahiũ, na ithuĩ ndungata ciaku tũrĩ na mahiũ.”
5 Wọ́n wí pé, “Tí a bá rí ojúrere rẹ, jẹ́ kí a fi ilẹ̀ yìí fún ìránṣẹ́ rẹ gẹ́gẹ́ bí ìní. Má ṣe jẹ́ kí a rékọjá odò Jordani.”
Makiuga atĩrĩ, “Angĩkorwo nĩtwĩtĩkĩrĩkĩte harĩ inyuĩ-rĩ, rekei bũrũri ũyũ ũheo ndungata cianyu ũtuĩke witũ. Mũtigatũme tũringe Rũũĩ rwa Jorodani.”
6 Mose sọ fún àwọn ọmọ Gadi àti fún ọmọ Reubeni pé, “Ṣé kí àwọn arákùnrin yín lọ sí ogun, kí ẹ̀yin kí ó sì jókòó sí bí?
Musa akĩũria andũ a Gadi na a Rubeni atĩrĩ, “Andũ anyu no mathiĩ ita-inĩ mamũtige mũikarĩte gũkũ?
7 Kí ni ó dé tí o fi mú ìrẹ̀wẹ̀sì bá àwọn ọmọ Israẹli láti lọ sí ibi ilẹ̀ tí Olúwa ti fi fún wọn?
Nĩ kĩĩ gĩgũtũma mũũrage ngoro cia andũ a Isiraeli nĩguo matikaringe rũũĩ matoonye bũrũri ũrĩa Jehova amaheete?
8 Èyí ni nǹkan tí baba yín ṣe nígbà tí mo rán wọn láti Kadeṣi-Barnea láti lọ wo ilẹ̀ náà.
Ũguo noguo maithe manyu meekire hĩndĩ ĩrĩa ndaamarekirie kuuma Kadeshi-Barinea mathiĩ magathigaane bũrũri ũcio.
9 Lẹ́yìn ìgbà tí wọ́n lọ sí àfonífojì Eṣkolu tí wọ́n rí ilẹ̀ náà, wọ́n mú ìrẹ̀wẹ̀sì bá àwọn ọmọ Israẹli láti wọ ilẹ̀ tí Olúwa ti fi fún wọn.
Thuutha wa kwambata, magĩkinya kĩanda kĩa Eshikoli na makĩĩrorera bũrũri ũcio-rĩ, nĩmatũmire andũ a Isiraeli makue ngoro makĩaga gũtoonya bũrũri ũrĩa Jehova amaheete.
10 Ìbínú Olúwa sì dìde sí wọn ní ọjọ́ náà, ó sì búra, wí pé,
Jehova agĩcinwo nĩ marakara mũthenya ũcio, akĩĩhĩta na mwĩhĩtwa ũyũ:
11 ‘Nítorí wọn kò tẹ̀lé mi tọkàntọkàn, kì í ṣe ọ̀kan nínú àwọn ọkùnrin náà tí ó jẹ́ ogún ọdún tàbí jù bẹ́ẹ̀ lọ tí ó gòkè láti Ejibiti ni yóò rí ilẹ̀ tí mo pinnu gẹ́gẹ́ bí ìbúra fún Abrahamu, fún Isaaki àti fún Jakọbu:
‘Nĩ ũndũ nĩmagĩte kũnũmĩrĩra na ngoro ciao kũna, hatirĩ mũndũ o na ũmwe wa ũkũrũ wa mĩaka mĩrongo ĩĩrĩ na makĩria wa arĩa moimire bũrũri wa Misiri ũkoona bũrũri ũrĩa nderĩire Iburahĩmu na Isaaka, o na Jakubu na mwĩhĩtwa,
12 kò sí ẹnìkankan àyàfi Kalebu ọmọ Jefunne ti Kenissiti àti Joṣua ọmọ Nuni, nítorí wọ́n tẹ̀lé Olúwa tọkàntọkàn.’
gũtirĩ o na ũmwe tiga Kalebu mũrũ wa Jefune, ũrĩa Mũkenizi, na Joshua mũrũ wa Nuni, nĩ ũndũ nĩmarũmĩrĩire Jehova na ngoro ciao kũna.’
13 Ìbínú Olúwa ru sí àwọn ọmọ Israẹli ó sì mú wọn rìn ní aginjù fún ogójì ọdún, títí tí àwọn ìran tí wọ́n ṣe búburú ní ojú rẹ̀ fi lọ.
Jehova agĩcinwo nĩ marakara nĩ ũndũ wa Isiraeli, nake agĩtũma morũũre werũ-inĩ mĩaka mĩrongo ĩna, o nginya rĩrĩa rũciaro rũu ruothe rwehĩtie maitho-inĩ make rwathirire.
14 “Níbí ni ẹ̀yin wà, ẹ̀yin ẹlẹ́ṣẹ̀, ẹ̀yin dìde ní ipò baba yín, ẹ sì jẹ́ kí ìbínú gbígbóná Olúwa ru sí Israẹli.
“Na rĩrĩ, mũrĩ haha inyuĩ, inyuĩ rũciaro rũrũ rwa ehia, mũcookete ithenya rĩa maithe manyu nĩguo mũtũme Jehova akĩrĩrĩrie kũrakarĩra Isiraeli.
15 Tí ẹ̀yin bá yípadà ní ẹ̀yìn rẹ̀ yóò sì fi àwọn ènìyàn wọ̀nyí sílẹ̀ ní aginjù, ìwọ yóò sì mú un ṣe ìparun.”
Mũngĩgarũrũka mũtige kũmũrũmĩrĩra-rĩ, nake Jehova nĩegũtiganĩria andũ aya othe gũkũ werũ-inĩ rĩngĩ, na inyuĩ mũtuĩke gĩtũmi gĩa kũmaniinithia.”
16 Nígbà náà wọ́n wá sí òkè ní ọ̀dọ̀ rẹ̀, “Àwa yóò fẹ́ láti kọ́ ilé ẹran níhìn-ín yìí fún ohun ọ̀sìn wa, àti ìlú fún àwọn obìnrin àti ọmọ wẹ́wẹ́ wa.
Nao magĩthiĩ kũrĩ Musa makĩmwĩra atĩrĩ, “Ithuĩ tũkwenda gwakĩra ũhiũ witũ ciugũ gũkũ, na twakĩre andũ-a-nja aitũ na ciana matũũra manene.
17 Ṣùgbọ́n àwa ṣetán láti dira ogun ṣáájú àwọn ọmọ Israẹli títí tí a yóò fi mú wọn dé ọ̀dọ̀ wọn lákokò yìí, àwọn obìnrin àti ọmọ wẹ́wẹ́ wa yóò gbé inú ìlú tí a mọ odi sí fún ìdáàbòbò wọn lọ́wọ́ olùgbé ilẹ̀ náà.
No rĩrĩ, nĩtwĩhaarĩirie kuoya indo ciitũ cia mbaara na tũthiĩ mbere ya andũ a Isiraeli nginya tũmakinyie kwao. Hĩndĩ ĩyo, andũ-a-nja aitũ na ciana maikarage matũũra manene mairigĩre na hinya, nĩgeetha magitĩrwo kuuma kũrĩ atũũri a bũrũri ũyũ.
18 A kì yóò padà sí ilẹ̀ wa láìṣe pé gbogbo àwọn ọmọ Israẹli ti gba ogún wọn.
Tũtigacooka mĩciĩ iitũ o nginya hĩndĩ ĩrĩa Mũisiraeli o wothe akaamũkĩra igai rĩake.
19 A kì yóò gba ogún kankan pẹ̀lú wọn ní òdìkejì Jordani, nítorí ogún ti wa, ti wá sí ọ̀dọ̀ wa ní ìhà ìlà-oòrùn Jordani.”
Ithuĩ tũtikaamũkĩra igai hamwe nao mũrĩmo ũrĩa ũngĩ wa Jorodani, nĩ ũndũ igai riitũ tũrĩ narĩo mwena wa irathĩro wa Rũũĩ rwa Jorodani.”
20 Nígbà náà ni Mose sọ fún wọn pé, “Tí ẹ̀yin yóò bá pa ara yín lára, níwájú Olúwa fún ogún.
Nake Musa akĩmeera atĩrĩ, “Mũngĩĩka ũguo-rĩ, na mwĩohe indo cianyu cia mbaara mbere ya Jehova nĩguo mũkarũe,
21 Bí gbogbo yín yóò bá lọ sí Jordani ní ìhámọ́ra níwájú Olúwa, títí yóò fi lé àwọn ọ̀tá rẹ̀ kúrò níwájú rẹ̀.
na inyuothe mũngĩthiĩ mwĩohete indo cia mbaara, mũringe Rũũĩ rwa Jorodani mũrĩ mbere ya Jehova o nginya rĩrĩa akaingata thũ ciake ciume mbere yake,
22 Tí a ó sì fi ṣe ilẹ̀ náà níwájú Olúwa; ẹ̀yin lè padà tí yóò sì di òmìnira lọ́wọ́ ìdè níwájú Olúwa àti Israẹli. Ilẹ̀ yìí yóò sì jẹ́ tiyín níwájú Olúwa.
hĩndĩ ĩrĩa bũrũri ũcio ũgaakorwo ũtooretio mbere ya Jehova, hĩndĩ ĩyo no mũcooke mĩciĩ yanyu na muohorwo kuuma kĩĩranĩro kĩanyu kũrĩ Jehova o na kũrĩ Isiraeli. Naguo bũrũri ũyũ nĩũgatuĩka wanyu maitho-inĩ ma Jehova.
23 “Ṣùgbọ́n tí ẹ̀yin bá kọ̀ láti ṣe èyí, ẹ̀yin yóò máa dẹ́ṣẹ̀ sí Olúwa; kí ẹ̀yin kí ó sì mọ̀ dájú pé ẹ̀ṣẹ̀ yín yóò fi yín hàn.
“No mũngĩkaaga gwĩka ũguo, nĩmũkehĩria Jehova; na mũmenye na ma atĩ mehia manyu nĩmakamũcookerera.
24 Ẹ kọ́ ilé fún àwọn obìnrin yín àti ọmọ wẹ́wẹ́ yín, àti ilé fún agbo ẹran yín, ṣùgbọ́n kí ẹ̀yin kí ó ṣe ohun tí ẹ ti pinnu.”
Akĩrai andũ-a-nja anyu na ciana matũũra manene na ciugũ cia ndũũru cianyu, no hingiai ũguo mweranĩra.”
25 Àwọn ọmọ Gadi àti ọmọ Reubeni sọ fún Mose pé, “Àwa ìránṣẹ́ rẹ yóò ṣe gẹ́gẹ́ bí olúwa wa ti pàṣẹ.
Andũ a Gadi na a Rubeni makĩĩra Musa atĩrĩ, “Ithuĩ ndungata ciaku nĩtũgwĩka o ta ũguo mwathi witũ aathana.
26 Àwọn ọmọ wa àti ìyàwó wa, àwọn agbo ẹran àti ohun ọ̀sìn wa yóò dúró ní ìlú Gileadi.
Ciana ciitũ na atumia aitũ megũikara gũkũ matũũra-inĩ manene ma Gileadi, ũndũ ũmwe na ndũũru ciitũ cia mbũri na cia ngʼombe.
27 Ṣùgbọ́n àwọn ìránṣẹ́ rẹ, gbogbo ọkùnrin tí ó wọ ìhámọ́ra ogun, yóò rékọjá lọ láti jà níwájú Olúwa; gẹ́gẹ́ bí olúwa wa ti sọ.”
No ithuĩ ndungata ciaku-rĩ, o mũndũ eyohete indo ciake cia mbaara, nĩtũkũringa mũrĩmo ũũrĩa tũkarũe tũrĩ mbere ya Jehova, o ta ũguo mwathi witũ oiga.”
28 Nígbà náà ni Mose pàṣẹ nípa wọn fún Eleasari àlùfáà àti Joṣua ọmọ Nuni àti sí gbogbo olórí ìdílé ẹ̀yà Israẹli.
Nake Musa akĩruta watho nĩ ũndũ wao, akĩarĩria Eleazaru ũrĩa mũthĩnjĩri-Ngai, na Joshua mũrũ wa Nuni, na atongoria a nyũmba cia mĩhĩrĩga ya andũ a Isiraeli,
29 Mose sì wí fún wọn pé, “Tí àwọn ọmọ Gadi àti ọmọ Reubeni, gbogbo ọkùnrin tí ó wọ ìhámọ́ra fún ogun rékọjá odò Jordani pẹ̀lú níwájú Olúwa, nígbà tí ẹ ṣẹ́gun ilẹ̀ náà níwájú yín, fún wọn ní ilẹ̀ Gileadi gẹ́gẹ́ bí ìní wọn.
akĩmeera atĩrĩ, “Angĩkorwo andũ a Gadi na a Rubeni nĩmekũringa Jorodani, o mũndũ wao eyohete indo cia mbaara, marĩ hamwe na inyuĩ marĩ mbere ya Jehova-rĩ, hĩndĩ ĩrĩa bũrũri ũcio ũgatoorio mbere yanyu, nĩmũkamahe bũrũri wa Gileadi ũtuĩke wao.
30 Ṣùgbọ́n tí wọn kò bá fẹ́ bá yín rékọjá pẹ̀lú ìhámọ́ra, wọn gbọdọ̀ gba ìní wọn pẹ̀lú yín ní Kenaani.”
No mangĩaga kũringa hamwe na inyuĩ meeohete indo ciao cia mbaara, no nginya metĩkĩre igai rĩao hamwe na inyuĩ bũrũri wa Kaanani.”
31 Àwọn ọmọ Gadi àti ọmọ Reubeni dáhùn pé, “Ìránṣẹ́ rẹ yóò ṣe ohun tí Olúwa ti sọ.
Andũ a Gadi na a Rubeni makĩmũcookeria atĩrĩ, “Ndungata ciaku nĩ igwĩka o ta ũguo Jehova oigĩte.
32 A máa rékọjá níwájú Olúwa lọ sí Kenaani pẹ̀lú ìhámọ́ra, ṣùgbọ́n ẹrù tí a jogún yóò wà ní ẹ̀bá Jordani.”
Nĩtũkũringa tũrĩ mbere ya Jehova tũtoonye bũrũri wa Kaanani twĩohete indo cia mbaara, no kũndũ kũrĩa ithuĩ tũkaagaya-rĩ, gũgaakorwo kũrĩ mbarĩ ĩno ya Jorodani.”
33 Nígbà náà Mose fún àwọn ọmọ Gadi àti àwọn ọmọ Reubeni àti ààbọ̀ ẹ̀yà Manase ọmọ Josẹfu ní ilẹ̀ ọba Sihoni ọba àwọn ọmọ Amori àti ilẹ̀ ọba Ogu ọba Baṣani ní gbogbo ilẹ̀ náà pẹ̀lú ìlú rẹ̀ àti agbègbè tí ó yí i ka.
Musa akĩhe andũ a Gadi na a Rubeni na nuthu ya mũhĩrĩga wa Manase mũrũ wa Jusufu, bũrũri ũrĩa wothe wathamakagwo nĩ Sihoni mũthamaki wa Aamori, na ũrĩa wothe wathamakagwo nĩ Ogu mũthamaki wa Bashani, akĩmahe bũrũri ũcio wothe, na matũũra manene makuo o na ngʼongo iria ciamarigiicĩirie.
34 Àwọn ará Gadi wọ́n kọ́ Diboni, Atarotu, Aroeri;
Andũ a Gadi nĩmakire Diboni, na Atarothu, na Aroeri,
35 pẹ̀lú Atrotu Ṣofani, Jaseri, àti Jogbeha,
na Atarothu-Shofani, na Jazeri, na Jogibeha,
36 pẹ̀lú Beti-Nimra, àti Beti-Harani ìlú olódi, àti agbo fún àgùntàn.
na Bethi-Nimira, na Bethi-Harani, maarĩ matũũra manene mairigĩre na hinya na magĩakĩra ndũũru ciao cia mbũri ciugũ.
37 Àwọn ọmọ Reubeni sì kọ́ Heṣboni, Eleale, Kiriataimu,
Nao andũ a Rubeni magĩaka Heshiboni, na Eleale, na Kiriathaimu rĩngĩ,
38 pẹ̀lú Nebo pẹ̀lú Baali-Meoni (wọ́n pàrọ̀ orúkọ wọn) àti Sibma. Wọ́n sì sọ ìlú tí wọ́n tún kọ́ ní orúkọ mìíràn.
o ũndũ ũmwe na Nebo na Baali-Meoni (marĩĩtwa macio nĩmagarũrirwo) na Sibima. Nao makĩhe matũũra macio manene maakire marĩĩtwa mangĩ.
39 Àwọn ọmọ Makiri ọmọ Manase lọ sí Gileadi, wọ́n sì lé àwọn ọmọ Amori tí ó wà níbẹ̀.
Nacio njiaro cia Makiru mũrũ wa Manase igĩthiĩ Gileadi, magĩkwĩnyiitĩra na makĩingata Aamori arĩa maarĩ kuo.
40 Mose sì fi àwọn ọmọ Gileadi fún àwọn ọmọ Makiri àwọn ìran Manase, wọ́n sì tẹ̀dó síbẹ̀.
Nĩ ũndũ ũcio Musa akĩheana Gileadi kũrĩ andũ a Makiru, acio njiaro cia Manase, nao magĩtũũra kuo.
41 Jairi, ọmọ Manase gba ibùjókòó wọn, ó sì pè wọ́n ní Haffotu Jairi.
Na rĩrĩ, Jairu wa rũciaro rwa Manase, akĩĩnyiitĩra tũtũũra twa Gileadi na agĩtwĩta Havothu-Jairu.
42 Noba gba Kenati àti àwọn ìtẹ̀dó rẹ̀, ó sì pè é ní Noba lẹ́yìn orúkọ ara rẹ̀.
Nake Noba akĩĩnyiitĩra Kenathu, na tũtũũra tũrĩa twagũthiũrũrũkĩirie agĩtwĩta Noba, o ta ũrĩa we eetagwo.