< Numbers 27 >
1 Ọmọbìnrin Selofehadi ọmọ Heferi, ọmọ Gileadi, ọmọ Makiri ọmọ Manase tó jẹ́ ìdílé Manase, ọmọ Josẹfu wá. Orúkọ àwọn ọmọbìnrin náà ni Mahila, Noa, Hogla, Milka àti Tirsa.
Hagi Serofehati'a Hefa mofavre manigeno, Hefa'a Giliati mofavre manigeno, Makiri'a Manase mofavre manigeno, Manase'a Josefe mofavre mani'ne. Hagi Selofehati'a a' erino 5fu'a mofanege zmante'neankino zamagi'a ama'ne, Malaki, Noaki, Hoglaki, Milkaki Tirsa'e.
2 Wọ́n súnmọ́ ẹnu-ọ̀nà àgọ́ ìpàdé wọ́n sì dúró níwájú Mose, àti Eleasari àlùfáà, àti níwájú àwọn olórí àti ìjọ, wọ́n sì wí pé,
Hagi ana mofanemo'za Mosesene Pristi ne' Eleasane Israeli vahete kva vahe zagamofo zamavuga atrumahu seli mono nomofo kasante vu'za amanage hu'naze,
3 “Baba wa kú sí aginjù. Kò sí lára àwọn ẹgbẹ́ Kora tí wọ́n kó ara wọn pọ̀ lòdì sí Olúwa, ṣùgbọ́n ó kú nítorí ẹ̀ṣẹ̀ rẹ̀ kò sì fi ọmọkùnrin sílẹ̀.
nerafa'ma ka'ma kopima fri'neana Kora naga'mo'zama Ra Anumzamofoma ha'ma rentazageno zamahe fri'nea vahe'enena ofri'neanki ne'mofavre'a kaseonte'neno agra'a kumi huno fri'ne.
4 Kín ni ó dé tí orúkọ baba wa yóò parẹ́ nínú ìdílé rẹ̀ nítorí pé kò ní ọmọkùnrin? Fún wa ní ilẹ̀ ìní láàrín àwọn arákùnrin baba wa.”
Hagi nahanigeno nerafa agimo'a agri'a nagapintira fanane hugahie? Na'ankure agra ne'mofavrea kase onte'ne. Hagi nerafa nagamokizmi mopafintira mago'a mopa refako huramigahaze.
5 Nígbà náà Mose mú ọ̀rọ̀ wọn wá síwájú Olúwa.
Hazageno Mosese'a ana kezamia erino Ra Anumzamofonte vigeno,
Ra Anumzamo'a amanage huno Mosesena asmi'ne,
7 “Ohun tí àwọn ọmọbìnrin Selofehadi ń sọ tọ̀nà. O gbọdọ̀ fún wọn ní ogún ìní ti baba wọn.
Selofehati mofa'ne naga'mo'za fatgo kante kea nehaze. Hagi nezamafa nagapintira nezmafa mopama me'neniama'a erizamige'za, erisantihare'za nezmafa afuhe'zama manisafina maniho.
8 “Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli, ‘Tí ọkùnrin kan bá kú tí kò sì fi ọmọkùnrin sáyé, ẹ fún àwọn ọmọbìnrin rẹ̀ ní ogún ìní rẹ̀.
Hagi mago'ane Israeli vahera zamasamio, mago ne'mo'ma ne' mofavre ote'neno fri'nesigeta, ana ne'mofo mopa erita mofa'amofo aminkeno erisantihareno.
9 Tí kò bá ní ọmọbìnrin, fi ohun ìní rẹ́ fún àwọn arákùnrin rẹ̀.
Hagi ana ne'mo'ma mofa'ma onte'neno frinige'za, afuhe'i erizamiho.
10 Tí kò bá ní arákùnrin, fi ogún ìní rẹ̀ fún arákùnrin baba rẹ̀.
Hagi afuhe'zama omani'nenazana agrama erisantima harenia mopa, nefa afu'agna eri zamigahaze.
11 Tí baba rẹ̀ kò bá ní arákùnrin, fún ará ilé rẹ̀ tí ó bá súnmọ́ jù ní ìdílé rẹ̀ ní ogún ìní rẹ̀, kí ó lè jogún rẹ̀. Èyí gbọdọ̀ jẹ́ ìlànà ìdájọ́ fún àwọn ọmọ Israẹli gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.’”
Hagi ana ne'mofo nefa afu'aganahe'zama omani'nesazana, agri'a nagapi vahe eri zamige'za erisantihareho. Ama anankemo'a Ra Anumza'mo'ma Mosesema hunte'nea kante Israeli vahepina trake megahie.
12 Nígbà náà Olúwa sọ fún Mose pé, “Lọ sì orí òkè Abarimu yìí, kí o sì lọ wo ilẹ̀ tí mo fún àwọn ọmọ Israẹli.
Ra Anumzamo'a Mosesena amanage huno asami'ne, Abarimi agonare marerinka Israeli vahe'ma zami'noa kokana ko.
13 Lẹ́yìn ìgbà tí o bá sì ti rí i, ìwọ náà yóò darapọ̀ mọ́ àwọn ènìyàn rẹ gẹ́gẹ́ bí Aaroni arákùnrin rẹ ṣe ṣe,
Hagi ana mopama ketenunka negagana Aroni'ma hu'neaza hunka frigahane.
14 nítorí nígbà tí ìlú ṣọ̀tẹ̀ níbi omi ní aginjù Sini, tí gbogbo yín ṣe àìgbọ́ràn sí mi láti yà mí sí mímọ́ níwájú wọn.” (Èyí ni omi Meriba ní Kadeṣi ní aginjù Sini.)
Na'ankure Zini ka'ma kopina Nagrama hi'oma hu'na tanasamu'a keni'a amagera onte'na'e. Hagi Israeli vahe'mo'zama zamarimpa knama hunenantageta'a, Nagrikura ruotage hu'ne huta Israeli vahepina erinte amara osu'na'e. (E'ina tina Kadasi ka'ma kopi Meriba me'ne.)
15 Mose sọ fún Olúwa wí pé,
Anante Mosese'a Ra Anumzamofona anage huno asami'ne,
16 “Jẹ́ kí Olúwa, Ọlọ́run ẹ̀mí gbogbo ènìyàn, kí ó yan ọkùnrin kan sí orí ìjọ ènìyàn yìí,
Ra Anumzana maka'zama zamasimu'ma nezamina Anumzamoka, Israeli vahe'ma kegavama hania nera mago azeri otigeno,
17 láti máa darí wọn, ẹni tí yóò mú wọn jáde, tí yóò sì mú wọn wọlé, gbogbo ènìyàn Olúwa kí yóò dàbí àgùntàn tí kò ní olùṣọ́.”
ana ne'mo ugota huzmanteno zamavareno vuno eno nehanige'za, Ra Anumzamofo vahe'mo'za sipisipimo'za kegava huzmante vahe omani'nege'za savri hu'za manizanknara osugahaze.
18 Nígbà náà ní Olúwa sọ fún Mose pé, “Mú Joṣua ọmọ Nuni, ọkùnrin nínú ẹni tí èmi wà, kí o sì gbé ọwọ́ rẹ lé e.
Hagi Ra Anumzamo'a Mosesena anage huno kenona hunte'ne, Agripima avamu'ma mani'nea ne' Nuni nemofo Josuana asenira kazana antenka nunamuna hunto.
19 Jẹ́ kí ó dúró níwájú Eleasari àlùfáà àti ojú gbogbo àwọn ìjọ ènìyàn Israẹli kí o sì fi àṣẹ fún un ní ojú wọn.
Hagi mika vahe zamavufi pristi ne' Eleasa avuga Josuana avrenka vunka eri'zama erisia eri'zana ome huhamprinto.
20 Kí ìwọ kí ó sì fi nínú ọláńlá rẹ sí i lára, kí gbogbo ìjọ àwọn ọmọ Israẹli kí ó lè gbọ́rọ̀ sí i lẹ́nu.
Anante eri'zama eneri'na hihamu mago'a amige'za, miko Israeli vahe'mo'za ke'a antahimi'za avaririho.
21 Kí ó dúró níwájú Eleasari àlùfáà, tí yóò gba ìpinnu fún láti béèrè Urimu níwájú Olúwa. Gẹ́gẹ́ bí òfin yìí ni òun pẹ̀lú gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli yóò jáde lọ, pẹ̀lú òfin rẹ̀ sì ni wọn ó wọlé.”
Hagi Josuama maka zampima Nagri navesi'ma kenaku'ma hanuno'a Eleasa pristi ne'mofo avuga vanigeno, Eleasa'a urimi havea erino Nagri navesi zana keno erifore hugahie. Hanigeno Eleasa'a mika nanekea Josuana asami'nigeno, Israeli vahera zamavareno vuno eno hugahie.
22 Mose sì ṣe gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti sọ fún un. Ó mú Joṣua ó sì mú kí ó dúró níwájú Eleasari àlùfáà àti níwájú gbogbo ìjọ.
Hagi Ra Anumzamo'ma huoma huno hunteaza huno Mosese'a Josuana avreno pristi ne' Eleasane Israeli vahe zamavuga vu'ne.
23 Nígbà náà ni ó gbé ọwọ́ rẹ̀ le e, ó sì fi àṣẹ fún un gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.
Hagi Mosese'a Ra Anumzamo'ma hunte'nea kante anteno Josuana asenirera azana anteno huhamprinte'ne.