< Numbers 20 >
1 Ní oṣù kìn-ín-ní, gbogbo àgbájọ ọmọ Israẹli gúnlẹ̀ sí pápá Sini, wọ́n sì dúró ní Kadeṣi. Níbẹ̀ ni Miriamu kú, wọ́n sì sin ín.
Og Israels Børn, den ganske Menighed, kom i den Ørk Zin, i den første Maaned, og Folket blev i Kades; og Maria døde der og blev begraven der.
2 Omi kò sí fún ìjọ ènìyàn, àwọn ènìyàn sì kó ara wọn jọ pọ̀ sí Mose àti Aaroni,
Og Menigheden havde intet Vand; da forsamledes de mod Mose og mod Aron.
3 wọ́n bá Mose jà wọ́n sì wí pé, “Ìbá kúkú sàn kí a kú nígbà tí àwọn arákùnrin ti kú níwájú Olúwa!
Og Folket kivedes med Mose, og de sagde: Gid vi dog havde opgivet Aanden, dengang vore Brødre opgave Aanden for Herrens Ansigt.
4 Kí ni ó dé tí o sì kó gbogbo ìjọ ènìyàn Olúwa wá sí aginjù yìí, kí àwa àti àwọn ẹran ọ̀sìn wa bá à kú síbí?
Og hvorfor førte I Herrens Menighed ind i denne Ørk, at vi skulle dø der, vi og vore Dyr?
5 Kí ni ó dé tí o fi mú wa gòkè kúrò ní Ejibiti wá sí ibi búburú yìí? Ibi tí kò ní oúnjẹ tàbí igi ọ̀pọ̀tọ́, èso àjàrà tàbí pomegiranate. Bẹ́ẹ̀ ni kò sí omi tí a ó mu níhìn-ín!”
Og hvorfor førte I os op af Ægypten for at bringe os til dette slemme Sted, som ikke er et Sted til Sæd og Figen og Vin og Granatæble, og hvor der ikke er Vand at drikke?
6 Mose àti Aaroni kúrò ní ibi àpéjọ, wọ́n sì lọ dojúbolẹ̀ sí ẹnu-ọ̀nà àgọ́ ìpàdé, ògo Olúwa sì farahàn wọ́n.
Og Mose og Aron kom fra Menighedens Ansigt til Forsamlingens Pauluns Dør og faldt ned paa deres Ansigter; og Herrens Herlighed viste sig for dem.
Og Herren talede til Mose og sagde:
8 “Mú ọ̀pá, náà kí o sì pe ìjọ àwọn ènìyàn jọ, ìwọ àti Aaroni arákùnrin rẹ, kí ẹ sọ̀rọ̀ sí àpáta náà ní ojú wọn, yóò sì tú omi rẹ̀ jáde, ìwọ ó sì fún ìjọ àti ẹran wọn mu.”
Tag Staven, og saml Menigheden, du og Aron, din Broder, og I skulle tale til Klippen for deres Øjne, saa skal den give Vand af sig; og du skal lade Vand af Klippen komme ud til dem og give Menigheden og deres Dyr at drikke.
9 Báyìí ni Mose mú ọ̀pá láti iwájú Olúwa wá, gẹ́gẹ́ bí ó ti pàṣẹ fún un.
Da tog Mose Staven bort fra Herrens Ansigt, som han havde befalet ham.
10 Òun àti Aaroni pe àwọn ènìyàn jọ sí ojú kan níwájú àpáta, Mose sì sọ fún wọn, “Ẹ gbọ́, ẹ̀yin ọlọ̀tẹ̀, àwa kì yóò lè mú omi jáde láti inú àpáta yìí wá bí?”
Og Mose og Aron samlede Menigheden lige for Klippen; og han sagde til dem: Hører dog, I genstridige! monne vi kunne lade Vand komme ud til eder af denne Klippe?
11 Nígbà náà ni Mose gbé ọwọ́ rẹ̀ sókè ó sì fi ọ̀pá ọwọ́ rẹ̀ lu àpáta lẹ́ẹ̀méjì. Omi sì tú jáde, gbogbo ìjọ ènìyàn àti àwọn ẹran ọ̀sìn wọn sì mu.
Og Mose opløftede sin Haand og slog Klippen med sin Stav to Gange; da udgik meget Vand, saa at Menigheden drak og deres Dyr.
12 Ṣùgbọ́n Olúwa sọ fún Mose àti Aaroni pé, “Nítorí pé ẹ̀yin kò gbà mí gbọ́ tó láti bu ọlá fún mi níwájú àwọn ọmọ Israẹli, ìwọ kò ní kó àwọn ìjọ ènìyàn yìí dé ilẹ̀ tí mo fún wọn.”
Og Herren sagde til Mose og til Aron: Fordi I ikke troede paa mig, til at helliggøre mig for Israels Børns Øjne, derfor skulle I ikke føre denne Menighed ind i det Land, som jeg har givet dem.
13 Èyí ni omi ti Meriba, níbi tí àwọn ọmọ Israẹli ti bá Olúwa jà àti ibi tí O ti fi ara rẹ̀ hàn bí ẹni mímọ́ láàrín wọn.
Dette er Kivevandet, hvor Israels Børn kivedes med Herren; og han helliggjorde sig paa dem.
14 Mose sì ránṣẹ́ láti Kadeṣi sí ọba Edomu, wí pé, “Èyí ni nǹkan tí arákùnrin rẹ Israẹli sọ, ìwọ ti mọ̀ nípa gbogbo ìnira, tí ó wá sí orí wa.
Og Mose sendte Bud fra Kades til Edoms Konge, saalunde: Saa siger din Broder Israel: Du ved al den Møje, som os er vederfaren,
15 Àwọn baba ńlá wa sọ̀kalẹ̀ wá sí Ejibiti, a sì gbé ibẹ̀ fún ọ̀pọ̀ ọdún. Àwọn ará Ejibiti ni wá lára àti àwọn baba wa,
at vore Fædre droge ned til Ægypten, og vi boede lang Tid i Ægypten, og Ægypterne handlede ilde med os og med vore Fædre.
16 ṣùgbọ́n nígbà tí a sọkún sí Olúwa, ó gbọ́ ẹkún wa, ó sì rán angẹli kan sí wa, ó sì mú wa jáde láti Ejibiti. “Báyìí àwa wà ní Kadeṣi, ìlú tí ó wà ní ẹ̀gbẹ́ ilẹ̀ rẹ.
Og vi raabte til Herren, og han hørte vor Røst og sendte en Engel og udførte os af Ægypten, og se, vi ere i Kades, Staden ved det yderste af dit Landemærke.
17 Jọ̀wọ́ jẹ́ kí a gba orílẹ̀-èdè rẹ kọjá, àwa kì yóò gba inú oko tàbí ọgbà àjàrà rẹ kọjá, tàbí mu omi láti inú kànga. A ó ma kọjá ní òpópónà ọba, àwa kì yóò yà sí ọ̀tún tàbí sí òsì títí àwa yóò fi kọjá ní ilẹ̀ rẹ.”
Kære, lad os gaa igennem dit Land, vi ville hverken gaa igennem Ager eller Vingaard og ej drikke Vand af nogen Brønd, vi ville gaa ad Kongevejen, vi ville hverken bøje til den højre eller til den venstre Side, indtil vi ere komne igennem dit Landemærke.
18 Ṣùgbọ́n Edomu dáhùn pé, “Ẹ̀yin kò le gba ibí kọjá; bí ẹ bá dán an wò, a ó dìde ogun sí yín, a ó sì bá yín jà pẹ̀lú idà.”
Og Edom sagde til ham: Du maa ikke gaa igennem mit Land, at jeg ikke skal drage ud mod dig med Sværd.
19 Àwọn ọmọ Israẹli dáhùn pé, “A ó gba ọ̀nà tóóró, bí àwa tàbí ẹran ọ̀sìn wa bá sì mú lára omi rẹ, a ó san owó rẹ̀. A kàn fẹ́ rìn kọjá lórí ilẹ̀ rẹ ni kò sí nǹkan kan mìíràn tí a fẹ́ ṣe.”
Og Israels Børn sagde til ham: Vi ville gaa op ad den alfare Vej, og dersom vi drikke af Vandet hos dig, jeg og mit Kvæg, da vil jeg give Betaling derfor; jeg vil slet intet gøre uden at gaa igennem til Fods.
20 Wọ́n tún dáhùn wí pé, “Ẹ kò lè kọjá.” Nígbà náà ni Edomu jáde wá láti kọjú ìjà sí wọn pẹ̀lú ọ̀pọ̀ àti alágbára ọmọ-ogun.
Men han sagde: Du maa ikke gaa igennem; og Edom drog ud imod ham med et svart Folk og en stærk Haand.
21 Nígbà tí Edomu sì kọ̀ jálẹ̀ láti jẹ́ kí wọn kọjá ní ilẹ̀ wọn, Israẹli yípadà kúrò lọ́dọ̀ wọn.
Saa vægrede Edom sig ved at tillade Israel at gaa igennem sit Landemærke; og Israel bøjede af Vejen for ham.
22 Gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli sì jáde láti Kadeṣi wọ́n sì wá sí orí òkè Hori.
Og de rejste fra Kades; og Israels Børn, al Menigheden kom til det Bjerg Hor.
23 Ní orí òkè Hori, ní ẹ̀gbẹ́ ààlà Edomu Olúwa sọ fún Mose àti Aaroni pé,
Og Herren talede til Mose og til Aron ved det Bjerg Hor, ved Edoms Landemærke, og sagde:
24 “Aaroni yóò kú. Kò ní wọ ilẹ̀ tí mo fi fún àwọn ọmọ Israẹli, nítorí ẹ̀yin méjèèjì ṣe àìgbọ́ràn sí òfin mi níbi omi Meriba.
Aron skal samles til sit Folk, thi han skal ikke komme ind i det Land, som jeg har givet Israels Børn, fordi I vare genstridige mod min Mund ved Meribas Vand.
25 Mú Aaroni àti ọmọ rẹ̀ Eleasari lọ sí orí òkè Hori.
Tag Aron og Eleasar, hans Søn, Og før dem op paa det Bjerg Hor.
26 Bọ́ aṣọ Aaroni kí o sì gbe wọ ọmọ rẹ̀ Eleasari, nítorí pé Aaroni yóò kú síbẹ̀.”
Og før Aron af sine Klæder, og før Eleasar, hans Søn, i dem; og Aron skal samles til sit Folk og dø der.
27 Mose sì ṣe gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti pàṣẹ, wọ́n lọ sí orí òkè Hori ní ojú gbogbo ìjọ ènìyàn.
Da gjorde Mose, som Herren havde befalet; og de gik op paa det Bjerg Hor for den ganske Menigheds Øjne.
28 Mose bọ́ aṣọ Aaroni ó sì gbe wọ ọmọ rẹ̀ Eleasari, Aaroni sì kú sí orí òkè. Nígbà náà Mose àti Eleasari sọ̀kalẹ̀ láti orí òkè,
Og Mose førte Aron af sine Klæder og førte Eleasar, hans Søn, i dem; saa døde Aron der oven paa Bjerget; men Mose og Eleasar gik ned ad Bjerget.
29 nígbà tí gbogbo ìjọ ènìyàn sì gbọ́ pé Aaroni ti kú, gbogbo ilé Israẹli ṣe ìdárò rẹ̀ fún ọgbọ̀n ọjọ́.
Og der al Menigheden saa, at Aron havde opgivet Aanden, da begræd de Aron i tredive Dage, hele Israels Hus.