< Numbers 20 >

1 Ní oṣù kìn-ín-ní, gbogbo àgbájọ ọmọ Israẹli gúnlẹ̀ sí pápá Sini, wọ́n sì dúró ní Kadeṣi. Níbẹ̀ ni Miriamu kú, wọ́n sì sin ín.
Na ka tae nga tama a Iharaira, ara te whakaminenga katoa, ki te koraha o Hini i te marama tuatahi: a ka noho te iwi ki Karehe; na ka mate a Miriama ki reira, a tanumia ana ki reira.
2 Omi kò sí fún ìjọ ènìyàn, àwọn ènìyàn sì kó ara wọn jọ pọ̀ sí Mose àti Aaroni,
A kahore he wai mo te whakaminenga: a ka huihui ki te ngangare ki a Mohi raua ko Arona.
3 wọ́n bá Mose jà wọ́n sì wí pé, “Ìbá kúkú sàn kí a kú nígbà tí àwọn arákùnrin ti kú níwájú Olúwa!
Na ka ngangau te iwi ki a Mohi, ka korero, ka mea, Aue, me i mate matou i te matenga o o matou tuakana i te aroaro o Ihowa!
4 Kí ni ó dé tí o sì kó gbogbo ìjọ ènìyàn Olúwa wá sí aginjù yìí, kí àwa àti àwọn ẹran ọ̀sìn wa bá à kú síbí?
He aha hoki i kawea mai ai e korua te whakaminenga a Ihowa ki tenei koraha, kia mate tahi matou me a matou kararehe ki konei?
5 Kí ni ó dé tí o fi mú wa gòkè kúrò ní Ejibiti wá sí ibi búburú yìí? Ibi tí kò ní oúnjẹ tàbí igi ọ̀pọ̀tọ́, èso àjàrà tàbí pomegiranate. Bẹ́ẹ̀ ni kò sí omi tí a ó mu níhìn-ín!”
He aha hoki matou i meinga ai e korua kia haere mai i Ihipa, kia kawea mai matou ki tenei wahi kino? ehara nei i te wahi purapura, i te wahi piki, waina, pamekaranete; kahore ano hoki he wai hei inu.
6 Mose àti Aaroni kúrò ní ibi àpéjọ, wọ́n sì lọ dojúbolẹ̀ sí ẹnu-ọ̀nà àgọ́ ìpàdé, ògo Olúwa sì farahàn wọ́n.
Na ka haere a Mohi raua ko Arona i te aroaro o te whakaminenga ki te whatitoka o te tapenakara o te whakaminenga, a ka kupapa iho o raua mata: na ko te putanga mai o te kororia o Ihowa ki a raua.
7 Olúwa sọ fún Mose pé,
A ka korero a Ihowa ki a Mohi, ka mea,
8 “Mú ọ̀pá, náà kí o sì pe ìjọ àwọn ènìyàn jọ, ìwọ àti Aaroni arákùnrin rẹ, kí ẹ sọ̀rọ̀ sí àpáta náà ní ojú wọn, yóò sì tú omi rẹ̀ jáde, ìwọ ó sì fún ìjọ àti ẹran wọn mu.”
Maua atu te tokotoko, huihuia mai ano te whakaminenga e korua ko tou tuakana, ko Arona, ka korero ai korua ki te kamaka i mua i o ratou kanohi, kia tukua mai tona wai; a ka whakaputaina mai e koe he wai mo ratou i roto i te kamaka: a ka meinga e koe te whakaminenga me a ratou kararehe kia inu.
9 Báyìí ni Mose mú ọ̀pá láti iwájú Olúwa wá, gẹ́gẹ́ bí ó ti pàṣẹ fún un.
Na ka maua e Mohi te tokotoko i te aroaro o Ihowa, pera ana ia me tana i whakahau ai.
10 Òun àti Aaroni pe àwọn ènìyàn jọ sí ojú kan níwájú àpáta, Mose sì sọ fún wọn, “Ẹ gbọ́, ẹ̀yin ọlọ̀tẹ̀, àwa kì yóò lè mú omi jáde láti inú àpáta yìí wá bí?”
I huihuia hoki te whakaminenga e Mohi raua ko Arona ki mua o te kamaka, a ka mea ia ki a ratou, Whakarongo mai, e te hunga tutu; me whakaputa mai ranei e maua he wai mo koutou i roto i tenei kamaka?
11 Nígbà náà ni Mose gbé ọwọ́ rẹ̀ sókè ó sì fi ọ̀pá ọwọ́ rẹ̀ lu àpáta lẹ́ẹ̀méjì. Omi sì tú jáde, gbogbo ìjọ ènìyàn àti àwọn ẹran ọ̀sìn wọn sì mu.
Na ka ara te ringa o Mohi, a e rua ana patunga i te kamaka ki tana tokotoko; ko te tino putanga mai o te wai, tona nui, a inu ana te iwi me a ratou kararehe.
12 Ṣùgbọ́n Olúwa sọ fún Mose àti Aaroni pé, “Nítorí pé ẹ̀yin kò gbà mí gbọ́ tó láti bu ọlá fún mi níwájú àwọn ọmọ Israẹli, ìwọ kò ní kó àwọn ìjọ ènìyàn yìí dé ilẹ̀ tí mo fún wọn.”
Na ka mea a Ihowa ki a Mohi raua ko Arona, Kahore nei korua i whakapono ki ahau, kia whakatapu i ahau i te tirohanga a nga tama a Iharaira, mo reira e kore korua e kawe i tenei whakaminenga ki te whenua e hoatu nei e ahau ki a ratou.
13 Èyí ni omi ti Meriba, níbi tí àwọn ọmọ Israẹli ti bá Olúwa jà àti ibi tí O ti fi ara rẹ̀ hàn bí ẹni mímọ́ láàrín wọn.
Ko te wai tena o Meripa; i ngangau hoki nga tama a Iharaira ki a Ihowa ki reira, a meinga ana ratou hei whakatapu mona.
14 Mose sì ránṣẹ́ láti Kadeṣi sí ọba Edomu, wí pé, “Èyí ni nǹkan tí arákùnrin rẹ Israẹli sọ, ìwọ ti mọ̀ nípa gbogbo ìnira, tí ó wá sí orí wa.
Na ka unga tangata a Mohi i Karehe ki te kingi o Eroma, Ko te kupu tenei a tou teina, a Iharaira, E mohio ana koe ki nga he katoa i pono mai ki a matou;
15 Àwọn baba ńlá wa sọ̀kalẹ̀ wá sí Ejibiti, a sì gbé ibẹ̀ fún ọ̀pọ̀ ọdún. Àwọn ará Ejibiti ni wá lára àti àwọn baba wa,
Ki te hekenga o o matou matua ki Ihipa, ki to matou nohoanga hoki i Ihipa, a maha noa nga ra; a ka tukino nga Ihipiana i a matou ko o matou matua:
16 ṣùgbọ́n nígbà tí a sọkún sí Olúwa, ó gbọ́ ẹkún wa, ó sì rán angẹli kan sí wa, ó sì mú wa jáde láti Ejibiti. “Báyìí àwa wà ní Kadeṣi, ìlú tí ó wà ní ẹ̀gbẹ́ ilẹ̀ rẹ.
A, i ta matou karangatanga atu ki a Ihowa, na ka rongo ia ki to matou reo, a unga ana e ia he anahera hei whakaputa mai i a matou i Ihipa: na, kei Karehe tenei matou, kei te pa whakamutunga o tou rohe:
17 Jọ̀wọ́ jẹ́ kí a gba orílẹ̀-èdè rẹ kọjá, àwa kì yóò gba inú oko tàbí ọgbà àjàrà rẹ kọjá, tàbí mu omi láti inú kànga. A ó ma kọjá ní òpópónà ọba, àwa kì yóò yà sí ọ̀tún tàbí sí òsì títí àwa yóò fi kọjá ní ilẹ̀ rẹ.”
Tena, tukua atu matou ma tou whenua: e kore matou e haere na nga mara, na nga mara waina ranei, e kore ano matou e inu i te wai o nga puna: ka haere matou i te huanui o te kingi, e kore matou e peka ki matau, ki maui, kia pahemo ra ano i a matou ou rohe.
18 Ṣùgbọ́n Edomu dáhùn pé, “Ẹ̀yin kò le gba ibí kọjá; bí ẹ bá dán an wò, a ó dìde ogun sí yín, a ó sì bá yín jà pẹ̀lú idà.”
Na ka mea a Eroma ki a ia, E kore koe e tika na toku wahi, kei haere ahau me te hoari ki te tu i a koe.
19 Àwọn ọmọ Israẹli dáhùn pé, “A ó gba ọ̀nà tóóró, bí àwa tàbí ẹran ọ̀sìn wa bá sì mú lára omi rẹ, a ó san owó rẹ̀. A kàn fẹ́ rìn kọjá lórí ilẹ̀ rẹ ni kò sí nǹkan kan mìíràn tí a fẹ́ ṣe.”
Na ka mea nga tama a Iharaira ki a ia, Ka haere matou na te huanui: a ki te inu ahau me aku kahui i tou wai, me utu e ahau: heoi rawa taku e mea ai, ko te haere kau o oku waewae na kona.
20 Wọ́n tún dáhùn wí pé, “Ẹ kò lè kọjá.” Nígbà náà ni Edomu jáde wá láti kọjú ìjà sí wọn pẹ̀lú ọ̀pọ̀ àti alágbára ọmọ-ogun.
Na ka mea ia, E kore koe e haere ra konei. A ka puta a Eroma me te ope nui, me te ringa kaha, ki te tu i a ia.
21 Nígbà tí Edomu sì kọ̀ jálẹ̀ láti jẹ́ kí wọn kọjá ní ilẹ̀ wọn, Israẹli yípadà kúrò lọ́dọ̀ wọn.
Heoi kihai a Eroma i pai ki te tuku i a Iharaira kia haere na tona rohe: na peka ke ana a Iharaira i a ia.
22 Gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli sì jáde láti Kadeṣi wọ́n sì wá sí orí òkè Hori.
Na ka turia atu e ratou i Karehe: a ka tae nga tama a Iharaira, ara te whakaminenga katoa ki Maunga Horo.
23 Ní orí òkè Hori, ní ẹ̀gbẹ́ ààlà Edomu Olúwa sọ fún Mose àti Aaroni pé,
Na ka korero a Ihowa ki a Mohi raua ko Arona i Maunga Horo, i te rohe o te whenua o Eroma, ka mea,
24 “Aaroni yóò kú. Kò ní wọ ilẹ̀ tí mo fi fún àwọn ọmọ Israẹli, nítorí ẹ̀yin méjèèjì ṣe àìgbọ́ràn sí òfin mi níbi omi Meriba.
Ka kohia atu a Arona ki tona iwi; e kore hoki ia e tae ki te whenua ka hoatu nei e ahau ki nga tama a Iharaira, mo korua i whakatoi ki taku kupu i te wai o Meripa.
25 Mú Aaroni àti ọmọ rẹ̀ Eleasari lọ sí orí òkè Hori.
Tangohia a Arona raua ko Ereatara, ko tana tama, kawea hoki raua ki runga ki Maunga Horo:
26 Bọ́ aṣọ Aaroni kí o sì gbe wọ ọmọ rẹ̀ Eleasari, nítorí pé Aaroni yóò kú síbẹ̀.”
Unuhia hoki nga kakahu o Arona, ka whakakakahu ai ki tana tama, ki a Ereatara: a ka kohia atu a Arona ki tona iwi, ka mate hoki ki reira.
27 Mose sì ṣe gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti pàṣẹ, wọ́n lọ sí orí òkè Hori ní ojú gbogbo ìjọ ènìyàn.
Na ka pera a Mohi me ta Ihowa i whakahau ai, a haere ana ratou ki runga ki Maunga Horo i te tirohanga a te whakaminenga katoa.
28 Mose bọ́ aṣọ Aaroni ó sì gbe wọ ọmọ rẹ̀ Eleasari, Aaroni sì kú sí orí òkè. Nígbà náà Mose àti Eleasari sọ̀kalẹ̀ láti orí òkè,
Na ka unuhia e Mohi nga kakahu o Arona, a whakakakahuria ana e ia ki tana tama, ki a Ereatara; a ka mate a Arona ki reira, ki te tihi o te maunga: a ka heke iho a Mohi raua ko Ereatara i runga i te maunga.
29 nígbà tí gbogbo ìjọ ènìyàn sì gbọ́ pé Aaroni ti kú, gbogbo ilé Israẹli ṣe ìdárò rẹ̀ fún ọgbọ̀n ọjọ́.
A, no te kitenga o te whakaminenga katoa kua mate a Arona, e toru tekau nga ra i tangihia ai a Arona e ratou, e te whare katoa o Iharaira.

< Numbers 20 >