< Numbers 31 >

1 Olúwa sọ fún Mose pé,
Angraeng mah Mosi khaeah,
2 “Gbẹ̀san lára àwọn Midiani fún àwọn ọmọ Israẹli. Lẹ́yìn ìgbà náà a ó kó ọ jọ pẹ̀lú àwọn ènìyàn rẹ.”
Israel kaminawk nuiah sak ih zaehaih baktih toengah, Midian kaminawk khaeah sah pathok ah; to pacoengah loe nangmah ih kaminawk khaeah la tih boeh, tiah a naa.
3 Mose sì sọ fún àwọn ènìyàn pé, “Ẹ wọ ogun fún àwọn kan nínú yín láti lọ da ojú ìjà kọ àwọn ọmọ Midiani láti gba ẹ̀san Olúwa lára wọn.
To pongah Mosi mah kaminawk khaeah, Midian kaminawk nuiah Angraeng ih lu to lak moe, Midian kaminawk to tuk hanah, nangcae thung ih thoemto kaminawk maiphaw maica hoi amthoep oh.
4 Rán ẹgbẹ̀rún ọmọ-ogun láti ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan ní Israẹli.”
Israel acaeng thung hoi acaeng maeto mah kami sang to misatuk hanah patoeh oh, tiah a naa.
5 Bẹ́ẹ̀ ni wọ́n sì yan nínú àwọn ẹgbẹẹgbẹ̀rún ènìyàn Israẹli, ẹgbẹ̀rún ènìyàn láti inú ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan, ẹgbàá mẹ́fà ènìyàn tí ó wọ ìhámọ́ra ogun.
To pongah Israel acaeng maeto boih thung hoiah patoeh ih kami sang hatlai hnetto loe misatuk hanah angthawk o.
6 Mose rán wọn lọ sí ogun, ẹgbẹ̀rún láti ẹ̀yà kọ̀ọ̀kan pẹ̀lú Finehasi ọmọ Eleasari, ti ó jẹ́ àlùfáà, ti òun ti ohun èlò ibi mímọ́ àti ìpè wọ̀n-ọn-nì ní ọwọ́ rẹ̀.
Mosi mah to kaminawk to misatuk hanah acaeng maeto thung hoiah kami sangto patoeh; nihcae hoi nawnto mongkah ueng Eleazar capa qaima Phinehas to hmuenciim thung ih maiphaw maicanawk hoiah nawnto patoeh.
7 Wọ́n dojú ìjà kọ Midiani gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti pàṣẹ fún Mose, kí wọn sì pa gbogbo wọn.
Angraeng mah Mosi khaeah thuih ih lok baktih toengah, nihcae mah Midian kaminawk to tuk o moe, nongpanawk to hum o boih.
8 Wọ́n sì pa àwọn ọba Midiani pẹ̀lú: àwọn ìyókù tí wọ́n pa lára wọn ni Efi, Rekemu, Suri àti Huri, àti Reba: ọba Midiani márùn-ún, wọ́n sì fi idà pa Balaamu ọmọ Beori.
A hum o ih kaminawk thungah Evi, Rekem, Zur, Hur hoi Reba, Midian siangpahrang pangato athum o; nihcae mah Beor capa Balaam doeh sumsen hoiah hum o.
9 Àwọn ọmọ Israẹli sì mú gbogbo obìnrin Midiani ní ìgbèkùn àti àwọn ọmọ kékeré wọn, wọ́n sì kó gbogbo ohun ọ̀sìn wọn àti gbogbo agbo ẹran wọn àti gbogbo ẹrù wọn.
Israel kaminawk mah Midian nongpatanawk hoi nawktanawk, nihcae ih hmuenmaenawk, maitawnawk hoi tuunawk to lomh pae o boih.
10 Wọ́n finá jó gbogbo ìlú wọn àti ibùdó wọn.
Midian kaminawk ohhaih vangpuinawk to hmai hoiah thlaek pae o boih; a ohhaih kahoih imnawk doeh thlaek pae o boih.
11 Wọ́n sì kó gbogbo ìní wọn, àti ènìyàn àti ẹran.
A naeh o ih kaminawk, a lak o ih hmuennawk hoi pacah ih moinawk doeh lak pae o boih.
12 Wọ́n sì kó gbogbo ohun tí wọ́n bàjẹ́ àti ènìyàn àti ẹran wá sọ́dọ̀ Mose àti Eleasari àlùfáà, àti sọ́dọ̀ ìjọ àwọn ọmọ Israẹli ní ibùdó àgọ́ ní pẹ̀tẹ́lẹ̀ Moabu tí ń bẹ lẹ́gbẹ̀ẹ́ Jordani létí Jeriko.
Misong ah naeh o ih kaminawk hoi a lak pae o ih hmuennawk boih loe, Moab azawn ih Jordan vapui taeng, Jeriko vangpui zaeh ah kaom, Mosi, qaima Eleazar hoi Israel kaminawk khaeah a sinh pae o.
13 Mose, Eleasari àlùfáà àti gbogbo olórí ìgbèríko lọ láti lọ bá wọn ní ìta ibùdó.
Mosi, qaima Eleazar hoi acaeng zaehoikung boih loe, nihcae tongh hanah ataihaih ahmuen tasa bangah caeh o.
14 Inú bí Mose sí àwọn olórí ọmọ-ogun, pẹ̀lú àwọn olórí ẹgbẹẹgbẹ̀rún àti olórí ọ̀rọ̀ọ̀rún tí wọ́n ti ogun dé.
To naah Mosi loe misatukhaih ahmuen hoiah amlaem misatuh angraengnawk, kami sangto ukkungnawk hoi kami cumvaito ukkungnawk nuiah palungphui.
15 Mose sì béèrè wí pé, “Ẹ̀yin ha dá gbogbo àwọn obìnrin sí bí?
Mosi mah nihcae khaeah, Nongpatanawk na pathlungh o boih maw? tiah a dueng.
16 Àwọn ni wọ́n tẹ̀lé ìmọ̀ràn Balaamu, àwọn ní ó ṣe okùnfà yíyí àwọn ọ̀mọ̀ Israẹli padà kúrò ní ọ̀dọ̀ Olúwa nínú èyí tí ó ṣẹlẹ̀ ní Peori, níbi tí àjàkálẹ̀-ààrùn ti kọlu ìjọ Olúwa.
Khenah, hae nongpatanawk loe Balaam ih lok to tahngaih o moe, Peor kawng pongah Israel kaminawk to Angraeng khae hoi loklam amkhraengs o sak boeh; to pongah Angraeng ih kaminawk salakah kasae nathaih to oh.
17 Nísinsin yìí, pa gbogbo ọ̀dọ́mọkùnrin àti àwọn obìnrin tí ó ti súnmọ́ ọkùnrin,
Vaihi nawktanawk salak ih nongpa to hum o boih ah; nongpa hoi nawnto iip nongpatanawk doeh hum o boih ah.
18 ṣùgbọ́n kí o dá obìnrin tí kò bá tí ì súnmọ́ ọkùnrin sí fún ara yín.
Toe nongpa panoek vai ai tanglanawk loe nangmacae han suem oh.
19 “Ẹnikẹ́ni tí ó bá ti pa ènìyàn tàbí fọwọ́ kan ẹni tí a pa gbọdọ̀ dúró ní ìta ibùdó àgọ́ fún ọjọ́ méje. Ní ọjọ́ kẹta àti ọjọ́ keje ẹ gbọdọ̀ ya ara yín àti ẹni tí ẹ kó lẹ́rú sí mímọ́.
Nangcae thungah mi kawbaktih doeh kami hum kami, to tih ai boeh loe hum ih kami qok sui kami to ataihaih im tasa bangah ni sarihto thung suem oh; ni thumto hoi ni sarihto naah nangmacae hoi na naeh o ih kaminawk boih ciimcaihaih to sah oh.
20 Kí ẹ̀yin kí ó ya aṣọ yín sí mímọ́ àti gbogbo ohun tí a fi awọ ṣe àti gbogbo iṣẹ́ irun ewúrẹ́ àti ohun tí a fi igi ṣe.”
Nangmacae ih khukbuen, moihin hoi sak ih hmuennawk, maeh mui, thing hoi sak ih hmuennawk to ciimcai o sak ah, tiah a naa.
21 Eleasari àlùfáà sì wí fún àwọn olórí ogun náà pé, “Èyí ní ìlànà òfin tí Olúwa fi lélẹ̀ ní àṣẹ fún Mose.
To pacoengah qaima Eleazar mah misatuk han kacaeh misatuh kaminawk khaeah, Angraeng mah Mosi khaeah paek ih atawk loe hae tiah oh;
22 Kìkì i wúrà, fàdákà, idẹ, irin, idẹ àti òjé.
sui, sum kanglung, sum kamling, sum, camphaeh ngan hoiah kimah,
23 Ohunkóhun tí ó lè la iná ni kí ẹ̀yin ó mú la iná, nígbà náà ni yóò jẹ́ mímọ́. Ṣùgbọ́n ẹ yóò fi omi ìyàsímímọ́ sọ ọ́ di mímọ́. Àti gbogbo ohun tí kò lè la iná kọjá ni kí a mú la inú omi.
hmai kakaang thaih hmuennawk boih loe hmai hoiah qoeng ah, to tiah nahaeloe ciim tih; ciimsakhaih tui hoiah doeh pasae oh; hmai khaan thai ai hmuennawk loe tui hoiah pasae oh.
24 Ní ọjọ́ keje, ẹ fọ aṣọ yín, ẹ̀yin yóò sì mọ́, nígbà náà ní ẹ̀yin yóò lè wọ inú ibùdó àjọ.”
Ni sarihto naah khukbuennawk to pasuk oh, to tiah nahaeloe na ciim o tih; to pacoengah loe ataihaih imthung ah nang zo o thai tih boeh, tiah a naa.
25 Olúwa sọ fún Mose pé,
Angraeng mah Mosi khaeah,
26 “Ìwọ àti Eleasari àlùfáà àti àwọn olórí ilé baba ìjọ ni kí o ka iye àwọn ènìyàn àti ẹranko tí a kó ní ìgbèkùn.
kaminawk mah lak o ih hmuenmaenawk to nangmah hoi qaima Eleazar hoi acaeng zaehoikung mah la oh loe,
27 Pín ohun ìní àti ìkógun náà láàrín àwọn ọmọ-ogun náà tí ó kópa nínú ogun náà àti láàrín gbogbo ìjọ.
to hmuennawk to ahmuen hnetto ah tapraek ah; misatuk han caeh misatuh kaminawk hoi amkhueng kaminawk han tapraek paeh.
28 Kí o sì gba ìdá ti Olúwa lọ́wọ́ àwọn ológun tí wọn jáde lọ sí ogun náà, ọ̀kan nínú ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta nínú àwọn ènìyàn àti nínú màlúù àti nínú kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, àti nínú agbo ẹran.
Misatuk han kacaeh misatuh kaminawk loe kami doeh, maitaw doeh, laa hrang doeh, tuu doeh, cumvai pangato thungah maeto, Angraeng khaeah paek han oh;
29 Gba ìdá yìí lára ààbọ̀ ìpín tiwọn, kí o sì fún Eleasari àlùfáà, fún ẹbọ ìgbésókè Olúwa.
nihcae mah hak ih tamut ahap to la ah loe, Angraeng taham to qaima Eleazar khaeah paek ah.
30 Lára ààbọ̀ ti Israẹli, yan ọ̀kan kúrò nínú àádọ́ta, yálà ènìyàn, ẹran ọ̀sìn, kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, àgùntàn, ewúrẹ́ tàbí ẹ̀yà ẹranko mìíràn. Kó wọn fún àwọn Lefi, tí ó dúró fún olùtọ́jú àgọ́ Olúwa.”
Israel acaeng ahap khae hoiah, kami doeh, maitaw doeh, laa hrang doeh, tuu doeh, maeh doeh, kalah moinawk doeh, qui pangato thungah maeto la ah loe, to hmuennawk to Angraeng ih kahni im khenzawnkung Levinawk khaeah paek ah, tiah a naa.
31 Nígbà náà Mose àti Eleasari àlùfáà ṣe gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.
To pongah Angraeng mah Mosi khaeah thuih ih lok baktih toengah, Mosi hoi qaima Eleazar mah sak hoi.
32 Èrè tí ó kù lára ìkógun tí àwọn ọmọ-ogun kó jẹ́, ọ̀kẹ́ mẹ́rìnlélọ́gbọ̀n ó dín ẹgbẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n àgùntàn.
Misatuh kaminawk mah lak o ih kanghmat tuunawk loe sang cumvai taruk, sang qui sarih, sang pangato oh.
33 Ẹgbàá méjìléláàádọ́rin màlúù
Maitaw sing sarih, sang hnetto,
34 ọ̀kẹ́ mẹ́ta ó lé ẹgbẹ̀rin kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́,
laa hrang sing taruk, sangto,
35 pẹ̀lú obìnrin ẹgbàá mẹ́rìndínlógún, ni kò ní ìbálòpọ̀ pẹ̀lú ọkùnrin rí.
nongpa hoi iip vai ai nongpata sing thum, sang hnetto oh o.
36 Ìpín ààbọ̀ àwọn tí ó jáde lọ sí ogun sì jẹ́: ẹgbàá méjìdínláàádọ́sàn-án ó lé lẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀jọ àgùntàn.
Misatuk naah kacaeh kaminawk ih taham ahap loe, tuu sing qui thum, sing thum, sang sarih, cumvai pangato,
37 Tí ìdá ti Olúwa sì jẹ́ ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀rin ó dín mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n àgùntàn;
Angraeng khaeah tathlang han ih hmuen loe cumvai taruk, qui sarih, pangato oh.
38 ẹgbọrọ màlúù jẹ́ ẹgbàá méjìdínlógún, tí ìdá Olúwa sì jẹ́ méjìléláàádọ́rin;
Maitaw sing thum, sang tarukto oh; to thung hoiah qui sarih, hnetto loe Angraeng khaeah paek han ih taham ah oh.
39 kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ sì jẹ́ ẹgbàá mẹ́ẹ̀ẹ́dógún ó lé lẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta, tí ìdá ti Olúwa sì jẹ́ mọ́kànlélọ́gọ́ta.
Laa hrang sing thum, cumvai pangato oh; to thung hoiah Angraeng ih taham loe qui taruk, maeto;
40 Àwọn ènìyàn sì jẹ́ ẹgbàá mẹ́jọ ìdá ti Olúwa sì jẹ́ méjìlélọ́gbọ̀n.
kami loe singto pacoeng, sang tarukto oh; to thung hoiah Angraeng ih taham loe qui thum, hnetto.
41 Mose fi ìdá náà fún Eleasari, àlùfáà gẹ́gẹ́ bí ìdá ti Olúwa, gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti pa á láṣẹ fún Mose.
Angraeng mah Mosi khaeah thuih ih lok baktih toengah, Mosi mah Angraeng ih taham to qaima Eleazar khaeah paek.
42 Ààbọ̀ tí ó jẹ́ ti àwọn ọmọ Israẹli, tí Mose yà sọ́tọ̀ kúrò lára àwọn ọkùnrin tí ó ja ogun.
Mosi mah misatuh kaminawk khae hoiah lak moe, Israel kaminawk mah hak han koi ahap,
43 Ààbọ̀ tí ìjọ jẹ́ ẹgbàá méjìdínláàádọ́sàn-án ó lé lẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀jọ àgùntàn,
rangpuinawk mah hak han koi ahap loe, tuu sang cumvai thum, sing thum, sang sarih, cumvai pangato;
44 pẹ̀lú ẹgbàá méjìdínlógún màlúù
maitaw sing thum, sang tarukto,
45 tí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ sì jẹ́ ẹgbàá mẹ́ẹ̀ẹ́dógún ó lé lẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀ta.
laa hrang sing thum, cumvai pangato hoi,
46 Àwọn ènìyàn sì jẹ́ ẹgbàá mẹ́jọ.
kami singto pacoeng, sang tarukto oh.
47 Lára ààbọ̀ ti àwọn ọmọ Israẹli, Mose yan ọ̀kan lára àádọ́ta ènìyàn àti ẹranko gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti pa á láṣẹ fún un. Ó sì fi wọ́n fún àwọn ọmọ Lefi, tí ń ṣe olùtọ́jú àgọ́ Olúwa.
Angraeng mah thuih ih lok baktih toengah, Israel rangpui mah hak han koi taham ahap thung hoiah, Mosi mah kami maw, moi maw qui pangato thungah maeto lak moe, Angraeng ih kahni im khenzawnkung Levi kaminawk khaeah paek.
48 Pẹ̀lú àwọn olórí tí ó wà lórí ẹgbẹẹgbẹ̀rin ogun náà, àti àwọn balógun ọ̀rọ̀ọ̀rún wá sọ́dọ̀ Mose.
To pacoengah misatuh sangto ukkungnawk hoi misatuh cumvaito ukkungnawk Mosi khaeah caeh o moe,
49 Wọ́n sì sọ fún un pé, “Ìránṣẹ́ rẹ ti ka àwọn ọmọ-ogun náà tí ó wà lábẹ́ ìtọ́jú wa, kò sì sí ọ̀kọ̀ọ̀kan tó dín.
anih khaeah, Na tammanawk mah misatuh kaminawk thung ih kami ka kroek o naah, maeto doeh anghmaa ai.
50 Nítorí náà làwa ṣe mú ọrẹ ẹbọ wá fún Olúwa, gbogbo ọrẹ wíwà tí a ní, wúrà, ẹ̀wọ̀n, àti júfù, àti òrùka-àmi, àti òrùka etí, àti ìlẹ̀kẹ̀ láti fi ṣe ètùtù fún ọkàn an wa níwájú Olúwa.”
To pongah Angraeng khaeah paek hanah sui hoiah sak ih hmuennawk, bungmunawk, ban lakoknawk, bantuetnawk, naa tangkraengnawk, hnah ah bangh koi hmuennawk to Angraeng hmaa ah angbawnhaih ah sak han ih kang sin o, tiah a naa o.
51 Mose àti Eleasari àlùfáà, gba wúrà náà lọ́wọ́ wọn pẹ̀lú gbogbo ohun iṣẹ́ ọ̀ṣọ́.
Mosi hoi qaima Eleazar mah nihcae ih suinawk to talawk pae hoi; ban tok sah kop kaminawk mah sak ih suinawk to talawk pae hoi.
52 Gbogbo wúrà tí àwọn balógun ẹgbẹẹgbẹ̀rún àti àwọn balógun ọ̀rọ̀ọ̀rún mú wá fún Mose àti Eleasari, èyí tí ó jẹ́ ẹbọ ìgbésókè fún Olúwa jẹ́ ẹgbàá mẹ́jọ ó lé lẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀rin ó lé àádọ́ta ṣékélì.
Mosi hoi qaima Eleazar mah misatuh kami sangto ukkungnawk hoi misatuh kami cumvaito ukkungnawk khae hoiah talawk ih Angraeng ih taham suinawk loe sangqum ah shekel sang hatlai taruk, cumvai sarih, qui pangato oh.
53 Nítorí ológun kọ̀ọ̀kan ti kó ẹrù fún ara rẹ̀.
Misatuh kami maeto mah angmah hanah hmuen maeto lak o boih.
54 Mose àti Eleasari àlùfáà gba wúrà náà lọ́wọ́ àwọn balógun ẹgbẹẹgbẹ̀rún àti lọ́wọ́ balógun ọ̀rọ̀ọ̀rún wọ́n sì ko wá sínú àgọ́ ìpàdé fún ìrántí àwọn Israẹli níwájú Olúwa.
Mosi hoi qaima Eleazar mah misatuh kami sangto hoi misatuh kami cumvaito ukkungnawk khae hoiah talawk hoi ih suinawk to Israel kaminawk mah panoek poe hanah amkhuenghaih kahni im ah Angraeng hmaa ah a sin hoi.

< Numbers 31 >