< Numbers 22 >

1 Nígbà náà àwọn ọmọ Israẹli rin ìrìnàjò lọ sí pẹ̀tẹ́lẹ̀ Moabu wọ́n sì pa ibùdó lẹ́gbẹ̀ẹ́ Jordani tí ó kọjá lọ sí Jeriko.
Isala: ili dunu da bu asili, Moua: be umi soge amo Yodane Hano ea eso mabe la: idi, Yeligou moilai bai bagade la: idila la: idilale diala, amogawi ilia fisisu hamoi.
2 Nísinsin yìí, Balaki ọmọ Sippori rí gbogbo ohun tí àwọn Israẹli ti ṣe sí àwọn ará Amori,
Moua: be hina bagade Ba: ila: ge (Sibo egefe), e da Isala: ili ilia hou amo A: moulaide dunuma hamoi amola ilia idi bagade nababeba: le,
3 ẹ̀rù sì ba Moabu nítorí pé ọ̀pọ̀ ènìyàn wà níbẹ̀ nítòótọ́, Moabu kún fún ẹ̀rù nítorí àwọn ọmọ Israẹli.
e amola ea fi dunu huluane da bagadewane beda: i galu.
4 Moabu sọ fún àwọn àgbàgbà Midiani pé, “Nísinsin yìí ni àwọn wọ̀nyí yóò lá gbogbo ohun tí ó yí wa ká, bí màlúù ṣe ń jẹ koríko tí ó wà nínú oko.” Bẹ́ẹ̀ ni Balaki ọmọ Sippori, tí ó jẹ́ ọba Moabu nígbà náà,
Moua: be dunu da Midia: ne fi dunu ilima amane sia: i, “Bulamagau gawali da gisi bugi ganodini gisi na ebelesa, amo defele Isala: ili fi bagade da ninia liligi huluane wadela: lesimu.”
5 rán oníṣẹ́ pé Balaamu ọmọ Beori, tí ó wà ní Petori, ní ẹ̀bá odò Eufurate, ti ilẹ̀ àwọn ènìyàn rẹ. Balaki sọ pé, “Àwọn ènìyàn kan jáde wá láti Ejibiti; wọ́n bo gbogbo ilẹ̀ ayé wọ́n sì pa ibùdó súnmọ́ ọ̀dọ̀ mi.
Amaiba: le, hina bagade Ba: ila: ge da sia: ne iasu dunu ilia Ba: ila: me (Bio egefe, e da Bidio moilai Amoue soge Iufala: idisi Hano gadenene esalu), amo dunu ema misa: ne sia: si. Sia: ne iasu dunu da Ba: ila: ge ea sia: amane sia: si, “Di da amo liligi dawa: ma: ne na da sia: sisa. Dunu fi bagade da Idibidi sogega goeguda: misi dagoi. Amo dunu da soge huluane amoga a: i ahoa, amola ilia da ninia soge huluane lamusa: magagisa.
6 Nísinsin yìí, wá fi àwọn ènìyàn wọ̀nyí bú, nítorí wọ́n ní agbára jù fún mi. Nípa ṣíṣe èyí èmi ó ṣẹ́gun wọn, kí n sì lé wọn kúrò ní ilẹ̀ yìí. Nítorí tí mo mọ̀ pé ìbùkún ni fún àwọn tí ìwọ bá bùkún, ìfibú sì ni ẹni tí ìwọ bá fi bú.”
Ilia idi da ninia idi baligi dagoi. Amaiba: le, di goeguda: misini, na fidima: ne ilima gagabusu aligima: ne ilegema. Amasea, amabela: ? ninia da ilima hasalimu amola ninia soge fisimusa: ili sefasimu. Na dawa: ! Di da dunu hahawane esaloma: ne sia: sea, ilia da hahawane esalumu, amola di da ilima gagabusu aligima: ne ilegesea, amo gagabusu da ilima aligi dialumu.”
7 Àti àwọn àgbàgbà Moabu àti Midiani sì lọ pẹ̀lú owó àyẹ̀wò lọ́nà wọn, nígbà tí wọ́n dé ọ̀dọ̀ Balaamu, wọ́n sọ nǹkan tí Balaki sọ fún wọn.
Amaiba: le, Moua: be amola Midia: ne ouligisu dunu da amo gagabusu ilegesu dabe sia: amo gaguli asili, Ba: ila: mema doaga: le, Ba: ila: ge ea sia: ema sia: ne i.
8 “Ẹ sùn níbí lálẹ́ yìí,” Balaamu sọ fún un pé, “èmi ó padà wá fún un yín ní èsì nǹkan tí Olúwa bá wí fún mi.” Nítorí tí àwọn ìjòyè Moabu dúró sọ́dọ̀ rẹ̀.
Ba: ila: me da ilima amane sia: i, “Wali guiguda: golale, aya na da Hina Gode Ea nama sia: mu, amo dilima olelemu.” Amaiba: le, Moua: be ouligisu dunu da Ba: ila: me ili esalu.
9 Ọlọ́run tọ Balaamu wá ó sì wí pé, “Ta ni àwọn ọkùnrin tí ó wà pẹ̀lú rẹ yìí?”
Gode da Ba: ila: mema misini, amane sia: i, “Amo dunu dili esalebe da nowa dunula: ?”
10 Balaamu sọ fún Ọlọ́run pé, “Balaki ọmọ Sippori, ọba Moabu, rán iṣẹ́ yìí sí mi pé,
Ba: ila: me da bu adole i, “Moua: be hina bagade Ba: ila: ge da ili nama amane olelema: ne asunasi,
11 ‘Àwọn ènìyàn kan ti ilẹ̀ Ejibiti jáde wá tí wọ́n bo ojú ilẹ̀. Nísinsin yìí, wá, kí o wá fi wọ́n bú fún mi. Bóyá èmi yóò lè bá wọn jà, èmi ó sì lé wọn jáde.’”
‘Dunu fi amo da Idibidi sogega misi da soge huluane amoga a: i ahoa. E da agoane hanai gala, amo na da gagubusu ilima aligima: ne ilegemu. Amasea, e da ilima doagala: le, gadili sefasimusa: dawa: mu.”
12 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run sọ fún Balaamu pé, “Má ṣe bá wọn lọ. Ìwọ kò gbọdọ̀ gé ègún lé àwọn ènìyàn náà lórí, nítorí a ti bùkún wọn.”
Gode da Ba: ila: mema amane sia: i, “Amo dunu mae sigi masa! Amola Isala: ili fi dunu ilima gagabui aligima: ne mae ilegema! Bai Na da ilima hahawane dogolegele hou ilegele i dagoi.”
13 Ní òwúrọ̀ ọjọ́ kejì Balaamu dìde ó sì sọ fún àwọn ìjòyè Balaki pé, “Ẹ padà sí orílẹ̀-èdè yín, nítorí tí Olúwa ti kọ̀ láti jẹ́ kí n tẹ̀lé yín.”
Golale, hahabe, Ba: ila: me da Ba: ila: ge ea sia: ne iasu dunuma asili, amane sia: i, “Dilia diasuga buhagima! Hina Gode da, na dili mae sigi masa: ne sia: i dagoi.”
14 Nígbà náà àwọn ìjòyè Moabu sì padà tọ Balaki lọ wọ́n sì wí pé, “Balaamu kọ̀ láti tẹ̀lé wa.”
Amaiba: le, ilia da Ba: ila: ge ema buhagili, Ba: ila: me da ili mae sigi misa: ne sia: i amo ema olelei.
15 Nígbà náà Balaki rán àwọn ìjòyè mìíràn tí wọ́n pọ̀ àwọn tí wọ́n sì níyì ju alákọ́kọ́ lọ.
Amalalu, Ba: ila: ge da sia: ne iasu dunu ilia idi da musa: asi dagoi, amo ilia hou da musa: asi hou ilia baligi, amo asunasi.
16 Wọ́n lọ sí ọ̀dọ̀ Balaamu wọ́n sì sọ pé, “Èyí ni ohun tí Balaki ọmọ Sippori sọ, má ṣe jẹ́ kí ohunkóhun kí ó dè ọ́ lọ́nà láti wá sí ọ̀dọ̀ mi,
Ilia da Ba: ila: mema asili, Ba: ila: ge ea sia: ema amane alofele i, “Na dima ha: giwane edegesa. Misa! Logo ga: su liligi mae dawa: ma!
17 nítorí pé èmi yóò fún ọ ní ẹ̀bùn dáradára, èmi yóò sì ṣe ohunkóhun tí ìwọ bá sọ. Wá, kí o sì wá fi àwọn ènìyàn wọ̀nyí bú fún mi.”
Na da bidi bagadewane dima imunu, amola dia hanai adole ba: su huluane hamomu. Na dima ha: giwane edegesa. Misa! Amola na fidima: ne amo Isala: ili dunu fi ilima gagabui aligima: ne ilegema.”
18 Ṣùgbọ́n Balaamu dá wọn lóhùn pé, “Kódà tí Balaki bá fún mi ní ààfin rẹ̀ tí ó kún fún fàdákà àti wúrà, èmi kò ní ṣe ohunkóhun tí ó tóbi tàbí kéré tí ó kọjá òfin Olúwa Ọlọ́run mi.
Be Ba: ila: me da bu adole i, “Ba: ila: ge da silifa amola gouli ea hina bagade diasu ganodini amo huluanedafa nama ianoba, na da Hina Gode Ea sia: fonobahadi afae fawane giadofamu da nama hamedei gala: loba.
19 Nísinsin yìí ẹ dúró níbí di ọjọ́ kejì gẹ́gẹ́ bí àwọn tókù ti ṣe nígbà náà èmi yóò mọ ohun tí Olúwa yóò tún sọ fún mi.”
Be dilia musa: misi dunu defele, wali gasia goeguda: esaloma. Bai na da Hina Godema bu adole ba: mu. Amabela: ? E da nama sia: eno ganabela: ?”
20 Ní alẹ́ ọjọ́ náà Ọlọ́run sì tọ Balaamu wá ó sì sọ wí pé, “Nígbà tí ọkùnrin yìí ti wá pè ọ́, lọ pẹ̀lú wọn, ṣùgbọ́n ẹnu nǹkan tí mo sọ fún ọ ni kí o ṣe.”
Amo gasia, Gode da Ba: ila: mema misini, amane sia: i, “Amo dunu da dia ili sigi masa: ne sia: musa: misi galea, defea, dia liligi momagele, ili sigi masa. Be Na hamoma: ne sia: i defele amo fawane hamoma.”
21 Balaamu dìde ní òwúrọ̀, ó sì di ẹrù lé kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀ òun pẹ̀lú àwọn ìjòyè Moabu.
Amaiba: le, hahabe, Ba: ila: me da ea dougi amo da: iya fa: le fisu amo lala: gilalu, fila heda: le, Moua: be ouligisu dunu amola sigi asi.
22 Ṣùgbọ́n Ọlọ́run bínú gidigidi, angẹli Olúwa sì dúró lójú ọ̀nà láti dojú ìjà kọ ọ́. Balaamu ń gun kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀ lọ, àwọn ìránṣẹ́ rẹ̀ méjì sì wà pẹ̀lú rẹ̀.
Ba: ila: me da ahoabeba: le, Gode da ougi ba: i. Amaiba: le, Ba: ila: me da ea dougi da: iya fila heda: le, ea hawa: hamosu dunu aduna amola gilisili: logoga ahoanoba, Hina Gode Ea a: igele dunu da ea logo hedofamusa: , logo dogoa lelu.
23 Nígbà tí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ náà sì rí angẹli Olúwa tí ó dúró ní ojú ọ̀nà pẹ̀lú idà tí a fàyọ ní ọwọ́ rẹ̀, ó kọjú kúrò ní ọ̀nà lọ sínú oko. Balaamu sì lù ú pé kí ó gbé òhun padà lọ sí ojú ọ̀nà.
Dougi da a: igele dunu gegesu gobihei bagade gaguliwane lelebe ba: beba: le, e da logo fisili, bu la: ididili sega sa: i. Ba: ila: me da ea dougi fananu, bu logoga logei.
24 Nígbà náà angẹli Olúwa dúró ní ojú ọ̀nà tóóró láàrín ọgbà àjàrà, pẹ̀lú ògiri ní ọ̀nà méjèèjì.
Amalalu, a:igele dunu da logo donoboi amo da waini efe sagai amo da igiga gagoi, amo dibiga asili, lelu.
25 Nígbà tí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rí angẹli Olúwa, ó lẹ̀ mọ́ ẹ̀gbẹ́ ògiri, ó sì rún ẹsẹ̀ Balaamu mọ́ ògiri. Nígbà náà, ó tún nà án, lẹ́ẹ̀kan sí i.
Dougi da a: igele ba: beba: le, logo la: idi amoga bobogala: le, Ba: ila: me ea emo da igiga gagoi amo damana fanasili gigidinai. Ba: ila: me da bu enowane dougi fai.
26 Nígbà náà angẹli Olúwa súnmọ́ wájú ó sì dúró níbi ọ̀nà tóóró níbi tí kò ti sí ọ̀nà láti yípadà, bóyá ní ọ̀tún tàbí òsì.
A: igele da eno ba: le gaidi asili, donoboidafa logo sogebi, la: ididili amola la: ididili baligimu hamedei sogebi, amoga lelu.
27 Nígbà tí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rí angẹli Olúwa, ó sì jókòó ní abẹ́ Balaamu, inú sì bí i tó sì nà án pẹ̀lú ọ̀pá rẹ̀.
Dougi da bu a: igele dunu ba: beba: le, osoboga diagudui. Ba: ila: me ea ougi bagade heda: le, e da dougi amo ea galiamoga fananu.
28 Nígbà náà Olúwa ṣí ẹnu kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, ó sì sọ fún Balaamu pé, “Kí ni mo ṣe fún ọ tí o fi nà mí lẹ́ẹ̀mẹ́ta?”
Amalalu, Hina Gode da dougi amoma, dunuga sia: be agoane sia: ma: ne, gasa i. Dougi da Ba: ila: mema amane sia: i, “Na da dima adi hamobela: ? Di da abuliba: le, na udiana agoane udigili fabela: ?”
29 Balaamu sọ fún kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ pé, “Nítorí ìwọ fi mí ṣẹ̀sín! Bí mo bá ní idà ní ọwọ́ ni èmi ìbá pa ọ́ nísinsin yìí.”
Ba: ila: me da bu adole i, “Bai di da na gagaoui dunu agoane ba: ma: ne, hamoi dagoi! Na da gegesu gobihei bagade gagui ganiaba, na da di medole legela: loba.”
30 Kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ sọ fún Balaamu pé, “Ṣé mi kì í ṣe kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ ni, tí o máa ń gùn ní gbogbo ìgbà, láti ìgbà pípẹ́ wá? Ǹjẹ́ mo hu irú ìwà báyìí sí ọ rí?” “Rárá,” Ó dáhùn.
Dougi da bu adole i, “Na da dia dougi amola dia esalusu ganodini di da eso huluane nama fila heda: le ahoanusu. Na da amo hou musa: dima hamobela: ?” Ba: ila: me da bu adole i, “Hame mabu!”
31 Nígbà náà Olúwa ṣí ojú Balaamu, ó sì rí angẹli Olúwa tí ó dúró ní ojú ọ̀nà pẹ̀lú idà rẹ̀ tí ó fàyọ. Ó sì tẹ orí rẹ̀ ba.
Amalalu, Hina Gode da Ba: ila: mema amo a: igele dunu gegesu gobihei bagade gaguiwane lelebe amo ba: ma: ne, e si doasi. Amalalu, Ba: ila: me da hina: odagi osoba guduli gala: lasa: i.
32 Nígbà náà angẹli Olúwa béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé, “Kí ni ó dé tí o fi na kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ nígbà mẹ́ta yìí? Mo wá síbí láti kọ ojú ìjà sí ọ nítorí ọ̀nà rẹ kò tọ́ níwájú mi.
A: igele da ema amane sia: i, “Dia abuliba: le udiana agoane dia dougi fabela: ? Na da dia logo hedofamusa: misi dagoi! Bai di da amodili masunu da defea hame galebe.
33 Kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rí mi ó sì yà kúrò fún mi lẹ́ẹ̀mẹ́ta yìí. Tí ó bá jẹ́ wí pé kò yà kúrò. Èmi kì ìbá ti pa ọ́ pátápátá nísinsin yìí, ṣùgbọ́n Èmi yóò sì dá òun sí.”
Be dia dougi da na ba: lalu udiana agoane sinidigi. E da agoai hame hamosa ganiaba, na da di fane legela: loba, amola dougi hame fane legela: loba.”
34 Balaamu sọ fún angẹli Olúwa pé, “Mo ti dẹ́ṣẹ̀, èmi kò mọ̀ pé o dúró níwájú ọ̀nà láti dojúkọ mí, nísinsin yìí tí inú rẹ kò bá dùn, èmi ó padà.”
Ba: ila: me da bu adole i, “Na da wadela: le hamoi dagoi. Di da na logo hedofamusa: logoga lelu, na da hame dawa: i galu. Be di da na bu masunu da defea hame dawa: sea, na da na diasuga buhagimu.”
35 Angẹli Olúwa sọ fún Balaamu pé, “Lọ pẹ̀lú àwọn arákùnrin náà, ṣùgbọ́n nǹkan tí mo sọ fún ọ nìkan ni kí o sọ.” Nígbà náà Balaamu lọ pẹ̀lú àwọn ìjòyè Balaki.
Be a: igele da ema amane sia: i, “Di mae buhagili, amo dunu sigi masa. Be na dima adomu liligi fawane sia: ma!” Amaiba: le, Ba: ila: me da Moua: be ouligisu dunu amola bu sigi asi.
36 Nígbà tí Balaki gbọ́ pé Balaamu ń bọ̀ wá, ó jáde lọ láti lọ pàdé rẹ̀ ní ìlú Moabu tí ó wà ní agbègbè Arnoni, ní ẹ̀gbẹ́ ilẹ̀ rẹ̀.
Ba: ila: ge da Ba: ila: me ea manebe sia: nababeba: le, e da A moilai bai bagade (Anone Hano bega: amola Moua: be soge alalo amoga dialu) amoga Ba: ila: me yosia: musa: asi.
37 Balaki sì sọ fún Balaamu pé, “Ǹjẹ́ èmi kò a ránṣẹ́ kánjúkánjú sí ọ? Kí ló dé tí ìwọ kò fi wá sí ọ̀dọ̀ mi? Ṣé èmi kò tó láti sọ ọ́ di ẹni ńlá?”
Ba: ila: ge da Ba: ila: mema amane sia: i, “Dia abuliba: le na da musa: misa: ne sia: i amoga hame misibala: ? Dia adi dawa: bela: ? Na da dima bidi defele imunu hamedebela: ?”
38 Balaamu sì wí fún Balaki pé, “Kíyèsi, èmi tọ̀ ọ́ wá, èmi kò ha ní agbára kan nísinsin yìí rárá láti wí ohun kan? Mo gbọdọ̀ sọ nǹkan tí Ọlọ́run fi sí mi lẹ́nu.”
Ba: ila: me da bu adole i, “Na da wali misi dagoi! Dafawanela: ? Be na da gasa hamedei. Na da Gode Ea nama sia: i liligi fawane sia: mu, amo fawane gasa gala.”
39 Nígbà náà Balaamu lọ pẹ̀lú Balaki sí Kiriati-Hosotia.
Amalalu, Ba: ila: me amola Ba: ila: ge da Gilia: de Husode moilai amoga asili,
40 Balaki rú ẹbọ akọ màlúù pẹ̀lú àgùntàn, ó sì fún Balaamu ní díẹ̀ pẹ̀lú àwọn ìjòyè tí ó wà ní ọ̀dọ̀ rẹ̀.
Ba: ila: ge da bulamagau amola sibi medole legele, amo ea hu mogili Ba: ila: me amola ouligisu dunu amo ili gilisili moma: ne ema i.
41 Ní òwúrọ̀ ọjọ́ kejì Balaki gbé Balaamu lọ sí Bamoti Baali, láti ibẹ̀ ló ti rí apá kan àwọn ènìyàn.
Golale, hahabe, Ba: ila: ge da Ba: ila: me amo Ba: imode Ba: ile (gado sogebi) amoga oule asi. Amoga, Ba: ila: me da Isala: ili fi dunu mogili ba: musa: dawa: i.

< Numbers 22 >