< Numbers 21 >

1 Nígbà tí ọba Aradi ará Kenaani, tí ń gbé ní gúúsù gbọ́ wí pé Israẹli ń bọ̀ wá ní ojú ọ̀nà Atarimu, ó bá Israẹli jà ó sì fi agbára mú díẹ̀ lára wọn.
Na rĩrĩ, rĩrĩa mũthamaki Mũkaanani wa Aradi, ũrĩa watũũraga Negevu, aiguire atĩ Isiraeli nĩokagĩra njĩra ya Atharimu, agĩthiĩ agĩtharĩkĩra andũ a Isiraeli, na agĩtaha amwe ao.
2 Nígbà náà ni Israẹli jẹ́ ẹ̀jẹ́ fún Olúwa pé, “Bí o bá lè fi àwọn ènìyàn yìí lé wa lọ́wọ́, gbogbo ìlú wọn ni a ó parun.”
Nao andũ Isiraeli makĩĩhĩta na mwĩhĩtwa ũyũ harĩ Jehova makiuga atĩrĩ: “Ũngĩneana andũ aya moko-inĩ maitũ-rĩ, nĩtũkananga matũũra mao marĩa manene biũ.”
3 Olúwa gbọ́ ẹ̀bẹ̀ àwọn ọmọ Israẹli, ó sì fi àwọn ará Kenaani lé wọn lọ́wọ́. Wọ́n pa wọ́n run pátápátá; torí náà ni a ṣe ń pe ibẹ̀ ní Horma.
Nake Jehova akĩigua ihooya rĩa andũ a Isiraeli na akĩneana andũ acio a Kaanani kũrĩ o. Nao makĩananga andũ acio biũ hamwe na matũũra mao; nĩ ũndũ ũcio handũ hau hagĩĩtwo Horoma.
4 Wọ́n rin ìrìnàjò láti òkè Hori lọ sí ọ̀nà tó lọ sí Òkun Pupa, láti kọjá yípo Edomu. Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn bínú ní ojú ọ̀nà;
Nao andũ a Isiraeli makĩnyiita rũgendo kuuma Kĩrĩma kĩa Horu magereire njĩra ya gũthiĩ Iria Itune, nĩguo mathiũrũrũke bũrũri wa Edomu. No andũ acio magĩthethũka marĩ njĩra-inĩ;
5 wọ́n sì sọ̀rọ̀ lòdì sí Ọlọ́run àti Mose, wọ́n wí pé, “Èéṣe tí ìwọ fi mú wa jáde láti Ejibiti kí a ba le wá kú sí aginjù yìí? Kò sí oúnjẹ! Kò sì sí omi! Àwa sì kórìíra oúnjẹ tí kò dára yìí!”
nao magĩũkĩrĩra Ngai o na Musa na mĩario makiuga atĩrĩ, “Mwatũrutire bũrũri wa Misiri tũũke tũkuĩre gũkũ werũ-inĩ nĩkĩ? Gũkũ gũtirĩ irio! Na gũtirĩ maaĩ! O na nĩtũthũire irio ici itarĩ kĩene!”
6 Nígbà náà ni Olúwa rán ejò olóró sí àárín wọn; wọ́n gé àwọn ènìyàn jẹ, ọ̀pọ̀ àwọn ọmọ Israẹli sì kú.
Nake Jehova akĩmatũmĩra nyoka ciarĩ na thumu; ikĩrũma andũ a Isiraeli, na aingĩ ao magĩkua.
7 Àwọn ènìyàn sì wá sí ọ̀dọ̀ Mose wọn wí pé, “A ti dá ẹ̀ṣẹ̀ nígbà tí asọ̀rọ̀-òdì sí Olúwa àti sí ìwọ pẹ̀lú. Gba àdúrà pé kí Olúwa mú ejò náà kúrò lọ́dọ̀ wa.” Nígbà náà ni Mose gbàdúrà fún àwọn ènìyàn.
Andũ acio magĩthiĩ kũrĩ Musa makĩmwĩra atĩrĩ, “Nĩtwehirie rĩrĩa twaaririe tũgĩũkĩrĩra Jehova hamwe nawe. Hooya nĩguo Jehova atwehererie nyoka ici.” Nĩ ũndũ ũcio Musa akĩhoera andũ acio.
8 Olúwa sọ fún Mose pé, “Rọ ejò, a ó sì gbé e kọ́ sókè lórí igi, ẹni tí ejò bá ti gé jẹ lè wò ó yóò sì yè.”
Nake Jehova akĩĩra Musa atĩrĩ, “Thondeka nyoka ũmĩcuurie gĩtugĩ igũrũ; mũndũ o wothe ũrĩĩrũmagwo-rĩ, aamĩrora nĩarĩtũũraga muoyo.”
9 Nígbà náà ni Mose sì rọ ejò onírin ó sì gbé e kọ́ sórí igi, bí ejò bá sì bu ẹnikẹ́ni jẹ bí ó bá ti wò ó yóò sì yè.
Nĩ ũndũ ũcio Musa agĩthondeka nyoka ya gĩcango, akĩmĩcuuria gĩtugĩ igũrũ. Na rĩrĩ, hĩndĩ ĩrĩa mũndũ o wothe aarũmwo nĩ nyoka na aarora nyoka ĩyo ya gĩcango, agatũũra muoyo.
10 Àwọn ọmọ Israẹli tẹ̀síwájú wọ́n sì péjọ sí Obotu.
Andũ a Isiraeli makiumagara, magĩthiĩ makĩamba hema ciao Obothu.
11 Wọ́n gbéra ní Obotu wọ́n sì pa ibùdó sí Iye-Abarimu, ní aginjù tí ó kọjú sí Moabu ní ìdojúkọ ìlà-oòrùn.
Ningĩ makiuma Obothu magĩthiĩ Iye-Abarimu, makĩamba hema ciao werũ-inĩ ũrĩa ũngʼethanĩire na Moabi mwena wa irathĩro.
12 Láti ibẹ̀ ni wọ́n ti gbéra wọ́n sì pa ibùdó ní àfonífojì Seredi.
Kuuma kũu magĩthiĩ na mbere, makĩamba hema ciao Kĩanda kĩa Zeredi.
13 Láti ibẹ̀ lọ, wọn ṣí, wọ́n sì dó sí ìhà kejì Arnoni, tí ó wà ní aginjù tí ó wà ní agbègbè ilẹ̀ àwọn ọmọ Amori. Arnoni jẹ́ ààlà fún ilẹ̀ Moabu, láàrín Moabu àti Amori.
Moimagara kuuma kũu makĩamba hema kũrigania na Rũũĩ rwa Arinoni, kũu werũ ũrĩa ũthiĩte nginya bũrũri wa Aamori; nĩgũkorwo Rũũĩ rwa Arinoni nĩruo rwarĩ mũhaka wa Moabi na Aamori.
14 Ìdí nìyìí tí ìwé ogun Olúwa se wí pé, “…Wahebu ní Sufa, Òkun Pupa àti ní odò Arnoni
Na nĩkĩo Ibuku rĩa Mbaara cia Jehova riugĩte atĩrĩ: “… Wahebu thĩinĩ wa Sufa, na mĩkuru, Arinoni
15 àti ní ìṣàn odò tí ó darí sí ibùjókòó Ari tí ó sì fi ara ti ìpínlẹ̀ Moabu.”
na igaragaro-inĩ cia mĩkuru ĩrĩa ithiĩte o nginya kũu Ari, na ĩgatwarana na mũhaka wa Moabi.”
16 Láti ibẹ̀ ni wọ́n ti bẹ̀rẹ̀ rìn dé Beeri, èyí ni kànga tí Olúwa sọ fún Mose, “Kó àwọn ènìyàn jọ èmi ó sì fún wọn ní omi.”
Kuuma kũu magĩthiĩ na mbere nginya kũu Biri, gĩthima-inĩ harĩa Jehova erire Musa atĩrĩ, “Cookereria andũ hamwe na nĩngũmahe maaĩ.”
17 Nígbà náà ni Israẹli kọ orin yìí pé, “Sun jáde, ìwọ kànga! Ẹ máa kọrin nípa rẹ̀,
Hĩndĩ ĩyo Isiraeli makĩina rwĩmbo rũrũ: “Therũka maaĩ, wee gĩthima gĩkĩ! Inyuĩ na inyuĩ inai ũhoro wakĩo,
18 nípa kànga tí àwọn ọmọ-aládé gbẹ́, nítorí àwọn ọlọ́lá ènìyàn ni ó gbẹ́ ẹ; tí àwọn ọlọ́lá àwọn ènìyàn sì fi ọ̀pá aládé àti ọ̀pá oyè wọn gbẹ́.” Nígbà náà wọ́n kúrò láti aginjù lọ sí Mattana,
ũhoro wa gĩthima kĩrĩa anene menjete, kĩrĩa gĩathikũririo nĩ andũ arĩa marĩ igweta, andũ arĩa marĩ igweta marĩ na njũgũma cia ũnene na mĩthĩĩgi yao.” Ningĩ makiuma werũ-inĩ magĩthiĩ Matana,
19 láti Mattana lọ sí Nahalieli, láti Nahalieli lọ sí Bamoti,
kuuma Matana magĩthiĩ Nahalieli, kuuma Nahalieli magĩthiĩ Bamothu,
20 àti láti Bamoti lọ sí àfonífojì ní Moabu níbi tí òkè Pisga, tí ó wà ní òkè ilé omi ti kọjú sí aginjù.
na kuuma Bamothu magĩthiĩ kĩanda kĩa Moabi, kũrĩa gacũmbĩrĩ ka Pisiga kangʼetheire werũ ũrĩa ũtarĩ kĩndũ.
21 Israẹli rán oníṣẹ́ láti sọ fún Sihoni ọba àwọn ará Amori wí pé,
Isiraeli nĩatũmire andũ kũrĩ Sihoni mũthamaki wa Aamori makamwĩre atĩrĩ:
22 “Jẹ́ kí a kọjá ní orílẹ̀-èdè rẹ. A kò ní kọjá sí inú oko pápá tàbí ọgbà àjàrà àbí mu omi láti inú kànga. A máa gba òpópónà náà ti ọba títí tí a ó fi la ilẹ̀ rẹ kọjá.”
“Twĩtĩkĩrie tũtuĩkanĩrie bũrũri wanyu. Tũtigũtoonya mĩgũnda yanyu ya irio, kana ya mĩthabibũ, kana tũnyue maaĩ kuuma gĩthima o na kĩmwe. Tũkũgerera njĩra ĩrĩa nene ya mũthamaki o nginya tũtuĩkanie bũrũri wanyu.”
23 Ṣùgbọ́n Sihoni kò ní jẹ́ kí àwọn Israẹli kọjá ní ilẹ̀ wọn. Ó pe àwọn ọmọ-ogun rẹ̀ jọ wọ́n sì wọ́de ogun lọ sí aginjù nítorí àwọn ọmọ Israẹli. Nígbà tí ó dé Jahasi, ó bá àwọn ọmọ Israẹli jà.
No Mũthamaki Sihoni akĩgiria andũ a Isiraeli mahĩtũkĩre bũrũri wake. We onganirie mbũtũ ciake ciothe cia ita, akiumagara agĩthiĩ werũ-inĩ agatharĩkĩre andũ a Isiraeli. Rĩrĩa aakinyire Jahazu-rĩ, akĩhũũrana na andũ a Isiraeli.
24 Àmọ́, Israẹli ṣẹ́gun, wọn fi ojú idà pa wọ́n, wọ́n sì gba ilẹ̀ láti ọwọ́ Arnoni lọ dé Jabbok, títí tí ó fi dé ilẹ̀ àwọn ará Ammoni, nítorí pé ààlà wọn jẹ́ olódi.
No andũ a Isiraeli makĩmooraga na hiũ cia njora na magĩtunya mũthamaki ũcio bũrũri wake kuuma Arinoni nginya Jaboku, no maakinyire o mũhaka-inĩ wa andũ a Amoni, tondũ warĩ mũirige na hinya mũno.
25 Israẹli sì gba gbogbo ìlú Amori wọ́n sì ń gbé ibẹ̀ pẹ̀lú Heṣboni, àti gbogbo ibùgbé ìlú tó yí i ká.
Isiraeli agĩtunya Aamori matũũra mothe mao marĩa manene na magĩtũũra kuo, o hamwe na Heshiboni na tũtũũra tuothe tũrĩa twarigainie nakuo.
26 Heṣboni ni ìlú Sihoni ọba àwọn ará Amori, ẹni tí ó bá ọba Moabu ti tẹ́lẹ̀ jà tí ó sì gba gbogbo ilẹ̀ rẹ̀ ní ọwọ́ rẹ̀ títí dé Arnoni.
Heshiboni nĩrĩo rĩarĩ itũũra inene rĩa Sihoni mũthamaki wa Aamori, ũrĩa warũĩte na mũthamaki wa Moabi ũrĩa waathanaga mbere ĩyo, na akamũtunya bũrũri wake wothe o nginya Arinoni.
27 Ìdí nìyìí tí akọrin sọ wí pé, “Wá sí Heṣboni kí ẹ jẹ́ kí a tún un kọ́; jẹ́ kí ìlú Sihoni padà bọ̀ sípò.
Kĩu nĩkĩo gĩtũmaga aini a marebeta moige atĩrĩ: “Ũkaai Heshiboni nĩgeetha rĩakwo rĩngĩ; itũũra inene rĩa Sihoni nĩrĩcokererio.
28 “Iná jáde láti Heṣboni, ọ̀wọ́-iná láti Sihoni. Ó jó Ari àti Moabu run, àti ìlú àwọn olùgbé ibi gíga Arnoni.
“Mwaki nĩwoimire kũu Heshiboni, rũrĩrĩmbĩ rũkiuma itũũra inene rĩa Sihoni. Ũkĩniina itũũra rĩa Ari Moabi, o atũũri a kũrĩa gũtũũgĩru kwa Arinoni.
29 Ègbé ní fún ọ, ìwọ Moabu! Ẹ ti parun, ẹ̀yin ènìyàn Kemoṣi! Ó ti fi ọmọ rẹ̀ ọkùnrin sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ìsáǹsá àti ọmọ rẹ̀ obìnrin gẹ́gẹ́ bí ìgbèkùn fún Sihoni ọba àwọn Amori.
Kaĩ ũrĩ na haaro, wee Moabi-ĩ! Inyuĩ andũ a Kemoshu! Kaĩ mũrĩ aanange-ĩ. Nĩarekereirie ariũ ake magatuĩka eethari, o na airĩtu ake akĩmarekereria matahwo nĩ Sihoni mũthamaki wa Aamori.
30 “Ṣùgbọ́n àti bì wọ́n ṣubú; a ti pa ìjẹgàba Heṣboni run, a pa wọ́n run títí dé Diboni. A sì ti bì wọ́n lulẹ̀ títí dé Nofa, tí ó sì fi dé Medeba.”
“No ithuĩ nĩtũmangʼaũranĩtie; Heshiboni kwanangĩtwo guothe nginya o Diboni. Tũmamomorete tũgakinya Nofa, itũũra rĩrĩa rĩkuhanĩrĩirie na Medeba.”
31 Nígbà náà ni àwọn ọmọ Israẹli sì ń gbé ní ilẹ̀ Amori.
Nĩ ũndũ ũcio andũ a Isiraeli magĩtũũra bũrũri ũcio wa Aamori.
32 Lẹ́yìn ìgbà tí Mose rán ayọ́lẹ̀wò lọ sí Jaseri, àwọn ọmọ Israẹli sì gba àwọn agbègbè tó yí wọn ká wọ́n sì lé àwọn Amori tó wà níbẹ̀ jáde.
Thuutha wa Musa gũtũma andũ magathigaane Jazeri, andũ a Isiraeli magĩtunyana tũtũũra tũrĩa twarigiicĩirie itũũra rĩu, na makĩingata Aamori arĩa maarĩ kuo.
33 Nígbà náà wọ́n pẹ̀yìndà wọ́n sì gòkè lọ sí Baṣani, Ogu ọba ti Baṣani àti gbogbo àwọn ọmọ-ogun tí ó wọ́de ogun jáde láti pàdé wọn ní ojú ogun ní Edrei.
Ningĩ makĩgarũrũka, makĩambata na njĩra marorete Bashani, nake Ogu mũthamaki wa Bashani na mbũtũ ciake ciothe cia ita makiumagara makahũũrane na Isiraeli kũu Edirei.
34 Olúwa sọ fún Mose pé, “Má ṣe bẹ̀rù rẹ̀, nítorí tí mó tí fi òun lé ọ lọ́wọ́, àti àwọn ọmọ-ogun rẹ̀, àti ilẹ̀ rẹ̀, kí ìwọ kí ó ṣe sí i gẹ́gẹ́ bí ìwọ ti ṣe sí Sihoni ọba Amori ẹni tí ó ń jẹ ọba ní Heṣboni.”
Nake Jehova akĩĩra Musa atĩrĩ, “Ndũkamwĩtigĩre, nĩ ũndũ nĩndĩmũneanĩte moko-inĩ maku, hamwe na mbũtũ ciake ciothe cia ita, o na bũrũri wake. Mwĩke o ũrĩa wekire Sihoni mũthamaki wa Aamori, ũrĩa waathanaga Heshiboni.”
35 Wọ́n sì pa á, pẹ̀lú àwọn ọmọ rẹ̀ àti gbogbo àwọn ọmọ-ogun rẹ̀, wọn kò fi ku ẹnìkan fún un láàyè. Wọ́n sì gba ìní ilẹ̀ rẹ̀.
Nĩ ũndũ ũcio makĩũraga Mũthamaki Ogu hamwe na ariũ ake, o na mbũtũ ciake ciothe cia ita, mategũtigia mũndũ o na ũmwe muoyo. Nao andũ a Isiraeli makĩĩgwatĩra bũrũri wake.

< Numbers 21 >