< Numbers 25 >

1 Nígbà tí àwọn Israẹli dúró ní Ṣittimu, àwọn ènìyàn sì bẹ̀rẹ̀ sí í ṣe àgbèrè pẹ̀lú àwọn ọmọbìnrin Moabu,
Na ka noho a Iharaira ki Hitimi, a ka anga te iwi ka moepuku ki nga tamahine a Moapa.
2 tí ó pè wọ́n sí ibi ẹbọ òrìṣà wọn. Àwọn ènìyàn náà jẹun wọ́n sì foríbalẹ̀ níwájú òrìṣà wọn.
Na ratou hoki i karanga te iwi ki nga patunga tapu ma o ratou atua: na kai ana te iwi, a koropiko ana ki o ratou atua.
3 Báyìí ni Israẹli ṣe darapọ̀ mọ́ wọn tí wọ́n sì jọ ń sin Baali-Peori. Ìbínú Olúwa sì ru sí wọn.
Na ka whakaukia a Iharaira ki a Paarapeoro, a ka mura te riri o Ihowa ki a Iharaira.
4 Olúwa sọ fún Mose pé, “Mú gbogbo àwọn olórí àwọn ènìyàn wọ̀nyí, pa wọ́n kí o sì fi wọ́n kọ́ sórí igi ní gbangba nínú oòrùn níwájú Olúwa, kí ìbínú Olúwa lè kúrò ní ọ̀dọ̀ Israẹli.”
Na ka mea a Ihowa ki a Mohi, Tangohia nga ariki katoa o te iwi, taronatia hoki ki te aroaro o Ihowa, i te ritenga atu o te ra, kia tahuri atu ai i a Iharaira te riri o Ihowa e mura nei.
5 Mose sọ fún àwọn onídàájọ́ Israẹli, “Ẹnìkọ̀ọ̀kan yín gbọdọ̀ pa arákùnrin rẹ̀ èyí tí ó darapọ̀ ní fífi orí balẹ̀ fún Baali-Peori.”
Na ka mea a Mohi ki nga kaiwhakawa o Iharaira, Patua e tenei, e tenei o koutou ona tangata i whakaukia ki a Paarapeoro.
6 Nítòótọ́ ọ̀kan lára àwọn ọmọkùnrin Israẹli sì mú obìnrin Midiani wá síwájú ojú Mose àti gbogbo ìjọ ti Israẹli wọ́n sì ń sọkún ní àbáwọlé àgọ́ ìpàdé.
Na, ka puta tetahi o nga tama a Iharaira, e mau ana mai i tetahi wahine Miriani ki ona teina i te tirohanga atu a Mohi, i te tirohanga atu ano hoki a te whakaminenga katoa o nga tama a Iharaira, i a ratou e tangi ana i te whatitoka o te tapenakar a o te whakaminenga.
7 Nígbà tí Finehasi, ọmọ Eleasari, ọmọ Aaroni, àlùfáà, rí èyí, ó fi ìjọ sílẹ̀, pẹ̀lú ọ̀kọ̀ ní ọwọ́ rẹ̀.
A, no te kitenga o Pinehaha, tama a Ereatara, tama a Arona tohunga, ka whakatika i te whakaminenga, ka hopu i te tao ki tona ringa;
8 Ó sì tẹ̀lé arákùnrin Israẹli yìí lọ sínú àgọ́. Ó sì fi ọ̀kọ̀ gún àwọn méjèèjì ní àgúnyọ láti ara ọkùnrin Israẹli àti sí ara obìnrin náà. Nígbà náà ni àjàkálẹ̀-ààrùn lórí àwọn ọmọ Israẹli sì dúró;
Na ka haere i muri i te tangata o Iharaira ki te teneti, a weohia ana raua tokorua, te tangata o Iharaira, me te wahine hoki i tona tia. A mutu iho te whiu o nga tama a Iharaira.
9 ṣùgbọ́n gbogbo àwọn tí ó kú nínú àjàkálẹ̀-ààrùn náà jẹ́ ẹgbàá méjìlá.
A ko te hunga i mate i te whiu e rua tekau ma wha mano.
10 Olúwa sì tún sọ fún Mose pé,
Na ka korero a Ihowa ki a Mohi, ka mea,
11 “Finehasi ọmọ Eleasari ọmọ Aaroni, àlùfáà, ti yí ìbínú mi padà kúrò lọ́dọ̀ àwọn ọmọ Israẹli, nítorí tí ó ní ìtara bí èmi náà ti ní ìtara fún iyì mi láàrín wọn, kí ó lè jẹ́ pé èmi ló pa wọ́n run nínú ìtara mi sí wọn.
Na Pinehaha, tama a Ereatara, tama a Arona tohunga, toku riri i anga ke atu ai i nga tama a Iharaira, i tona ngakau hae penei i toku i roto i a ratou, i kore ai nga tama a Iharaira e poto i ahau, i ahau e hae ana.
12 Nítorí náà sọ fún un pé èmi ṣe májẹ̀mú àlàáfíà mi pẹ̀lú rẹ̀.
Mo reira me ki atu e koe, Nana, ka hoatu e ahau ki a ia taku kawenata mo te rangimarie:
13 Òun àti irú-ọmọ rẹ̀ yóò ní májẹ̀mú láéláé fún iṣẹ́ àlùfáà, nítorí pé ó ní ìtara fún Ọlọ́run rẹ̀ láti fi yẹ́ Ọlọ́run sí, ó sì ṣe ètùtù fún àwọn ọmọ Israẹli.”
A ka mau ki a ia, ki ona uri hoki i muri i a ia, hei kawenata kia mau tonu te mahi tohunga; mona i hae, he whakaaro ki tona Atua, i mea whakamarietanga ano hoki mo nga tama a Iharaira.
14 Orúkọ ọmọ Israẹli tí a pa pẹ̀lú obìnrin Midiani náà ni Simri, ọmọ Salu, olórí ilé kan nínú àwọn ọmọ Simeoni.
A ko te ingoa o te tangata o Iharaira i patua, i patua tahitia ra me te wahine Miriani, ko Timiri tama a Haru, he rangatira no tetahi whare kaumatua i roto i nga Himioni.
15 Orúkọ ọmọbìnrin Midiani náà tí a pa ní Kosbi ọmọbìnrin Suri, tí ṣe olóyè àwọn ẹ̀yà kan nínú ìdílé kan ní Midiani.
Ko te ingoa hoki o te wahine Miriani i patua nei ko Kohopi, he tamahine na Turu; he rangatira ia no tetahi iwi, no tetahi whare kaumatua o Miriana.
16 Olúwa sì tún sọ fún Mose pé,
Na ka korero a Ihowa ki a Mohi, ka mea,
17 “Ka àwọn ará Midiani sí ọ̀tá, kí o sì pa wọ́n,
Whakataria he pakanga ki nga Miriani, patua hoki:
18 nítorí pé wọ́n ṣe sí yín gẹ́gẹ́ bí ọ̀tá nígbà tí wọ́n tàn yín nípa ìṣẹ̀lẹ̀ Peori, àti arábìnrin wọn Kosbi ọmọbìnrin ìjòyè Midiani kan, obìnrin tí a pa nígbà tí àjàkálẹ̀-ààrùn ṣẹlẹ̀ nítorí Peori.”
E whakatari ano hoki ratou i a koutou ki a ratou mahi tinihanga, i tinihangatia ra koutou e ratou i te mea mo Peoro, i te mea hoki mo Kohipi, tamahine a te rangatira o Miriana, he tuahine no ratou, i patua ra i te ra o te whiunga mo Peoro.

< Numbers 25 >