< Numbers 24 >
1 Nísinsin yìí nígbà tí Balaamu rí i wí pé ó tẹ́ Olúwa lọ́rùn láti bùkún àwọn Israẹli, kò lo ọ̀nà ìṣoṣó gẹ́gẹ́ bí ti ìgbà ìṣáájú, ṣùgbọ́n ó yí ojú rẹ̀ sí apá aginjù.
Be wali, Ba: ila: me da Hina Gode da Ea Isala: ili dunu ilima hahawane dogolegele aligima: ne ilegemu fawane hanai, amo e dawa: i galu. Amaiba: le, ea musa: hou defele hame hamoi. E da dawa: digima: ne olelesu liligi amo hogomusa: hame asi. E da hafoga: i soge ba: musa: sinidigili,
2 Nígbà tí Balaamu wo ìta ó sì rí Israẹli tí wọ́n pàgọ́ gẹ́gẹ́ bí ẹ̀yà wọn, Ẹ̀mí Ọlọ́run sì bà sórí rẹ̀
Isala: ili dunu ilia fisisu ba: i. E da ilia sosogo fi afae afae dafulili esalebe ba: i. Gode Ea A: silibu Hadigidafa da ema aligila sa: ili,
3 ó sì sọ àsọtẹ́lẹ̀ rẹ̀, “Àsọtẹ́lẹ̀ tí Balaamu ọmọ Beori, àsọtẹ́lẹ̀ ẹni tí ojú rẹ̀ ríran kedere,
e da amo ba: la: lusu sia: i, “Ba: ila: me, Bio ea mano, da moloiwane ba: sa. Ea sia: da agoane gala.
4 àsọtẹ́lẹ̀ ẹni tí ó gbọ́ ọ̀rọ̀ Ọlọ́run, ẹni tí ó ríran láti ọ̀dọ̀ Olódùmarè, ẹni tí ó dojúbolẹ̀, tí ojú rẹ̀ là kedere.
Nowa da Gode Ea sia: dalebe nababela: ? Na da si godonasini agoane sosodosa. Na da esala ba: lala, Gode Bagadedafa da nama olelesa.
5 “Àgọ́ rẹ ti dára tó, ìwọ Jakọbu, àti ibùgbé rẹ, ìwọ Israẹli!
Isala: ili ilia abula diasu da isisima: goi ba: sa.
6 “Gẹ́gẹ́ bí àfonífojì tí ó tàn jáde, gẹ́gẹ́ bí ọgbà tí ó wà ní ẹ̀bá odò ńlá, gẹ́gẹ́ bí igi aloe tí Olúwa gbìn, gẹ́gẹ́ bí igi kedari tí ó wà lẹ́bàá odò.
Ilia da gumudi yobo dadalei sedade defele. O ifabi hano bega: bugi agoane ba: sa. Ilia da gabusiga: ifa Hina Gode Ea bugi defele, o dolo ifa, hano bega: lelebe agoane ba: sa.
7 Omi yóò sàn láti inú garawa: èso wọn yóò ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ omi. “Ọba wọn yóò ga ju Agagi lọ; ìjọba wọn yóò di gbígbéga.
Ilia da gibu dabe bagade ba: mu. Ilia da hawa: amo nasegagi hano bagade soge ganodini bugimu. Ilia hina bagade da A: iga: ge ea hou bagadewane baligimu. Ea ouligisu hou da soge bagohame amoga heda: mu.
8 “Ọlọ́run mú wọn jáde láti Ejibiti wá; wọ́n ní agbára gẹ́gẹ́ bí i ti àgbáǹréré. Wọ́n jẹ orílẹ̀-èdè tí ń ṣe ọ̀tá rẹ̀ run, wọ́n sì fọ́ egungun wọn sí túútúú; wọ́n ó sì fi ọfà wọn ta wọ́n ní àtapòyọ.
Gode da ili Idibidi sogega fisili masa: ne, oule misi. E da sigua bulamagau defele, ili fidima: ne gegenana. Ilia da ilia ha lai dunu amo na dagosa. Ilia da ilia gasa goudasa amola ilia dadi wadela: lesisa.
9 Ó tẹríba ó sì dùbúlẹ̀ bí kìnnìún, bí abo kìnnìún: ta ni ó gbọdọ̀ jí wọn? “Ìbùkún ni fún ẹni tí ó bùkún fún ọ, kí ìfibú jẹ́ ti ẹni tí ó fi ọ́ bú!”
Isala: ili fi da gasa bagade laione wa: me agoane. E da golai dialea, dunu eno da beda: iba: le, hamedafa didilisisa. Nowa da Isala: ili hahawane dogolegelewane aligima: ne ilegesea, da Gode Ea hahawane dogolegesu ba: mu. Amola nowa da Isala: ili ilima gagabusu aligima: ne ilegesea, da amo gagabusu sinidigili hihima aligima: ne ilegei dagoi ba: mu.”
10 Nígbà náà ni ìbínú Balaki sì dé sí Balaamu. Ó sì fi ọwọ́ lu ọwọ́ ó wí pé, “Mo pè ọ́ láti bú àwọn ọ̀tá mi ṣùgbọ́n o tún bùkún fún wọn nígbà mẹ́ta yìí.
Ba: ila: ge da ougili ea lobo usuna gaguli, Ba: ila: mema amane sia: i, “Na da di na ha lai dunu amo gagabusu aligima: ne ilegema sia: i. Be udiana agoane di da amo mae hamone, ilima Gode Ea hahawane dogolegesu hou aligima: ne sia: i dagoi.
11 Nísinsin yìí sálọ sí ibùjókòó rẹ! Èmi ti rò láti sọ ọ́ di ẹni ńlá, ṣùgbọ́n Olúwa tí fà ọ́ sẹ́yìn láti gba èrè yìí.”
Dia diasuga masa! Na da dima bidi bagade imunu sia: i. Be Hina Gode da dia amo bidi lama: ne logo hedofai dagoi.”
12 Balaamu dá Balaki lóhùn, “Ǹjẹ́ èmi kò sọ fún àwọn ìránṣẹ́ tí o rán sí mi wí pé,
Ba: ila: me da bu adole i, “Na da sia: ne iasu dunu di nama asunasi ilima olelei, amane,
13 ‘Kódà bí Balaki bá fún mi ní ààfin rẹ̀ tí ó kún fún fàdákà àti wúrà, èmi kò le ṣe ohunkóhun lọ́wọ́ ara mi, yálà búburú tàbí rere, láti kọjá òfin Olúwa: ohun tí Olúwa bá wí ni èmi ó sọ’?
‘Ba: ila: ge da silifa amola gouli ea hina bagade diasu ganodini gala amo huluanedafa nama ia: noba, na da ni hanaiga Hina Gode Ea hamoma: ne sia: i fonobahadi nama sia: i amo giadofamu da hamedela: loba. Na da Hina Gode Ea nama sia: i liligi fawane bu sia: mu.”
14 Nísinsin yìí mò ń padà lọ sí ọ̀dọ̀ àwọn ènìyàn mi, ṣùgbọ́n jẹ́ kí èmi kí ó kìlọ̀ fún ọ nítorí nǹkan tí àwọn ènìyàn wọ̀nyí yóò ṣe sí àwọn ènìyàn rẹ ní ọjọ́ iwájú.”
Ba: ila: me da Ba: ila: gema amane sia: i, “Na da wali na fidafa amoga buhagimu. Be hidadea, na da dima sisasu sia: mu. Amalu da fa: no Isala: ili dunu ilia hou dia fi dunuma hamomu, amo na da dima sia: mu.”
15 Nígbà náà ni ó bẹ̀rẹ̀ òwe: “Òwe Balaamu ọmọ Beori, òwe ẹni tí ojú rẹ̀ ríran kedere,
Amalalu, e da amo ba: la: lusu amane sia: i, “Ba: ila: me, Bio ea mano, da moloiwane ba: sa. Ea sia: da agoane gala.
16 ẹni tó gbọ́ ọ̀rọ̀ Ọlọ́run ń wí, tí ó sì mọ ìmọ̀ Ọ̀gá-ògo, tí ó ríran láti ọ̀dọ̀ Olódùmarè, ẹni tí ó dọ̀bálẹ̀, tí ojú rẹ̀ sì ṣí:
Na da Gode Ea sia: dalebe naba. Na da si godonasini agoane sosodosa. Na da esalebe ba: lala, Gode Bagadedafa da nama olelesa.
17 “Mo rí i, ṣùgbọ́n kì í ṣe ìsinsin yìí. Mo kíyèsi, ṣùgbọ́n kò súnmọ́. Ìràwọ̀ kan yóò jáde láti ọ̀dọ̀ Jakọbu; yóò yọ jáde láti Israẹli. Yóò tẹ̀ fọ́ orí Moabu, yóò sì fọ́ agbárí gbogbo ọmọ Seti.
Na da hobea misunu hou ba: la: lala. Na da Isala: ili fi ba: sa. Hina Bagade dunu, hadigi bagade gasumuni agoai, amo fi ganodini heda: lebe ba: mu. E da ofa: su gasumuni defele Isala: ili sogega misunu. E da Moua: be ouligisu dunu famu amola Sede soge dunu amo banenesimu.
18 Wọn yóò borí Edomu; yóò ṣẹ́gun Seiri ọ̀tá rẹ̀, ṣùgbọ́n Israẹli yóò dàgbà nínú agbára.
E da ea ha lai dunu Idome sogega esala amo hasalili, ilia soge huluane suguli lamu. Amola Isala: ili dunu da hasaliliwane masunu.
19 Olórí yóò jáde láti Jakọbu yóò sì pa àwọn tó ṣẹ́kù nínú ìlú náà run.”
Isala: ili fi dunu da ilia ha lai amo osa: le heda: le, dunu hame bogoi esalebe, amo huluane fane legemu.”
20 Nígbà náà ni Balaamu rí Amaleki ó sì bẹ̀rẹ̀ òwe: “Amaleki ni àkọ́kọ́ nínú àwọn orílẹ̀-èdè, ṣùgbọ́n yóò dahoro níkẹyìn.”
Amalalu, Ba: ila: ge da ea esala ba: su amo ganodini A: malege fi ba: lalu, amane ba: la: lusu sia: i, “A: malege ea gasa bagade hou da eno fi huluane baligi dagoi. Be fa: no e da gugunufinisi dagoi ba: mu.”
21 Nígbà náà ní ó rí ará Keni ó sì bẹ̀rẹ̀ òwe: “Ibùgbé rẹ ní ààbò, ìtẹ́ rẹ ni a tò sínú àpáta;
Amalalu, Ba: ila: ge da ea esalebe ba: su amo ganodini, Ginaide dunu fi ba: i. E da amo ba: la: lusu sia: i, “Dia esalebe sogebi da gaga: i dagoi. Sio ea bibi da gafulu bagade amoga bibiba: le, eno liligiga wadela: lesimu hamedei.
22 síbẹ̀ ẹ̀yin ará Keni ni yóò di píparun nígbà tí Asiria bá mú yín ní ìgbèkùn.”
Be dilia Ginaide dunu da gugunufinisi dagoi ba: mu. Bai Asilia dunu da dili doagala: le, suguli lamu.”
23 Nígbà náà ni ó bẹ̀rẹ̀ òwe rẹ̀: “Háà, ta ni ó lè yè nígbà tí Ọlọ́run bá ṣe èyí?
Ba: ila: me da eno ba: la: lusu amane sia: i, “Dunu da gadili (north) amogawi gilisilalebe da nowa dunula: ?
24 Ọkọ̀ yóò wá láti ibùdókọ̀ Kittimu; wọn yóò ṣẹ́gun Asiria àti Eberi, ṣùgbọ́n àwọn náà yóò di píparun.”
Doagala: su golili dasu dunu da Saibalase sogega, dusagai ganodini manebe ba: mu. Ilia da Asilia amola Ibe amo hasalimu. Be Saibalase dunu amola da fa: no gugunufinisi dagoi ba: mu.”
25 Nígbà náà ni Balaamu dìde ó sì padà sí ilé rẹ̀, Balaki sì lọ ní ọ̀nà tirẹ̀.
Amalalu, Ba: ila: me da momagele, hi diasuga buhagi. Amola Ba: ila: ge da hi logoga asi.