< Numbers 30 >

1 Mose sì sọ fún olórí àwọn ẹ̀yà ọmọ Israẹli pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa pàṣẹ,
и глагола Моисей князем племен сынов Израилевых, глаголя: сие слово, еже повеле Господь.
2 nígbà tí ọkùnrin kan bá jẹ́ ẹ̀jẹ́ sí Olúwa tàbí búra láti fi de ara rẹ̀ ní ìdè kí òun má bà ba ọ̀rọ̀ rẹ̀ jẹ́ kí ó ṣe gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣe sọ.
Человек человек, иже аще обещает обет Господу, или закленется клятвою, или определит пределом о души своей, не осквернавит словесе своего: вся, елика изыдут из уст его, да сотворит.
3 “Nígbà tí ọmọbìnrin kan bá sì wà ní ilé baba rẹ̀ tó bá jẹ́ ẹ̀jẹ́ fún Olúwa tàbí búra láti fi de ara rẹ̀
Аще же обещает жена обет Господу, или определит определение в дому отца своего в юности своей,
4 tí baba rẹ̀ bá sì gbọ́ ẹ̀jẹ́ rẹ̀ tàbí ìdè rẹ̀ tí kò sì sọ nǹkan kan sí i, kí gbogbo ẹ̀jẹ́ rẹ̀ kí ó dúró àti gbogbo ìdè tí ó fi de ara rẹ̀ yóò sì dúró.
и услышит отец ея обеты ея и определения ея, яже определи на душу свою, и премолчит отец ея, и да состоятся вся обеты ея, и вся определения, яже определи на душу свою, да пребудут ей.
5 Ṣùgbọ́n tí baba rẹ̀ bá kọ̀ fun un ní ọjọ́ tí ó gbọ́, kò sí ọ̀kan nínú ẹ̀jẹ́ rẹ̀ tàbí nínú ìdè tí ó fi de ara rẹ̀ tí yóò dúró; Olúwa yóò sì tú u sílẹ̀ nítorí baba rẹ̀ kọ̀ fún un.
Аще же возбранением возбранит отец ея, в оньже день услышит вся обеты ея и определения, яже определи на душу свою, не состоятся: и Господь очистит ю, яко возбрани отец ея.
6 “Tí ó bá sì ní ọkọ lẹ́yìn ìgbà tí ó jẹ́ ẹ̀jẹ́ tàbí lẹ́yìn ìgbà tí ó sọ ọ̀rọ̀ kan láti ẹnu rẹ̀ jáde nínú èyí tí ó fi de ara rẹ̀ ní ìdè,
Аще же посягла за мужа, и обеты ея на ней, по определении уст ея, елика определи на душу свою,
7 tí ọkọ rẹ̀ sì gbọ́ nípa èyí ṣùgbọ́n tí kò sọ nǹkan kan, nígbà náà ni ẹ̀jẹ́ tàbí ìdè tí ó fi de ara rẹ̀ tó dúró.
и услышит муж ея, и премолчит ей, в оньже день услышит, и тако состоятся вся обеты ея, и определения ея, яже определи на душу свою, да состоятся.
8 Ṣùgbọ́n tí ọkọ rẹ̀ bá kọ̀ nígbà tí ó gbọ́, ǹjẹ́ òun yóò mú ẹ̀jẹ́ rẹ̀ tí ó jẹ́ àti ohun tí ó ti ti ẹnu rẹ̀ jáde, èyí tí ó fi de ara rẹ̀ dasán, Olúwa yóò sì dáríjì í.
Аще же возбранением возбранит муж ея, в оньже день услышит вся обеты ея и определения ея, яже определи на душу свою, да не пребудут, яко муж возбрани ей: и Господь очистит ю.
9 “Ṣùgbọ́n ẹ̀jẹ́ kí ẹ̀jẹ́ tàbí ìdè kí ìdè tí opó tàbí obìnrin tí a kọ̀sílẹ̀ bá ṣe yóò wà lórí rẹ̀.
И обет вдовицы и пущеницы, елика аще обещают на душу свою, да пребудут им.
10 “Bí obìnrin tí ó ń gbé pẹ̀lú ọkọ rẹ̀ bá jẹ́ ẹ̀jẹ́ tàbí de ara rẹ̀ ní ìdè lábẹ́ ìbúra,
Аще же в дому мужа ея обет ея или определение, еже на душу ея с клятвою,
11 tí ọkọ rẹ̀ bá sì gbọ́, ṣùgbọ́n tí kò sọ̀rọ̀, tí kò sì kọ̀, nígbà náà ni ẹ̀jẹ́ rẹ̀ yóò dúró.
и услышит муж ея, и премолчит ей, и не возбранит ей, и состоятся вся обеты ея, и вся определения ея, яже определи на душу свою да состоятся на ню.
12 Ṣùgbọ́n tí ọkọ rẹ̀ bá sọ wọ́n dasán, nígbà tí ó gbọ́, nígbà náà kò sí ẹ̀jẹ́ tàbí ìdè tí ó ti ẹnu rẹ̀ jáde tí yóò dúró, ọkọ rẹ̀ ti sọ wọ́n dasán, Olúwa yóò tú u sílẹ̀.
Аще же отлучая отлучит муж ея, в оньже день услышит, вся елика изыдоша из уст ея по обетом ея и по определением ея яже на душу ея, не пребудут ей: муж бо ея отлучил есть, и Господь очистит ю.
13 Ọkọ rẹ̀ lè ṣe ìwádìí tàbí sọ ọ́ dasán ẹ̀jẹ́ tàbí ìbúra ìdè tí ó ti ṣe láti fi de ara rẹ̀.
Всяк обет и всяка клятва соуза во еже озлобити душу, муж ея поставит ей, и муж ея отимет.
14 Ṣùgbọ́n tí ọkọ rẹ̀ kò bá sọ nǹkan kan sí í nípa rẹ̀ ní ọjọ́ dé ọjọ́, nígbà náà ni ó ṣe ìwádìí nípa ẹ̀jẹ́ àti ìbúra ìdè tí ó dè é. Kí ọkùnrin náà ṣe ìwádìí lórí rẹ̀ láìsọ nípa rẹ̀ si nígbà tí ó gbọ́ nípa rẹ̀.
Аще же молча премолчит ей день от дне, и поставит ей вся обеты ея, и определения яже на ней, поставит ей, яко умолча ей в день, в оньже услыша.
15 Bí ó ti wù kí ó rí, bí ọkùnrin náà bá sọ ọ́ dasán, ní àkókò kan lẹ́yìn tí ó ti gbọ́ wọn, nígbà náà ó jẹ̀bi ọ̀rọ̀ náà.”
Аще же отлучая отлучит муж ея по дни, в оньже услыша, и приимет грех свой.
16 Èyí ni ìlànà tí Olúwa fún Mose nípa ìbátan láàrín ọkùnrin àti obìnrin àti láàrín baba àti ọ̀dọ́mọbìnrin rẹ̀ tí ó sì ń gbé ní ilé rẹ̀.
Сия оправдания, елика заповеда Господь Моисею, между мужем и между женою его, и между отцем и дщерию в юности ея, в дому отчи.

< Numbers 30 >