< Numbers 30 >
1 Mose sì sọ fún olórí àwọn ẹ̀yà ọmọ Israẹli pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa pàṣẹ,
Mojzes je spregovoril poglavarjem rodov glede Izraelovih otrok, rekoč: »To je stvar, ki jo je Gospod zapovedal.
2 nígbà tí ọkùnrin kan bá jẹ́ ẹ̀jẹ́ sí Olúwa tàbí búra láti fi de ara rẹ̀ ní ìdè kí òun má bà ba ọ̀rọ̀ rẹ̀ jẹ́ kí ó ṣe gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣe sọ.
Če se mož zaobljubi Gospodu zaobljubo ali priseže prisego, da svojo dušo zaveže z vezjo, ne bo prelomil svoje besede; storil bo glede na vse, kar je izšlo iz njegovih ust.
3 “Nígbà tí ọmọbìnrin kan bá sì wà ní ilé baba rẹ̀ tó bá jẹ́ ẹ̀jẹ́ fún Olúwa tàbí búra láti fi de ara rẹ̀
Če se tudi ženska zaobljubi Gospodu zaobljubo in se zaveže z vezjo, ko je v hiši svojega očeta, v svoji mladosti,
4 tí baba rẹ̀ bá sì gbọ́ ẹ̀jẹ́ rẹ̀ tàbí ìdè rẹ̀ tí kò sì sọ nǹkan kan sí i, kí gbogbo ẹ̀jẹ́ rẹ̀ kí ó dúró àti gbogbo ìdè tí ó fi de ara rẹ̀ yóò sì dúró.
in njen oče sliši njeno zaobljubo in njeno vez, s katero je zavezala svojo dušo in bo njen oče ob njej ohranil svoj mir, potem bodo vse njene zaobljube veljale in vsaka vez, s katero je zavezala svojo dušo, bo veljala.
5 Ṣùgbọ́n tí baba rẹ̀ bá kọ̀ fun un ní ọjọ́ tí ó gbọ́, kò sí ọ̀kan nínú ẹ̀jẹ́ rẹ̀ tàbí nínú ìdè tí ó fi de ara rẹ̀ tí yóò dúró; Olúwa yóò sì tú u sílẹ̀ nítorí baba rẹ̀ kọ̀ fún un.
Toda če ji njen oče brani na dan, ko to sliši niti ena izmed njenih zaobljub ali izmed njenih vezi, s katerimi je zvezala svojo dušo, ne bo veljala in Gospod ji bo oprostil, ker ji je njen oče branil.
6 “Tí ó bá sì ní ọkọ lẹ́yìn ìgbà tí ó jẹ́ ẹ̀jẹ́ tàbí lẹ́yìn ìgbà tí ó sọ ọ̀rọ̀ kan láti ẹnu rẹ̀ jáde nínú èyí tí ó fi de ara rẹ̀ ní ìdè,
Če pa je sploh imela soproga, ko se je zaobljubila ali izustila iz svojih ustnic, s čimer je zavezala svojo dušo
7 tí ọkọ rẹ̀ sì gbọ́ nípa èyí ṣùgbọ́n tí kò sọ nǹkan kan, nígbà náà ni ẹ̀jẹ́ tàbí ìdè tí ó fi de ara rẹ̀ tó dúró.
in je njen soprog to slišal in je ob njej ohranil svoj mir na dan, ko je to slišal, potem bodo njene zaobljube veljale in njene vezi, s katerimi je zavezala svojo dušo, bodo veljale.
8 Ṣùgbọ́n tí ọkọ rẹ̀ bá kọ̀ nígbà tí ó gbọ́, ǹjẹ́ òun yóò mú ẹ̀jẹ́ rẹ̀ tí ó jẹ́ àti ohun tí ó ti ti ẹnu rẹ̀ jáde, èyí tí ó fi de ara rẹ̀ dasán, Olúwa yóò sì dáríjì í.
Toda če ji njen soprog brani na dan, ko to sliši, potem bo naredil njeno zaobljubo, s katero se je zaobljubila in to, ki jo je izrekla s svojimi ustnicami, s katero je zavezala svojo dušo, brez učinka in Gospod ji bo oprostil.
9 “Ṣùgbọ́n ẹ̀jẹ́ kí ẹ̀jẹ́ tàbí ìdè kí ìdè tí opó tàbí obìnrin tí a kọ̀sílẹ̀ bá ṣe yóò wà lórí rẹ̀.
Toda vsaka zaobljuba vdove in tiste, ki je ločena, s katero so zavezale svoje duše, bo veljala zoper njo.
10 “Bí obìnrin tí ó ń gbé pẹ̀lú ọkọ rẹ̀ bá jẹ́ ẹ̀jẹ́ tàbí de ara rẹ̀ ní ìdè lábẹ́ ìbúra,
Če se je zaobljubila v hiši svojega soproga ali je svojo dušo zavezala z vezjo prisege
11 tí ọkọ rẹ̀ bá sì gbọ́, ṣùgbọ́n tí kò sọ̀rọ̀, tí kò sì kọ̀, nígbà náà ni ẹ̀jẹ́ rẹ̀ yóò dúró.
in je njen soprog to slišal in ob njej ohranil svoj mir in ji ni branil, potem bodo vse njene zaobljube veljale in vsaka vez, s katero je zavezala svojo dušo, bo veljala.
12 Ṣùgbọ́n tí ọkọ rẹ̀ bá sọ wọ́n dasán, nígbà tí ó gbọ́, nígbà náà kò sí ẹ̀jẹ́ tàbí ìdè tí ó ti ẹnu rẹ̀ jáde tí yóò dúró, ọkọ rẹ̀ ti sọ wọ́n dasán, Olúwa yóò tú u sílẹ̀.
Toda če jih je njen soprog popolnoma izničil na dan, ko jih je slišal, potem karkoli je izšlo iz njenih ustnic glede njenih zaobljub ali glede vezi njene duše, ne bo veljalo. Njen soprog jih je izničil in Gospod ji bo oprostil.
13 Ọkọ rẹ̀ lè ṣe ìwádìí tàbí sọ ọ́ dasán ẹ̀jẹ́ tàbí ìbúra ìdè tí ó ti ṣe láti fi de ara rẹ̀.
Vsako zaobljubo in vsako prisego, ki zadeva dušo, lahko njen soprog uveljavi ali izniči.
14 Ṣùgbọ́n tí ọkọ rẹ̀ kò bá sọ nǹkan kan sí í nípa rẹ̀ ní ọjọ́ dé ọjọ́, nígbà náà ni ó ṣe ìwádìí nípa ẹ̀jẹ́ àti ìbúra ìdè tí ó dè é. Kí ọkùnrin náà ṣe ìwádìí lórí rẹ̀ láìsọ nípa rẹ̀ si nígbà tí ó gbọ́ nípa rẹ̀.
Toda če iz dneva v dan njen soprog ob njej povsem ohrani svoj mir, potem je vzpostavil vse njene zaobljube ali vse njene vezi, ki so na njej. Potrjuje jih, ker je ohranil svoj mir ob njej na dan, ko jih je slišal.
15 Bí ó ti wù kí ó rí, bí ọkùnrin náà bá sọ ọ́ dasán, ní àkókò kan lẹ́yìn tí ó ti gbọ́ wọn, nígbà náà ó jẹ̀bi ọ̀rọ̀ náà.”
Toda če jih bo na katerikoli način izničil, potem ko jih je slišal, potem bo nosil njeno krivičnost.«
16 Èyí ni ìlànà tí Olúwa fún Mose nípa ìbátan láàrín ọkùnrin àti obìnrin àti láàrín baba àti ọ̀dọ́mọbìnrin rẹ̀ tí ó sì ń gbé ní ilé rẹ̀.
To so zakoni, ki jih je Gospod zapovedal Mojzesu, med moškim in njegovo ženo, med očetom in njegovo hčerjo, ki je še v svoji mladosti, v hiši svojega očeta.