< Numbers 30 >

1 Mose sì sọ fún olórí àwọn ẹ̀yà ọmọ Israẹli pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa pàṣẹ,
Moses loh Israel ca rhoek koca kah boeilu rhoek te a voek tih BOEIPA loh a uen bangla ol he a thui pah.
2 nígbà tí ọkùnrin kan bá jẹ́ ẹ̀jẹ́ sí Olúwa tàbí búra láti fi de ara rẹ̀ ní ìdè kí òun má bà ba ọ̀rọ̀ rẹ̀ jẹ́ kí ó ṣe gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣe sọ.
Tongpa he BOEIPA taengah olcaeng a caeng vaengah khaw, a hinglu dongah rhuikhih te khih ham olhlo a toemngam vaengah khaw a ol te poeih boel saeh. A ka lamloh a thoeng bangla boeih saii saeh.
3 “Nígbà tí ọmọbìnrin kan bá sì wà ní ilé baba rẹ̀ tó bá jẹ́ ẹ̀jẹ́ fún Olúwa tàbí búra láti fi de ara rẹ̀
Huta he BOEIPA taengah olcaeng a caeng tih a camoe ah a napa im kah rhuikhih loh a khih mai ni.
4 tí baba rẹ̀ bá sì gbọ́ ẹ̀jẹ́ rẹ̀ tàbí ìdè rẹ̀ tí kò sì sọ nǹkan kan sí i, kí gbogbo ẹ̀jẹ́ rẹ̀ kí ó dúró àti gbogbo ìdè tí ó fi de ara rẹ̀ yóò sì dúró.
A hinglu dongah a khih a olcaeng neh a rhuikhih te a napa loh a yaak dae a napa loh anih te a ngam tak. Te vaengah a olcaeng boeih te cak vetih a hinglu dongah a khih rhuikhih boeih te khaw cak ni.
5 Ṣùgbọ́n tí baba rẹ̀ bá kọ̀ fun un ní ọjọ́ tí ó gbọ́, kò sí ọ̀kan nínú ẹ̀jẹ́ rẹ̀ tàbí nínú ìdè tí ó fi de ara rẹ̀ tí yóò dúró; Olúwa yóò sì tú u sílẹ̀ nítorí baba rẹ̀ kọ̀ fún un.
A napa loh a yaak hnin ah anih te khaban koinih a olcaeng boeih neh a hinglu dongkah a khih a rhuikhih te cak mahpawh. Te vaeng daengah napa loh anih te a khaban dae BOEIPA loh anih te khodawk a ngai ni.
6 “Tí ó bá sì ní ọkọ lẹ́yìn ìgbà tí ó jẹ́ ẹ̀jẹ́ tàbí lẹ́yìn ìgbà tí ó sọ ọ̀rọ̀ kan láti ẹnu rẹ̀ jáde nínú èyí tí ó fi de ara rẹ̀ ní ìdè,
A va taengah om khaw om mai tih amah sokah a olcaeng neh a hmuilai kah olhlo te a hinglu dongah a khih khaming.
7 tí ọkọ rẹ̀ sì gbọ́ nípa èyí ṣùgbọ́n tí kò sọ nǹkan kan, nígbà náà ni ẹ̀jẹ́ tàbí ìdè tí ó fi de ara rẹ̀ tó dúró.
Te vaengah a va loh a yaak tih a yaak hnin ah pataeng anih te hil a phah tak atah a olcaeng te cak vetih a hinglu dongah a khih a rhuikhih te cak ni.
8 Ṣùgbọ́n tí ọkọ rẹ̀ bá kọ̀ nígbà tí ó gbọ́, ǹjẹ́ òun yóò mú ẹ̀jẹ́ rẹ̀ tí ó jẹ́ àti ohun tí ó ti ti ẹnu rẹ̀ jáde, èyí tí ó fi de ara rẹ̀ dasán, Olúwa yóò sì dáríjì í.
Tedae a va loh a yaak hnin ah anih te a khaban khaming. Te vaengah amah sokah a olcaeng neh a hinglu dongah a khih a hmuilai kah olhlo khaw a phae coeng dongah BOEIPA loh anih te khodawk a ngai ni.
9 “Ṣùgbọ́n ẹ̀jẹ́ kí ẹ̀jẹ́ tàbí ìdè kí ìdè tí opó tàbí obìnrin tí a kọ̀sílẹ̀ bá ṣe yóò wà lórí rẹ̀.
Nuhmai olcaeng neh vama kah a hinglu dongah a khih boeih boeih tah amah soah pai ni.
10 “Bí obìnrin tí ó ń gbé pẹ̀lú ọkọ rẹ̀ bá jẹ́ ẹ̀jẹ́ tàbí de ara rẹ̀ ní ìdè lábẹ́ ìbúra,
A va im kah a caeng mai akhaw, olhlo lamloh a hinglu dongah rhuikhih a khih akhaw,
11 tí ọkọ rẹ̀ bá sì gbọ́, ṣùgbọ́n tí kò sọ̀rọ̀, tí kò sì kọ̀, nígbà náà ni ẹ̀jẹ́ rẹ̀ yóò dúró.
A va loh a yaak vaengah a taengah hil a phah tih anih khaban pawt daengah ni a olcaeng boeih cak vetih a hinglu dongah a khih a rhuikhih boeih khaw a cak eh.
12 Ṣùgbọ́n tí ọkọ rẹ̀ bá sọ wọ́n dasán, nígbà tí ó gbọ́, nígbà náà kò sí ẹ̀jẹ́ tàbí ìdè tí ó ti ẹnu rẹ̀ jáde tí yóò dúró, ọkọ rẹ̀ ti sọ wọ́n dasán, Olúwa yóò tú u sílẹ̀.
A va loh a yaak hnin ah te te a phae, a phae tih a hmuilai kah aka thoeng boeih, a olcaeng khaw, a hinglu dongkah rhuikhih khaw cak sak mai mahpawh. Te rhoek te a va loh a phae dongah BOEIPA loh huta te khodawk a ngai ni.
13 Ọkọ rẹ̀ lè ṣe ìwádìí tàbí sọ ọ́ dasán ẹ̀jẹ́ tàbí ìbúra ìdè tí ó ti ṣe láti fi de ara rẹ̀.
Olcaeng cungkuem neh, hinglu aka phaep ham rhuikhih olhlo cungkuem he a va loh a cak sak mai tih a va loh a phae mai thai.
14 Ṣùgbọ́n tí ọkọ rẹ̀ kò bá sọ nǹkan kan sí í nípa rẹ̀ ní ọjọ́ dé ọjọ́, nígbà náà ni ó ṣe ìwádìí nípa ẹ̀jẹ́ àti ìbúra ìdè tí ó dè é. Kí ọkùnrin náà ṣe ìwádìí lórí rẹ̀ láìsọ nípa rẹ̀ si nígbà tí ó gbọ́ nípa rẹ̀.
Tedae a taengah a va te a hnin hnin ah a ngam la ngam khaming. A yaak hnin ah pataeng a taengah a ngam dongah huta kah olcaeng boeih te cak tih a sokah a rhuikhih boeih cak.
15 Bí ó ti wù kí ó rí, bí ọkùnrin náà bá sọ ọ́ dasán, ní àkókò kan lẹ́yìn tí ó ti gbọ́ wọn, nígbà náà ó jẹ̀bi ọ̀rọ̀ náà.”
A yaak neh te te a phae la a phae atah huta kah amah lothaesainah te phueih saeh.
16 Èyí ni ìlànà tí Olúwa fún Mose nípa ìbátan láàrín ọkùnrin àti obìnrin àti láàrín baba àti ọ̀dọ́mọbìnrin rẹ̀ tí ó sì ń gbé ní ilé rẹ̀.
He oltlueh he tongpa laklo neh a yuu taengkah ham, pa laklo a camoe kah a napa im ah aka om a canu ham BOEIPA loh Moses te a uen pah.

< Numbers 30 >