< Numbers 24 >

1 Nísinsin yìí nígbà tí Balaamu rí i wí pé ó tẹ́ Olúwa lọ́rùn láti bùkún àwọn Israẹli, kò lo ọ̀nà ìṣoṣó gẹ́gẹ́ bí ti ìgbà ìṣáájú, ṣùgbọ́n ó yí ojú rẹ̀ sí apá aginjù.
Israel yoethen paek te BOEIPA mikhmuh ah hoeikhang tila Balaam loh a hmuh dongah lung te doe ham voei vai khaw cet pawh. Te dongah a maelhmai te khosoek la a khueh.
2 Nígbà tí Balaamu wo ìta ó sì rí Israẹli tí wọ́n pàgọ́ gẹ́gẹ́ bí ẹ̀yà wọn, Ẹ̀mí Ọlọ́run sì bà sórí rẹ̀
Balaam loh a mik a huel vaengah Israel te amah koca la kho a sak tih Pathen Mueihla a soah a om te a hmuh.
3 ó sì sọ àsọtẹ́lẹ̀ rẹ̀, “Àsọtẹ́lẹ̀ tí Balaamu ọmọ Beori, àsọtẹ́lẹ̀ ẹni tí ojú rẹ̀ ríran kedere,
Te vaengah a thuidoeknah te a poh tih Beor capa Balaam olphong neh mikdai dai hlang kah olphong te a thui.
4 àsọtẹ́lẹ̀ ẹni tí ó gbọ́ ọ̀rọ̀ Ọlọ́run, ẹni tí ó ríran láti ọ̀dọ̀ Olódùmarè, ẹni tí ó dojúbolẹ̀, tí ojú rẹ̀ là kedere.
Pathen ol aka ya kah olphong tah Tlungthang mikhlam aka tla te a hmuh tih a mik a dai.
5 “Àgọ́ rẹ ti dára tó, ìwọ Jakọbu, àti ibùgbé rẹ, ìwọ Israẹli!
Jakob nang kah dap neh Israel nang kah dungtlungim tah metlam a hoeikhang.
6 “Gẹ́gẹ́ bí àfonífojì tí ó tàn jáde, gẹ́gẹ́ bí ọgbà tí ó wà ní ẹ̀bá odò ńlá, gẹ́gẹ́ bí igi aloe tí Olúwa gbìn, gẹ́gẹ́ bí igi kedari tí ó wà lẹ́bàá odò.
Soklong bangla langdai, tuiva kah dum bangla, BOEIPA kah a phung thingul bangla, tui taengkah lamphai bangla,
7 Omi yóò sàn láti inú garawa: èso wọn yóò ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ omi. “Ọba wọn yóò ga ju Agagi lọ; ìjọba wọn yóò di gbígbéga.
A tuiduen lamloh tui sih tih a tiingan khaw tui yet dongah om. A manghai Agag lakah a vetih a ram a phueih ni.
8 “Ọlọ́run mú wọn jáde láti Ejibiti wá; wọ́n ní agbára gẹ́gẹ́ bí i ti àgbáǹréré. Wọ́n jẹ orílẹ̀-èdè tí ń ṣe ọ̀tá rẹ̀ run, wọ́n sì fọ́ egungun wọn sí túútúú; wọ́n ó sì fi ọfà wọn ta wọ́n ní àtapòyọ.
Pathen loh anih te Egypt lamloh amah taengah cung ki bangla a loh. A rhal namtom te a ngaeh coeng dongah a rhuh te a cilh vetih a thaltang neh a phop ni.
9 Ó tẹríba ó sì dùbúlẹ̀ bí kìnnìún, bí abo kìnnìún: ta ni ó gbọdọ̀ jí wọn? “Ìbùkún ni fún ẹni tí ó bùkún fún ọ, kí ìfibú jẹ́ ti ẹni tí ó fi ọ́ bú!”
Sathueng neh sathuengnu bangla koisu tih yalh phoeiah tah anih aka haeng te unim? Nang loh yoethen na paek te a yoethen tih nang loh thae na phoei khaw thaephoei a yook.
10 Nígbà náà ni ìbínú Balaki sì dé sí Balaamu. Ó sì fi ọwọ́ lu ọwọ́ ó wí pé, “Mo pè ọ́ láti bú àwọn ọ̀tá mi ṣùgbọ́n o tún bùkún fún wọn nígbà mẹ́ta yìí.
Te vaengah Balak kah thintoek te Balaam taengah sai tih a kut te a paeng. Balak loh Balaam te, “Ka thunkha rhoek te tap ham ni nang kang khue dae he rhoek kah yoethen la voei thum yoethen na paek coeng he.
11 Nísinsin yìí sálọ sí ibùjókòó rẹ! Èmi ti rò láti sọ ọ́ di ẹni ńlá, ṣùgbọ́n Olúwa tí fà ọ́ sẹ́yìn láti gba èrè yìí.”
Te dongah namah hmuen la nang te yong laeh. Nang te kan thangpom rhoe kan thangpom eh ka ti coeng dae BOEIPA loh nang te thangpomnah lamkah n'hloh coeng ne,” a ti nah.
12 Balaamu dá Balaki lóhùn, “Ǹjẹ́ èmi kò sọ fún àwọn ìránṣẹ́ tí o rán sí mi wí pé,
Te dongah Balaam loh Balak te, “Kai taengla na puencawn nan tueih taengah khaw ka thui moenih a?
13 ‘Kódà bí Balaki bá fún mi ní ààfin rẹ̀ tí ó kún fún fàdákà àti wúrà, èmi kò le ṣe ohunkóhun lọ́wọ́ ara mi, yálà búburú tàbí rere, láti kọjá òfin Olúwa: ohun tí Olúwa bá wí ni èmi ó sọ’?
Kai he Balak loh cak neh sui a im kah a bae la m'pae cakhaw BOEIPA olka te poe hamla ka coeng moenih. Then cakhaw thae cakhaw ngai ham om. Ka lungbuei lamlong pataeng BOEIPA kah a thui te ni ka thui eh ka ti.
14 Nísinsin yìí mò ń padà lọ sí ọ̀dọ̀ àwọn ènìyàn mi, ṣùgbọ́n jẹ́ kí èmi kí ó kìlọ̀ fún ọ nítorí nǹkan tí àwọn ènìyàn wọ̀nyí yóò ṣe sí àwọn ènìyàn rẹ ní ọjọ́ iwájú.”
Kai tah ka pilnam taengla ka cet pawn ni he. Halo lamtah hmailong tue ah he pilnam loh na pilnam soah a saii ham te nang kang uen eh?,” a ti nah.
15 Nígbà náà ni ó bẹ̀rẹ̀ òwe: “Òwe Balaamu ọmọ Beori, òwe ẹni tí ojú rẹ̀ ríran kedere,
Te phoeiah a thuidoeknah a dangrhoek tih Beor capa Balaam kah olphong neh mik aka dai hlang kah olphong te a thui.
16 ẹni tó gbọ́ ọ̀rọ̀ Ọlọ́run ń wí, tí ó sì mọ ìmọ̀ Ọ̀gá-ògo, tí ó ríran láti ọ̀dọ̀ Olódùmarè, ẹni tí ó dọ̀bálẹ̀, tí ojú rẹ̀ sì ṣí:
Pathen kah olthui aka ya tih Khohni mingnah aka ming, tlungthang mikhlam aka hmu tih a bakop doela mik aka dai kah olphong loh,
17 “Mo rí i, ṣùgbọ́n kì í ṣe ìsinsin yìí. Mo kíyèsi, ṣùgbọ́n kò súnmọ́. Ìràwọ̀ kan yóò jáde láti ọ̀dọ̀ Jakọbu; yóò yọ jáde láti Israẹli. Yóò tẹ̀ fọ́ orí Moabu, yóò sì fọ́ agbárí gbogbo ọmọ Seti.
Amah te ka hmuh dae tahae ah moenih, amah te ka mae dae yoei pawh. Jakob lamkah aisi thoeng vetih Israel lamloh mancai thoo ni. Moab baengki a phop pah vetih Seth koca te boeih a phuet ni.
18 Wọn yóò borí Edomu; yóò ṣẹ́gun Seiri ọ̀tá rẹ̀, ṣùgbọ́n Israẹli yóò dàgbà nínú agbára.
Edom kah a pang om vetih a thunkha Seir kah a pang om cakhaw Israel loh thadueng neh a saii ni.
19 Olórí yóò jáde láti Jakọbu yóò sì pa àwọn tó ṣẹ́kù nínú ìlú náà run.”
Jakob lamloh a taemrhai vetih khopuei kah rhaengnaeng te a milh sak ni.
20 Nígbà náà ni Balaamu rí Amaleki ó sì bẹ̀rẹ̀ òwe: “Amaleki ni àkọ́kọ́ nínú àwọn orílẹ̀-èdè, ṣùgbọ́n yóò dahoro níkẹyìn.”
Amalek te a hmuh vaengah a thuidoeknah a poh tih, “Amaklek tah namtom kah a tongnah la om dae a hmailong tah pocinah la om.
21 Nígbà náà ní ó rí ará Keni ó sì bẹ̀rẹ̀ òwe: “Ibùgbé rẹ ní ààbò, ìtẹ́ rẹ ni a tò sínú àpáta;
Keni te a hmuh vaengah a thuidoeknah te a poh tih, “Na ngolhmuen khangmai tih thaelpang soah bu na khueh.
22 síbẹ̀ ẹ̀yin ará Keni ni yóò di píparun nígbà tí Asiria bá mú yín ní ìgbèkùn.”
Tedae hatah Assyria loh nang n'sol duela Kain te hlup hamla om bitni,” a ti nah.
23 Nígbà náà ni ó bẹ̀rẹ̀ òwe rẹ̀: “Háà, ta ni ó lè yè nígbà tí Ọlọ́run bá ṣe èyí?
A thuidoeknah a poh tih, “Anunae Pathen loh te a saii vaengah unim aka hing ve?
24 Ọkọ̀ yóò wá láti ibùdókọ̀ Kittimu; wọn yóò ṣẹ́gun Asiria àti Eberi, ṣùgbọ́n àwọn náà yóò di píparun.”
Kittim lihmoi lamkah timbaw rhoek neh Assyria khaw phaep uh ni. Eber khaw a phaep uh ni. Tedae amah khaw pocinah ham ni,” a ti nah.
25 Nígbà náà ni Balaamu dìde ó sì padà sí ilé rẹ̀, Balaki sì lọ ní ọ̀nà tirẹ̀.
Te phoeiah Balaam te thoo tih aka cet te amah hmuen la mael. Te dongah Balak khaw amah longpuei la cet.

< Numbers 24 >