< Numbers 23 >

1 Balaamu wí fún Balaki pé, “Kọ́ pẹpẹ méje fún mi níbí, kí o sì mú akọ màlúù méje àti àgbò méje wá fún mi.”
Балаам а зис луй Балак: „Зидеште-мь аич шапте алтаре ши прегэтеште-мь аич шапте вицей ши шапте бербечь.”
2 Balaki ṣe bí Balaamu ti sọ, àwọn méjèèjì fi akọ màlúù kọ̀ọ̀kan àti àgbò kọ̀ọ̀kan rú ẹbọ lórí pẹpẹ kọ̀ọ̀kan.
Балак а фэкут кум спусесе Балаам, ши Балак ши Балаам ау адус кыте ун вицел ши кыте ун бербек пе фиекаре алтар.
3 Nígbà náà Balaamu sọ fún Balaki pé, “Dúró ti ẹbọ sísun rẹ kí èmi sì lọ sí ẹ̀gbẹ́ kan. Bóyá Olúwa yóò farahàn mí. Ohunkóhun tí ó bá fihàn mí, èmi yóò wí fún ọ.” Nígbà náà ó sì lọ sí ibi gíga.
Балаам а зис луй Балак: „Стай лынгэ ардеря та де тот, ши еу мэ вой депэрта де еа; поате кэ Домнул ымь ва еши ынаинте ши че-мь ва дескопери ыць вой спуне.” Ши с-а дус пе ун лок ыналт.
4 Ọlọ́run sì pàdé rẹ̀, Balaamu sì sọ pé, “Mo tí ṣe pẹpẹ méje, lórí pẹpẹ kọ̀ọ̀kan mo ti fi akọ màlúù àti àgbò kọ̀ọ̀kan rú ẹbọ.”
Думнезеу а венит ынаинтя луй Балаам ши Балаам Й-а зис: „Ам ридикат шапте алтаре ши, пе фиекаре алтар, ам адус кыте ун вицел ши кыте ун бербек.”
5 Olúwa sì fi ọ̀rọ̀ sí ẹnu Balaamu ó wí pé, “Padà sí ọ̀dọ̀ Balaki kí o sì jẹ́ iṣẹ́ yìí fún un.”
Домнул а пус кувинте ын гура луй Балаам ши а зис: „Ынтоарче-те ла Балак ши аша сэ-й ворбешть.”
6 Ó sì padà sí ọ̀dọ̀ rẹ̀ ó sì ba tí ó dúró ti ẹbọ sísun rẹ̀, pẹ̀lú gbogbo àwọn ìjòyè Moabu.
Балаам с-а ынторс ла Балак ши ятэ кэ Балак стэтя лынгэ ардеря луй де тот, ел ши тоате кэпетенииле Моабулуй.
7 Nígbà náà ni Balaamu sọ ọ̀rọ̀-ìjìnlẹ̀ jáde wí pé, “Balaki mú mi láti Aramu wá, ọba Moabu láti òkè ìlà-oòrùn wá Ó wí pé, ‘Wá fi Jakọbu bú fún mi; wá, kí o sì jẹ́rìí sí Israẹli.’
Балаам шь-а ростит пророчия ши а зис: „Балак м-а адус дин Арам (Месопотамия). Ымпэратул Моабулуй м-а кемат дин мунций Рэсэритулуй, зикынд: ‘Вино ши блестемэ-мь пе Иаков! Вино ши дефэймязэ-мь пе Исраел!’
8 Báwo ní èmi ó ṣe fi bú àwọn tí Ọlọ́run kò fi bú? Báwo ni èmi ó ṣe bá wọn wí àwọn tí Olúwa kò bá wí?
Кум сэ блестем еу пе чел че ну-л блестемэ Думнезеу? Кум сэ дефэймез еу пе чел пе каре ну-л дефэймязэ Домнул?
9 Láti ṣóńṣó ibi gíga orí àpáta ni mo ti rí wọn, láti orí ibi gíga ni mo ti ń wò wọ́n. Mo rí àwọn ènìyàn tí ń gbé lọ́tọ̀ wọn kò sì ka ará wọn kún ara àwọn orílẹ̀-èdè.
Ыл вэд дин вырфул стынчилор, Ыл привеск де пе ынэлцимя дялурилор: Есте ун попор каре локуеште деопарте Ши ну фаче парте динтре нямурь.
10 Ta ni ó lè ka eruku Jakọbu tàbí ka ìdámẹ́rin Israẹli? Jẹ́ kí èmi kú ikú olódodo, kí ìgbẹ̀yìn mi kí ó dà bí tirẹ̀!”
Чине поате сэ нумере пулберя луй Иаков Ши сэ спунэ нумэрул унуй сферт дин Исраел? О, де аш мури де моартя челор неприхэниць Ши сфыршитул меу сэ фие ка ал лор!”
11 Balaki sọ fún Balaamu pé, “Kí lo ṣe fún mi? Mo gbé ọ wá láti fi àwọn ọ̀tá mi bú, ṣùgbọ́n o kò ṣe nǹkan kan, ṣùgbọ́n o bùkún wọn!”
Балак а зис луй Балаам: „Че мь-ай фэкут? Те-ам луат сэ блестемь пе врэжмашул меу, ши ятэ кэ ту-л бинекувынтезь!”
12 Ó sì dáhùn wí pé, “Ṣé kí n má sọ nǹkan tí Olúwa fi sí mi lẹ́nu?”
Ел а рэспунс ши а зис: „Ну требуе оаре сэ спун че-мь пуне Домнул ын гурэ?”
13 Nígbà náà Balaki sọ fún un pé, “Wá pẹ̀lú mi sí ibòmíràn tí o ti lè rí wọn; wà á rí díẹ̀, ṣùgbọ́n kì í ṣe gbogbo wọn. Láti ibẹ̀, wá fi wọ́n bú fún mi.”
Балак й-а зис: „Вино, те рог, ку мине ын алт лок, де унде ыл поць ведя, кэч аич ну везь декыт о парте дин ел, ну-л везь ынтрег. Ши де аколо сэ ми-л блестемь.”
14 Ó sì lọ sí pápá Sofimu ní orí òkè Pisga, ó sì kọ́ pẹpẹ méje síbẹ̀ ó sì fi akọ màlúù àti àgbò kọ̀ọ̀kan rú ẹbọ lórí pẹpẹ kọ̀ọ̀kan.
Л-а дус ын кымпул Цофим, спре вырфул мунтелуй Писга, а зидит шапте алтаре ши а адус кыте ун вицел ши ун бербек пе фиекаре алтар.
15 Balaamu ṣo fún Balaki pé, “Dúró níbí ti ẹbọ sísun rẹ nígbà tí mo bá lọ pàdé rẹ̀ níbẹ̀.”
Балаам а зис луй Балак: „Стай аич, лынгэ ардеря та де тот, ши еу мэ вой дуче ынаинтя луй Думнезеу.”
16 Olúwa pàdé Balaamu ó sì fi ọ̀rọ̀ sí ní ẹnu wí pé, “Padà lọ sí ọ̀dọ̀ Balaki kí o sì jíṣẹ́ fún un.”
Домнул а венит ынаинтя луй Балаам, й-а пус кувинте ын гурэ ши а зис: „Ынтоарче-те ла Балак ши аша сэ-й ворбешть.”
17 Nígbà náà ó lọ sí ọ̀dọ̀ rẹ̀ ó sì bá à tí ó dúró ti ẹbọ sísun rẹ̀ pẹ̀lú àwọn ìjòyè Moabu. Balaki sì béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé, “Kí ni Olúwa wí?”
Балаам с-а ынторс ла ел, ши ятэ кэ Балак стэтя лынгэ ардеря луй де тот, ку кэпетенииле Моабулуй. Балак й-а зис: „Че ць-а спус Домнул?”
18 Nígbà náà ó bẹ̀rẹ̀ ọ̀rọ̀ sísọ, “Dìde, Balaki; kí o sì gbọ́ mi ọmọ Sippori.
Балаам шь-а ростит пророчия ши а зис: „Скоалэ-те, Балак, ши аскултэ! Я аминте ла мине, фиул луй Ципор!
19 Ọlọ́run kì í ṣe ènìyàn, tí yóò fi purọ́, tàbí ọmọ ènìyàn, tí ó lè yí ọkàn rẹ̀ padà. Ǹjẹ́ ó sọ̀rọ̀ kí ó má ṣe é? Ǹjẹ́ ó ti ṣèlérí kí ó má mu un ṣẹ?
Думнезеу ну есте ун ом, ка сэ минтэ, Нич ун фиу ал омулуй, ка сэ-Й парэ рэу. Че а спус, оаре ну ва фаче? Че а фэгэдуит, оаре ну ва ымплини?
20 Èmi gba àṣẹ láti bùkún; Ó sì ti bùkún, èmi kò sì lè yípadà.
Ятэ кэ ам примит порункэ сэ бинекувынтез. Да, Ел а бинекувынтат, ши еу ну пот ынтоарче.
21 “Kò rí ẹ̀ṣẹ̀ kankan nínú Jakọbu, kò sì rí búburú kankan nínú Israẹli. Olúwa Ọlọ́run wọn sì wà pẹ̀lú wọn. Ìhó ọba sì wà pẹ̀lú wọn.
Ел ну веде ничо фэрэделеӂе ын Иаков, Ну веде ничо рэутате ын Исраел. Домнул Думнезеул луй есте ку ел, Ел есте Ымпэратул луй, веселия луй.
22 Ọlọ́run mú wọn jáde láti Ejibiti wá, wọ́n ní agbára màlúù ẹhànnà.
Думнезеу й-а скос дин Еӂипт, Тэрия Луй есте пентру ел ка а биволулуй.
23 Kò ní àfọ̀ṣẹ sí Jakọbu, tàbí àfọ̀ṣẹ sí àwọn Israẹli. Nísinsin yìí a ó sọ nípa ti Jakọbu àti Israẹli, ‘Wo ohun tí Ọlọ́run ti ṣe!’
Дескынтекул ну поате фаче нимик ымпотрива луй Иаков, Нич врэжитория ымпотрива луй Исраел. Акум се поате спуне деспре Иаков ши Исраел: ‘Че лукрурь марь а фэкут Думнезеу!’
24 Àwọn ènìyàn náà yóò dìde bí abo kìnnìún; wọ́n yóò sì gbé ara wọn sókè bí i kìnnìún òun kì yóò sì dùbúlẹ̀ títí yóò fi jẹ ohun ọdẹ títí yóò sì fi mu nínú ẹ̀jẹ̀ ohun pípa.”
Да, попорул ачеста се скоалэ ка о леоайкэ Ши се ридикэ ынтокмай ка ун леу. Ну се кулкэ пынэ че н-а мынкат прада Ши н-а бэут сынӂеле челор учишь.”
25 Nígbà náà ni Balaki wí fún Balaamu pé, “O kò kúkú fi wọ́n bú, bẹ́ẹ̀ ni o kò súre fún wọn rárá!”
Балак а зис луй Балаам: „Ну-л блестема, дар мэкар нич ну-л бинекувынта!”
26 Balaamu dáhùn ó sì wí fún Balaki pé, “Ǹjẹ́ èmi kò ha ti wí fún ọ pé, gbogbo èyí tí Olúwa bá sọ, òun ni èmi yóò ṣe?”
Балаам а рэспунс ши а зис луй Балак: „Ну ць-ам спус кэ вой фаче тот че ва спуне Домнул?”
27 Nígbà náà Balaki sọ fún Balaamu pé, “Wá jẹ́ kí èmi kí ó mú ọ lọ sí ibòmíràn bóyá yóò tẹ́ Ọlọ́run lọ́rùn kí ó fi wọ́n bú láti ibẹ̀ lọ.”
Балак а зис луй Балаам: „Вино, те рог, те вой дуче ынтр-ун алт лок; поате кэ Думнезеу ва гэси ку кале сэ-мь блестемь де аколо пе попорул ачеста!”
28 Balaki gbé Balaamu wá sí orí òkè Peori, tí ó kọjú sí aginjù.
Балак а дус пе Балаам пе вырфул мунтелуй Пеор, каре есте ку фаца спре пустиу.
29 Balaamu sì wí fún Balaki pé, “Mọ pẹpẹ méje fún mi níbí kí o sì pèsè akọ màlúù àti àgbò fún mi.”
Балаам а зис луй Балак: „Зидеште-мь аич шапте алтаре ши прегэтеште-мь аич шапте вицей ши шапте бербечь!”
30 Balaki sì ṣe bí Balaamu ti sọ fún un, ó sì gbé akọ màlúù kan àti àgbò lórí pẹpẹ kọ̀ọ̀kan.
Балак а фэкут кум зисесе Балаам ши а адус кыте ун вицел ши кыте ун бербек пе фиекаре алтар.

< Numbers 23 >