< Numbers 18 >

1 Olúwa sọ fún Aaroni pé, “Ìwọ, àti àwọn ọmọ rẹ àti ìdílé baba rẹ ni yóò ru gbogbo ẹ̀ṣẹ̀ tí wọ́n ti dá fún ilé tí a yà sí mímọ́ fún Ọlọ́run, àti ìwọ àti àwọn ọmọ rẹ nìkan ni yóò máa ru ẹ̀ṣẹ̀ iṣẹ́ àlùfáà yín.
Nake Jehova akĩĩra Harũni atĩrĩ, “Wee, na ariũ aku, na andũ a nyũmba ya thoguo, nĩ inyuĩ mũrĩcookagĩrĩrwo nĩ mahĩtia marĩa mangĩĩkwo makoniĩ handũ-harĩa-haamũre, na wee na ariũ aku inyuĩ nĩ inyuĩ mũrĩcookagĩrĩrwo nĩ mahĩtia marĩa mangĩĩkwo makoniĩ wĩra wa ũthĩnjĩri-Ngai.
2 Kí o sì mú àwọn ènìyàn rẹ ará Lefi láti ẹ̀yà ìran rẹ láti dàpọ̀ mọ́ ìwọ láti ràn ọ́ lọ́wọ́ nígbà tí ìwọ àti àwọn ọmọ rẹ ọkùnrin bá ń ṣe iṣẹ́ ìránṣẹ́ níwájú Àgọ́ ẹ̀rí.
Rehe Alawii a mbarĩ yanyu, a mũhĩrĩga wa maithe manyu, nĩguo manyiitane na inyuĩ na mamũteithagĩrĩrie rĩrĩa wee na ariũ aku mũgũtungata mbere ya Hema-ya-Ũira.
3 Àwọn ni ó yẹ láti dúró fún ọ àti láti ṣe gbogbo iṣẹ́ ti Àgọ́, ṣùgbọ́n wọn kò gbọdọ̀ súnmọ́ ibi tí a ti ṣe lọ́ṣọ̀ọ́ tí a sì yà sí mímọ́ tàbí ibi pẹpẹ, tàbí gbogbo wọn àti ìwọ ló máa kú.
Acio nĩwe marĩathĩkagĩra na marutage wĩra wothe wa Hema ĩyo, no matikanakuhĩrĩrie indo cia handũ hau haamũre kana kĩgongona, kana wee hamwe nao mũkue.
4 Ó yẹ kí wọ́n darapọ̀ mọ́ ọ láti jẹ ìyà iṣẹ́ fún àìtọ́jú ibi ti àgọ́ ìpàdé àti gbogbo iṣẹ́ tí ó wà ní ibi àgọ́, àti wí pé kò sí àlejò tí ó le wá sí ẹ̀gbẹ́ ibi tí o wà.
Marĩrutithanagia wĩra na inyuĩ na mamenyagĩrĩre Hema-ya-Gũtũnganwo, marutage wĩra wothe wa Hema ĩyo na gũtikagĩe na mũndũ ũngĩ o wothe ũngĩkuhĩrĩria harĩa mũrĩ.
5 “Kí o sì mójútó iṣẹ́ ibi mímọ́ àti iṣẹ́ ibi pẹpẹ, kí ìbínú má ba wá sí orí àwọn ọmọ Israẹli mọ́.
“Nĩ wĩra wanyu kũmenyerera handũ hau haamũre o na kĩgongona, nĩguo mangʼũrĩ ma Jehova matikanakinyĩre andũ a Isiraeli rĩngĩ.
6 Èmi fúnra mi ti yan àwọn arákùnrin rẹ tí í ṣe ọmọ Lefi kún àwọn ọmọ Israẹli yòókù, wọn jẹ́ ẹ̀bùn fún ọ, èyí ni a fún Olúwa láti ṣe iṣẹ́ tí ó wà ní àgọ́ ìpàdé.
Niĩ mwene nĩthuurĩte Alawii athiritũ anyu kuuma thĩinĩ wa andũ a Isiraeli matuĩke kĩheo kĩanyu, maamũrĩirwo Jehova nĩguo marutage wĩra wa Hema-ya-Gũtũnganwo.
7 Ṣùgbọ́n ìwọ àti àwọn ọmọ rẹ ni yóò mójútó iṣẹ́ àlùfáà yín fún gbogbo ohun tó bá jẹ mọ́ ibi pẹpẹ àti ti ẹ̀yin aṣọ títa, ẹ ó sì máa ṣiṣẹ́ ibi pẹpẹ àti nínú aṣọ tí a ta. Mo fún ọ ní iṣẹ́ àlùfáà gẹ́gẹ́ bí ẹ̀bùn. Ṣùgbọ́n àlejò tí ó bá súnmọ́ tòsí ibi ìyàsímímọ́ fún Ọlọ́run ni a ó pa.”
No rĩrĩ, no wee na ariũ aku mũrĩĩtungataga ta athĩnjĩri-Ngai maũndũ-inĩ mothe ma kĩgongona, na mũtungatage o na mwena ũcio ũngĩ wa gĩtambaya kĩu gĩa kũhakania. Niĩ nĩndamũhe ũtungata wa ũthĩnjĩri-Ngai ta kĩheo. Mũndũ ũngĩ o wothe ũngĩkuhĩrĩria handũ hau haamũre no nginya ooragwo.”
8 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Aaroni pé, “Èmi fúnra mi ti fi ọ́ ṣọ́ ìdí gbogbo ẹbọ tí a bá mú wá fún gbogbo ọrẹ mímọ́ tí àwọn ọmọ Israẹli bá fún mi, mo fún ìwọ àti àwọn ọmọ rẹ gẹ́gẹ́ bí ìpín rẹ tí yóò máa ṣe.
Ningĩ Jehova akĩĩra Harũni atĩrĩ, “Niĩ mwene nĩngũtuĩte mũmenyereri wa maruta marĩa ndehagĩrwo; maruta mothe maamũre marĩa andũ a Isiraeli marĩndutagĩra nĩ ndakũhe wee na ariũ aku matuĩke gĩcunjĩ gĩaku na rũgai rwaku rwa mahinda mothe.
9 Ìwọ ni kí o ni ìpín ọrẹ mímọ́ jùlọ tí a mú kúrò ní ibi iná, nínú gbogbo ọrẹ tí wọ́n mú wá gẹ́gẹ́ bí ẹbọ mímọ́ jùlọ, yálà ẹbọ ohun jíjẹ, ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀ tàbí ẹbọ ẹ̀bi, ìpín wọ̀nyí jẹ́ ti ìwọ àti àwọn ọmọ rẹ.
Wee ũrĩheagwo gĩcunjĩ kĩa maruta marĩa maamũre mũno marĩa matarĩ ma gũcinwo na mwaki. Kuuma kũrĩ iheo ciothe iria andũ a Isiraeli marĩndutagĩra irĩ maruta maamũre mũno, marĩ ma mũtu, kana ma kũhoroherio mehia, kana maruta ma mahĩtia, gĩcunjĩ kĩu nĩ gĩaku na ciana ciaku.
10 Ẹ jẹ ẹ́ ní ibi mímọ́ jùlọ, gbogbo ọkùnrin ni ó gbọdọ̀ jẹ ẹ́. Ó gbọdọ̀ kà á sí mímọ́.
Rĩĩaga gĩcunjĩ kĩu ta kĩndũ kĩamũre mũno; mũndũ mũrũme o wothe wa nyũmba yaku nĩagakĩrĩĩaga. Wee no nginya ũtuage atĩ gĩcunjĩ kĩu nĩ kĩamũre.
11 “Èyí tún jẹ́ tìrẹ pẹ̀lú: ohunkóhun tí a bá yà sọ́tọ̀ lára ẹ̀bùn ọrẹ fífì àwọn ọmọ Israẹli. Mó fún ìwọ àti àwọn ọmọ rẹ ọkùnrin àti ọmọ rẹ obìnrin gẹ́gẹ́ bí ìpín tí yóò máa ṣe déédé nínú ìdílé rẹ, tí o bá wà ní mímọ́ ni o le jẹ ẹ́.
“O na ningĩ ici no ciaku: kĩrĩa gĩothe kĩamũrĩtwo kuuma iheo ciothe cia gũthũngũthio cia andũ a Isiraeli. Icio nĩndakũhe wee, na ariũ aku, na airĩtu aku, ituĩke rũgai rwaku rwa hĩndĩ ciothe. Mũndũ o wothe wa nyũmba yaku ũtarĩ na thaahu no acirĩe.
12 “Mo fún ọ ní gbogbo òróró tí ó dára jùlọ àti gbogbo ọtí tuntun dáradára jùlọ àti ọkà tí wọ́n mú wá fún Olúwa ní àkọ́so ohun ọ̀gbìn wọn tí wọ́n kórè.
“Nĩndakũhe maguta mothe marĩa mega mũno ma mũtamaiyũ na ndibei yothe ĩrĩa njega mũno ya mũhihano, na ngano ĩrĩa maheaga Jehova ĩrĩ maciaro ma mbere ma magetha mao.
13 Gbogbo àkọ́so nǹkan ilẹ̀ wọ́n tí wọn mú wá fún Olúwa yóò jẹ́ tìrẹ. Ẹnikẹ́ni nínú ìdílé rẹ, àwọn tí ó jẹ́ mímọ́ nínú ìdílé rẹ lè jẹ ẹ́.
Maciaro mothe ma bũrũri ma mbere marĩa marĩrehagĩra Jehova marĩtuĩkaga maku. Mũndũ o wothe wa nyũmba yaku ũtarĩ thaahu no amarĩe.
14 “Gbogbo nǹkan tí a yà sọ́tọ̀ fún Olúwa ní Israẹli jẹ́ tìrẹ.
“Kĩndũ gĩothe kĩrĩ Isiraeli kĩrĩa kĩamũrĩirwo Jehova nĩ gĩaku.
15 Gbogbo àkọ́bí nínú gbogbo ohun alààyè tí wọ́n mú wá fún Olúwa, ìbá à jẹ́ ti ènìyàn tàbí ti ẹranko jẹ́ tìrẹ ṣùgbọ́n o gbọdọ̀ ra gbogbo àkọ́bí ọmọkùnrin padà àti àkọ́bí àwọn ẹranko aláìmọ́.
Marigithathi mothe, marĩ ma andũ kana ma nyamũ, marĩa marĩrutagĩrwo Jehova nĩ maku. No rĩrĩ, no nginya ũkũũrithagie irigithathi rĩothe rĩa kahĩĩ, na ũkũũrithagie irigithathi rĩa njamba rĩa nyamũ iria irĩ thaahu.
16 Nígbà tí wọ́n bá pé oṣù kan, o gbọdọ̀ rà wọ́n padà ní iye owó ìràpadà tí í ṣe ṣékélì márùn-ún fàdákà, gẹ́gẹ́ bí iye ṣékélì ibi mímọ́ tí ó wọn ìwọ̀n ogún gera.
Marigithathi macio marĩ ma mweri ũmwe, no nginya ũkaamakũũrithia na thogora wa gũkũũrana ũrĩa ũtuĩtwo wa cekeri ithano cia betha, kũringana na cekeri ya handũ-harĩa-haamũre, ĩrĩa ĩrĩ na ũritũ wa geera mĩrongo ĩĩrĩ.
17 “Ṣùgbọ́n o kò gbọdọ̀ ra àwọn àkọ́bí ọmọ màlúù, àgùntàn tàbí ewúrẹ́; wọ́n jẹ́ mímọ́. Wọ́n ẹ̀jẹ̀ wọn sórí pẹpẹ kí o sì sun ọ̀rá rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọrẹ àfinásun, ẹbọ òórùn dídùn sí Olúwa.
“No mũtikanakũũrithie marigithathi ma ndegwa, kana ma ngʼondu, kana ma mbũri; icio nĩ nyamũre. Thakame yacio nĩĩminjaminjagwo kĩgongona-inĩ igũrũ, na maguta ma cio macinwo na mwaki nĩguo matuĩke igongona rĩ na mũtararĩko wa gũkenia Jehova.
18 Ẹran wọn gbọdọ̀ jẹ́ tìrẹ, gẹ́gẹ́ bí igẹ̀ ọrẹ ẹbọ fífì àti itan ọ̀tún ṣe jẹ́ tìrẹ.
Nyama ciacio nĩ ciaku, o ta ũrĩa gĩthũri kĩa igongona rĩa gũthũngũthio na kĩero kĩa ũrĩo irĩ ciaku.
19 Ohunkóhun tí a bá ti yà sọ́tọ̀ nínú ọrẹ àwọn ọmọ Israẹli tí wọ́n mú wá fún Olúwa ni mo fún ìwọ àti àwọn ọmọ rẹ ọkùnrin àti ọmọ rẹ obìnrin gẹ́gẹ́ bí ìpín rẹ tí yóò máa ṣe déédé. Ó jẹ́ májẹ̀mú iyọ̀ láéláé níwájú Olúwa fún ìwọ àti ọmọ rẹ.”
Kĩrĩa gĩothe kĩamũragĩrwo Jehova nĩ andũ a Isiraeli kĩrĩ kĩamũre nĩndakũhe wee mwene, na ariũ aku, na airĩtu aku, kĩrĩ rũgai rwaku rwa hĩndĩ ciothe. Nĩkĩo kĩrĩkanĩro gĩa tene na tene gĩa cumbĩ mbere ya Jehova kũrĩ wee na njiaro ciaku.”
20 Olúwa sọ fún Aaroni pé, “O kò ní ní ogún nínú ilẹ̀ wọn bẹ́ẹ̀ ni ìwọ kò ní ní ìpín láàrín wọn; Èmi ni ìpín àti ogún rẹ láàrín àwọn ọmọ Israẹli.
Ningĩ Jehova akĩĩra Harũni atĩrĩ, “Wee ndũgakorwo na igai bũrũri-inĩ wao, kana ũgĩe na rũgai thĩinĩ wao; niĩ nĩ niĩ rũgai rwaku o na igai rĩaku thĩinĩ wa andũ a Isiraeli.
21 “Mó ti fún àwọn ọmọ Lefi ní gbogbo ìdámẹ́wàá ní Israẹli gẹ́gẹ́ bí ogún fún iṣẹ́ tí wọ́n ṣe, nígbà tí wọ́n ń ṣiṣẹ́ níbi àgọ́ ìpàdé.
“Nĩndahe Alawii icunjĩ ciothe cia ikũmi thĩinĩ wa Isiraeli, arĩ rĩo igai rĩao nĩ ũndũ wa wĩra ũrĩa marutaga rĩrĩa megũtungata Hema-inĩ-ya-Gũtũnganwo.
22 Láti ìsinsin yìí àwọn ọmọ Israẹli, kò gbọdọ̀ súnmọ́ àgọ́ ìpàdé, bí wọ́n bá ṣe bẹ́ẹ̀, wọn yóò jẹ ìyà ẹ̀ṣẹ̀ wọn, wọn á sì kú.
Kuuma rĩu andũ a Isiraeli matigakuhagĩrĩrie Hema-ya-Gũtũnganwo, kana macookererwo nĩ mehia mao, nao makue.
23 Àwọn ọmọ Lefi ní ó gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́ tí ó wà nínú àgọ́ ìpàdé, wọn yóò sì jìyà ẹ̀ṣẹ̀ wọn bí wọ́n bá kúrò láti ṣe é. Èyí ni ìlànà láéláé fún àwọn ìran tí ó ń bọ̀. Wọn kò nígbà ogún kankan láàrín àwọn ọmọ Israẹli.
Alawii nĩo marĩrutaga wĩra Hema-inĩ-ya-Gũtũnganwo na nĩo marĩcookagĩrĩrwo nĩ mahĩtia marĩa meekĩirwo hau. Ũyũ nĩ watho wa gũtũũrio nĩ njiaro iria igooka. Matikagĩa na igai thĩinĩ wa andũ a Isiraeli.
24 Kàkà bẹ́ẹ̀, mo fún àwọn ọmọ Lefi gẹ́gẹ́ bí ogún wọn, ìdákan nínú ìdámẹ́wàá tí àwọn ọmọ Israẹli pèsè gẹ́gẹ́ bí ọrẹ sí Olúwa. Èyí ni mo wí nípa wọn. Wọn kò ní gba ogún kankan láàrín àwọn ọmọ Israẹli.”
Handũ ha ũguo-rĩ, ngũhe Alawii icunjĩ cia ikũmi iria andũ a Isiraeli marehaga irĩ maruta kũrĩ Jehova ituĩke igai rĩao. Nĩkĩo ndoigire igũrũ rĩao atĩrĩ: ‘Matikagĩa na igai thĩinĩ wa andũ a Isiraeli.’”
25 Olúwa sọ fún Mose pé,
Jehova akĩĩra Musa atĩrĩ,
26 “Sọ fún àwọn ọmọ Lefi kí o sì wí fún wọn pé: ‘Nígbà tí ìdámẹ́wàá bá ń wọlé láti ọ̀dọ̀ àwọn ọmọ Israẹli gẹ́gẹ́ bí ogún rẹ. O gbọdọ̀ mú ìdámẹ́wàá lára rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọrẹ Olúwa.
“Arĩria Alawii, ũmeere atĩrĩ: ‘Rĩrĩa mwamũkĩra icunjĩ cia ikũmi kuuma kũrĩ andũ a Isiraeli iria ndĩmũheete arĩ cio igai rĩanyu-rĩ, no nginya mũrehage gĩcunjĩ gĩa ikũmi gĩa gĩcunjĩ kĩu, kĩrĩ iruta kũrĩ Jehova.
27 A ó ka ọrẹ rẹ gẹ́gẹ́ bí ọkà irúgbìn láti ilẹ̀ ìpakà tàbí wáìnì láti fún wa.
Maruta manyu marĩtuĩkaga ta ngano ĩrĩa ĩrutĩtwo kĩhuhĩro-inĩ, kana ndibei ĩrĩa ĩrutĩtwo kĩhihĩro-inĩ.
28 Báyìí ni ìwọ gan an náà yóò mú ọrẹ wa fún Olúwa láti ara ìdámẹ́wàá tí ìwọ gbà láti ọ̀dọ̀ àwọn ọmọ Israẹli. Láti ara ìdámẹ́wàá ó gbọdọ̀ mú ọrẹ Olúwa fún Aaroni àlùfáà.
Ũguo nĩguo o na inyuĩ mũrĩrutagĩra Jehova iruta kuuma kũrĩ icunjĩ cia ikũmi iria mũrĩamũkagĩra ciumĩte kũrĩ andũ a Isiraeli. Kuuma kũrĩ icunjĩ icio cia ikũmi, no nginya mũnengagĩre Harũni mũthĩnjĩri-Ngai gĩcunjĩ kĩa Jehova.
29 Ìwọ gbọdọ̀ mú wá gẹ́gẹ́ bí ìpín Olúwa èyí tí ó dára jùlọ àti tí ó jẹ́ mímọ́ jùlọ lára gbogbo nǹkan tí wọ́n mú wá fún ọ.’
No nginya mũkarutagĩra Jehova gĩcunjĩ kĩrĩa kĩega mũno na kĩrĩa kĩamũre mũno kĩa indo ciothe iria mũheetwo.’
30 “Sọ fún àwọn ọmọ pé, ‘Nígbà tí ẹ̀yin bá mú ìpín tí ó dára jù wá, a ó kà á sí fún àwọn ọmọ Lefi gẹ́gẹ́ bí ìkórè láti ilẹ̀ ìpakà tàbí ìfúntí yín.
“Ĩra Alawii atĩrĩ, ‘Rĩrĩa mwaruta gĩcunjĩ kĩrĩa kĩega mũno-rĩ, kĩrĩtuĩkaga ta iruta rĩanyu riumĩte kĩhuhĩro-inĩ kĩa ngano kana kĩhihĩro-inĩ kĩa ndibei.
31 Ìwọ àti àwọn ìdílé rẹ̀ le jẹ èyí tí ó kù ní ibikíbi gbogbo. Nítorí pé ó jẹ́ ọrẹ fún iṣẹ́ rẹ níbi àgọ́ ìpàdé.
Inyuĩ na andũ a nyũmba cianyu no mũrĩĩre icio ingĩ handũ o hothe, nĩgũkorwo ũcio nĩ mũcaara wanyu nĩ ũndũ wa wĩra wanyu kũu Hema-inĩ-ya-Gũtũnganwo.
32 Nípa ṣíṣe ìgbékalẹ̀ ìpín tí ó dára jùlọ o kò ní jẹ̀bi lórí ọ̀rọ̀ yìí, ìwọ kò sì ní ba ọrẹ mímọ́ àwọn ọmọ Israẹli jẹ́, ìwọ kì yóò sì kú.’”
Nĩ ũndũ wa kũruta gĩcunjĩ kĩu kĩega mũno gĩacio, mũtigaatuĩrwo mahĩtia nĩ ũndũ wa ũndũ ũyũ; na ningĩ mũtigathaahia maruta marĩa maamũre ma andũ a Isiraeli, na nĩ ũndũ ũcio mũtigaakua.’”

< Numbers 18 >