< Numbers 21 >

1 Nígbà tí ọba Aradi ará Kenaani, tí ń gbé ní gúúsù gbọ́ wí pé Israẹli ń bọ̀ wá ní ojú ọ̀nà Atarimu, ó bá Israẹli jà ó sì fi agbára mú díẹ̀ lára wọn.
A LOHE ae la ke alii o Arada ka Kanaana, e noho ana ma ke kukuluhema, e hele mai ana ka Iseraela ma ke ala e hiki ai i na wahi ona, alaila, kaua mai la ia i ka Iseraela, a lawe pio aku la i kekahi poe o lakou.
2 Nígbà náà ni Israẹli jẹ́ ẹ̀jẹ́ fún Olúwa pé, “Bí o bá lè fi àwọn ènìyàn yìí lé wa lọ́wọ́, gbogbo ìlú wọn ni a ó parun.”
Hoohiki aku la ka Iseraela ia Iehova, i aku la, Ina paha e haawi mai oe i keia poe kanaka iloko o ko'u lima, alaila e luku loa aku no au i na kulanakauhale o lakou.
3 Olúwa gbọ́ ẹ̀bẹ̀ àwọn ọmọ Israẹli, ó sì fi àwọn ará Kenaani lé wọn lọ́wọ́. Wọ́n pa wọ́n run pátápátá; torí náà ni a ṣe ń pe ibẹ̀ ní Horma.
Hoolohe mai la o Iehova i ka leo o ka Iseraela, a hoolilo mai la i ka poe Kanaana: a luku loa aku la lakou ia lakou la, a me na kulanakauhale o lakou; a kapa aku la ia i ka inoa o ia wahi o Horema.
4 Wọ́n rin ìrìnàjò láti òkè Hori lọ sí ọ̀nà tó lọ sí Òkun Pupa, láti kọjá yípo Edomu. Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn bínú ní ojú ọ̀nà;
Hele aku la lakou mai ke kuahiwi o Hora aku, ma ke alanui o ke Kaiula, e puni i ka aina o Edoma: a ua pau ke aho o na kanaka no ke alanui.
5 wọ́n sì sọ̀rọ̀ lòdì sí Ọlọ́run àti Mose, wọ́n wí pé, “Èéṣe tí ìwọ fi mú wa jáde láti Ejibiti kí a ba le wá kú sí aginjù yìí? Kò sí oúnjẹ! Kò sì sí omi! Àwa sì kórìíra oúnjẹ tí kò dára yìí!”
Olelo ino aku la na kanaka i ke Akua, a ia Mose, No ke aha la olua i kai mai nei ia makou mailoko mai o Aigupita e make ma ka waonahele? no ka mea, aohe berena, aole hoi ho wai; a ke hoopailua nei ko makou naau i keia ai mama.
6 Nígbà náà ni Olúwa rán ejò olóró sí àárín wọn; wọ́n gé àwọn ènìyàn jẹ, ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ Israẹli sì kú.
Hoouna mai la o Iehova i na nahesa wela iwaena o na kanaka, a nahu mai la lakou i na kanaka; a he nui na kanaka o ka Iseraela i make.
7 Àwọn ènìyàn sì wá sí ọ̀dọ̀ Mose wọn wí pé, “A ti dá ẹ̀ṣẹ̀ nígbà tí asọ̀rọ̀-òdì sí Olúwa àti sí ìwọ pẹ̀lú. Gba àdúrà pé kí Olúwa mú ejò náà kúrò lọ́dọ̀ wa.” Nígbà náà ni Mose gbàdúrà fún àwọn ènìyàn.
No ia mea, hele mai la na kanaka io Mose la, i mai la, Ua haua hewa makou; no ka mea, ua olelo ino aku makou ia Iehova a ia oe: e pule aku oe ia Iehova, e lawe aku ia i na nahesa mai o makou aku nei. A pule aku la o Mose no na kanaka.
8 Olúwa sọ fún Mose pé, “Rọ ejò, a ó sì gbé e kọ́ sókè lórí igi, ẹni tí ejò bá ti gé jẹ lè wò ó yóò sì yè.”
Olelo mai la o Iehova ia Mose, E hana oe nau i nahesa wela, a e kau aku ia maluna o ka laau, a o kela mea keia mea i nahuia, i ka wa e nana aku ai oia ia mea, e ola no ia.
9 Nígbà náà ni Mose sì rọ ejò onírin ó sì gbé e kọ́ sórí igi, bí ejò bá sì bu ẹnikẹ́ni jẹ bí ó bá ti wò ó yóò sì yè.
A hana iho la o Mose i nahesa keleawe, a kau aku la ia maluna o ka laau; a o ke kanaka i nahuia i ka nahesa wela, i ka wa i nana aku ai oia i ka nahesa keleawe, ua ola ia.
10 Àwọn ọmọ Israẹli tẹ̀síwájú wọ́n sì péjọ sí Obotu.
A hele aku la na mamo a Iseraela, a hoomoana iho la ma Obota.
11 Wọ́n gbéra ní Obotu wọ́n sì pa ibùdó sí Iye-Abarimu, ní aginjù tí ó kọjú sí Moabu ní ìdojúkọ ìlà-oòrùn.
A hele lakou mai Obota aku, a hoomoana iho la ma Iieabarima, i ka waonahele ma ke alo o Moaba, ma ka hikina o ka la.
12 Láti ibẹ̀ ni wọ́n ti gbéra wọ́n sì pa ibùdó ní àfonífojì Seredi.
Mailaila aku lakou i hele ai, a hoomoana iho la ma ke kahawai o Zareda.
13 Láti ibẹ̀ lọ, wọn ṣí, wọ́n sì dó sí ìhà kejì Arnoni, tí ó wà ní aginjù tí ó wà ní agbègbè ilẹ̀ àwọn ọmọ Amori. Arnoni jẹ́ ààlà fún ilẹ̀ Moabu, láàrín Moabu àti Amori.
Mailaila aku lakou i hele ai, a hoomoana iho la ma hela aoao o Arenona, ma ka waonahele e hele mai ana mailoko mai o na palena o ka Amora; no ka mea, o Arenona oia ka palena o Moaba, mawaena o Moaba a me ka Amora.
14 Ìdí nìyìí tí ìwé ogun Olúwa se wí pé, “…Wahebu ní Sufa, Òkun Pupa àti ní odò Arnoni
Nolaila, ua olelo ia maloko o ka buke o na kaua a Iehova, ma Vaheba ma Supa, a ma na kahawai o Arenona,
15 àti ní ìṣàn odò tí ó darí sí ibùjókòó Ari tí ó sì fi ara ti ìpínlẹ̀ Moabu.”
A ma ke kahe ana o na kahawai, ka mea hele ma ka noho ana o Ara, a moe iho ma ka palena o Moaba.
16 Láti ibẹ̀ ni wọ́n ti bẹ̀rẹ̀ rìn dé Beeri, èyí ni kànga tí Olúwa sọ fún Mose, “Kó àwọn ènìyàn jọ èmi ó sì fún wọn ní omi.”
Mailaila aku lakou a Beera; oia ka punawai kahi a Iehova i olelo mai ai ia Mose, E hoakoakoa i na kanaka, a e haawi aku no wau i wai no lakou.
17 Nígbà náà ni Israẹli kọ orin yìí pé, “Sun jáde, ìwọ kànga! Ẹ máa kọrin nípa rẹ̀,
Alaila mele aku la ka Iseraela i keia mele, E huahuai mai, e ka punawai; E mele aku oukou ia ia:
18 nípa kànga tí àwọn ọmọ-aládé gbẹ́, nítorí àwọn ọlọ́lá ènìyàn ni ó gbẹ́ ẹ; tí àwọn ọlọ́lá àwọn ènìyàn sì fi ọ̀pá aládé àti ọ̀pá oyè wọn gbẹ́.” Nígbà náà wọ́n kúrò láti aginjù lọ sí Mattana,
O na luna ka i kohi iho i ka punawai, O na'lii o na kanaka i eli iho ia, Mamuli o ka Lunakanawai, me na kookoo o lakou. A mai ka waonahele aku lakou a Matana;
19 láti Mattana lọ sí Nahalieli, láti Nahalieli lọ sí Bamoti,
A mai Matana aku a Nahaliela; a mai Nahaliela aku a Bamota:
20 àti láti Bamoti lọ sí àfonífojì ní Moabu níbi tí òkè Pisga, tí ó wà ní òkè ilé omi ti kọjú sí aginjù.
A mai Bamota aku lakou a i ke awawa ma ke kula o Moaba, malalo o ka puu o Pisega, ma ka aoao e huli ana i ka waonahele.
21 Israẹli rán oníṣẹ́ láti sọ fún Sihoni ọba àwọn ará Amori wí pé,
Hoouna aku la ka Iseraela i na elele io Sihona la ke alii o ka Amora, i aku la,
22 “Jẹ́ kí a kọjá ní orílẹ̀-èdè rẹ. A kò ní kọjá sí inú oko pápá tàbí ọgbà àjàrà àbí mu omi láti inú kànga. A máa gba òpópónà náà ti ọba títí tí a ó fi la ilẹ̀ rẹ kọjá.”
E ae mai oe e hele aku wau mawaena o kou aina: aole makou e kipa ma na mahinaai, aole hoi ma na pawaina: aole makou e inu i ka wai o ka punawai; e hele aku no makou ma ke alanui o ke alii, a hala aku la makou mai kou mau palena aku.
23 Ṣùgbọ́n Sihoni kò ní jẹ́ kí àwọn Israẹli kọjá ní ilẹ̀ wọn. Ó pe àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ jọ wọ́n sì wọ́de ogun lọ sí aginjù nítorí àwọn ọmọ Israẹli. Nígbà tí ó dé Jahasi, ó bá àwọn ọmọ Israẹli jà.
Aole no i ae mai o Sihona e hele aku ka Iseraela mawaena o kona mau palena: aku, hoakoakoa ae la o Sihona i kona poe kanaka a pau, a hele aku la iloko o ka waonahele e ku e i ka Iseraela: a hele mai la ia i Iahaza, a kaua mai la i ka Iseraela.
24 Àmọ́, Israẹli ṣẹ́gun, wọn fi ojú idà pa wọ́n, wọ́n sì gba ilẹ̀ láti ọwọ́ Arnoni lọ dé Jabbok, títí tí ó fi dé ilẹ̀ àwọn ará Ammoni, nítorí pé ààlà wọn jẹ́ olódi.
Luku aku la ka Iseraela la ia i ka pahikaua, a komo aku la i kona aina mai Arenona a Iaboka, a hiki i na mamo a Amona: no ka mea, ua paa ka palena o na mamo a Amona.
25 Israẹli sì gba gbogbo ìlú Amori wọ́n sì ń gbé ibẹ̀ pẹ̀lú Heṣboni, àti gbogbo ibùgbé ìlú tó yí i ká.
Lawe pio ae la ka Iseraela i keia mau kulanakauhale a pau: a noho iho la ka Iseraela ma na kulanakauhale a pau o ka Amora, i Hesebona, a i na kauhale a pau o ia wahi.
26 Heṣboni ni ìlú Sihoni ọba àwọn ará Amori, ẹni tí ó bá ọba Moabu ti tẹ́lẹ̀ jà tí ó sì gba gbogbo ilẹ̀ rẹ̀ ní ọwọ́ rẹ̀ títí dé Arnoni.
No ka mea, o Hesebona ke kulanakauhale o Sihona ke alii o ka Amora, nana i kaua aku mamua i ke alii o Moaba, a lawe ae la i kona aina a pau mai kona lima aku, a hiki i Arenona.
27 Ìdí nìyìí tí akọrin sọ wí pé, “Wá sí Heṣboni kí ẹ jẹ́ kí a tún un kọ́; jẹ́ kí ìlú Sihoni padà bọ̀ sípò.
No ia mea, i mai la na hakumele, E hele oukou iloko o Hesebona, e hana hou ia Ke kulanakauhale o Sihona e hookumuia:
28 “Iná jáde láti Heṣboni, ọ̀wọ́-iná láti Sihoni. Ó jó Ari àti Moabu run, àti ìlú àwọn olùgbé ibi gíga Arnoni.
No ka mea, mai Hesebona i hele aku ai ke ahi, He lapalapa ahi ma ke kulanakauhale o Sihona aku: Ua hoopau oia ia Ara o Moaba, A me na haku o na wahi kiekie o Arenona.
29 Ègbé ní fún ọ, ìwọ Moabu! Ẹ ti parun, ẹ̀yin ènìyàn Kemoṣi! Ó ti fi ọmọ rẹ̀ ọkùnrin sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ìsáǹsá àti ọmọ rẹ̀ obìnrin gẹ́gẹ́ bí ìgbèkùn fún Sihoni ọba àwọn Amori.
Auwe oe, e Moaba! ua make no oe! E na kanaka o Kemosa! Ua haawi aku ia i kana mau keikikane i pakele, A me kana mau kaikamahine, i poe pio No ke alii o ka Amora, no Sihona.
30 “Ṣùgbọ́n àti bì wọ́n ṣubú; a ti pa ìjẹgàba Heṣboni run, a pa wọ́n run títí dé Diboni. A sì ti bì wọ́n lulẹ̀ títí dé Nofa, tí ó sì fi dé Medeba.”
Ua pana pua aku makou ia lakou; Ua lukuia o Hesebona a hiki i Dibona, Ua hooneoneo makou a hiki aku i Nopa, A hiki hoi i Medeba.
31 Nígbà náà ni àwọn ọmọ Israẹli sì ń gbé ní ilẹ̀ Amori.
A noho iho la ka Iseraela ma ka aina o ka Amora.
32 Lẹ́yìn ìgbà tí Mose rán ayọ́lẹ̀wò lọ sí Jaseri, àwọn ọmọ Israẹli sì gba àwọn agbègbè tó yí wọn ká wọ́n sì lé àwọn Amori tó wà níbẹ̀ jáde.
A hoouna aku la o Mose e makaikai ia Iaazera, a komo lakou i na kulanakauhale o ia wahi, a hookuke aku la i ka Amora malaila.
33 Nígbà náà wọ́n pẹ̀yìndà wọ́n sì gòkè lọ sí Baṣani, Ogu ọba ti Baṣani àti gbogbo àwọn ọmọ-ogun tí ó wọ́de ogun jáde láti pàdé wọn ní ojú ogun ní Edrei.
Haliu ae la lakou, a pii aku la ma ke alanui o Basana: a hele mai la o Oga ke alii o Basana e ku e mai ia lakou, oia a me kona poe kanaka a pau, i ke kaua ma Ederei.
34 Olúwa sọ fún Mose pé, “Má ṣe bẹ̀rù rẹ̀, nítorí tí mó tí fi òun lé ọ lọ́wọ́, àti àwọn ọmọ-ogun rẹ̀, àti ilẹ̀ rẹ̀, kí ìwọ kí ó ṣe sí i gẹ́gẹ́ bí ìwọ ti ṣe sí Sihoni ọba Amori ẹni tí ó ń jẹ ọba ní Heṣboni.”
Olelo mai la o Iehova ia Mose, Mai makau oe ia ia; no ka mea, ua haawi aku no wau ia ia iloko o kou lima, me kona kanaka a pau, a me kona aina: a e hana aku oe ia ia me kau i hana aku ai ia Sihona ke alii o ka Amora i noho ma Hesebona.
35 Wọ́n sì pa á, pẹ̀lú àwọn ọmọ rẹ̀ àti gbogbo àwọn ọmọ-ogun rẹ̀, wọn kò fi ku ẹnìkan fún un láàyè. Wọ́n sì gba ìní ilẹ̀ rẹ̀.
A luku aku la lakou ia ia, me kana mau keikikane, a me kona poe kanaka a pau, aole i koe kekahi e ola ana nona: a komo aku la lakou i kona aina.

< Numbers 21 >