< Numbers 16 >

1 Kora ọmọ Isari, ọmọ Kohati, ọmọ Lefi àwọn ọmọ Reubeni: Datani àti Abiramu, àwọn ọmọ Eliabu, àti Oni ọmọ Peleti mú ènìyàn mọ́ra.
A KUKA iho la o Kora, ke keiki a Izekara, ke keiki a Kohata, ke keiki a Levi, a o Datana a me Abirama na keiki a Eliaba, a me Ona ke keiki a Peleta, na keiki a Reubena:
2 Wọ́n sì dìde sí Mose, pẹ̀lú àádọ́ta lé nígba ọkùnrin nínú àwọn ọmọ Israẹli, ìjòyè nínú ìjọ, àwọn olórúkọ nínú àjọ, àwọn ọkùnrin olókìkí.
A ku iluna lakou me kekahi poe mamo a Iseraela imua o Mose, he elua haneri a me kanalima na luna o na kanaka, he poe pookela ma ke anaina kanaka, na kanaka kaulana:
3 Wọ́n kó ara wọn jọ láti tako Mose àti Aaroni, wọ́n sọ fún wọn pé, “Ẹ ti kọjá ààyè yín, ó tó gẹ́ẹ́! Mímọ́ ni gbogbo ènìyàn, kò sí ẹni tí kò mọ́ láàrín wọn, Olúwa sì wà pẹ̀lú wọn, nítorí kí wá ni ẹ̀yin ṣe gbé ara yín ga ju ìjọ ènìyàn Olúwa lọ?”
Houluulu ae la lakou e ku e ia Mose a ia Aarona, i mai la ia laua, He nui loa ka olua, no ka mea, ua laa ke anaina kanaka a pau loa, a o Iehova kekahi iwaena o lakou: no ke aha la hoi olua e hookiekie ae nei ia olua iho maluna o ke anaina kanaka o Iehova?
4 Nígbà tí Mose gbọ́ èyí, ó dojúbolẹ̀,
A lohe ae la o Mose, moe iho la ia ilalo ke alo.
5 Ó sì sọ fún Kora àti gbogbo ẹgbẹ́ rẹ̀ pé, “Ní ọ̀la ni Olúwa yóò fi ẹni tí í ṣe tirẹ̀ àti ẹni tó mọ́ hàn, yóò sì mú kí ẹni náà súnmọ́ òun. Ẹni tí ó bá yàn ni yóò mú kí ó súnmọ́ òun.
Olelo aku la ia ia Kora, a me kona poe a pau, i aku la, A kakahiaka ae, e hoike mai o Iehova i ka mea nona, a me ka mea laa; a e hookokoke aku ai ia ia io na la; o ka mea ana e koho ai, oia kana e hookokoke aku ai io na la.
6 Kí Kora àti gbogbo ẹgbẹ́ rẹ̀ ṣe èyí, ẹ mú àwo tùràrí.
O keia ka oukou e hana'i; E lawe oukou i na ipukuniala, o Kora a me kona mau hoa a pau;
7 Kí ẹ sì fi iná àti tùràrí sínú rẹ̀ lọ́la níwájú Olúwa, yóò sì ṣe, ọkùnrin tí Olúwa bá yàn òun ni. Ẹ̀yin ọmọ Lefi, ẹ ti kọjá ààyè yín!”
E hahao i ke ahi maloko, e hahao hoi i ka mea ala maloko imua o Iehova i ka la apopo: a o ka mea a Iehova e wae mai ai, oia ka mea laa: he nui loa ka oukou, e na mamo a Levi.
8 Mose sì tún sọ fún Kora pé, “Ẹ gbọ́ báyìí o, ẹ̀yin ọmọ Lefi!
I aku la o Mose ia Kora ma, Ke noi aku nei au ia oukou, e hoolohe mai oukou, e na mamo a Levi.
9 Kò ha tọ́ fún yín pé Ọlọ́run Israẹli ti yà yín sọ́tọ̀ lára ìjọ Israẹli yòókù, tó sì mú yín súnmọ́ ara rẹ̀ láti ṣiṣẹ́ nínú àgọ́ Olúwa àti láti dúró ṣiṣẹ́ ìsìn níwájú àwọn ènìyàn?
He mea uuku anei ia oukou, i hookaawale ae ke Akua o ka Iseraela ia oukou mai ke anaina kanaka o ka Iseraela mai, e hookokoke oka ia oukou io na la, e hana i ka hana ma ka halelewa o Iehova, a e ku imua o ko anaina kanaka, e lawelawe na lakou?
10 Ó ti mú àwọn ènìyàn yín tó jẹ́ ọmọ Lefi súnmọ́ ara rẹ̀, ṣùgbọ́n báyìí ẹ tún ń wá ọnà láti ṣiṣẹ́ àlùfáà.
A ua hookokoke mai no oia ia oe a me kou poe hoahanau na mamo a Levi me oe: a ke imi nei anei hoi oukou i ka oihana kahuna?
11 Olúwa ni ìwọ àti gbogbo ẹlẹgbẹ́ rẹ takò. Ta a ni Aaroni jẹ́ tí ẹ̀yin ó fi kùn sí i?”
No ia mea, ua akoakoa ae nei oe me ou poe a pau e ku e ia Iehova; heaha hoi o Aarona i ohumu aku ai oukou ia ia?
12 Mose sì ránṣẹ́ sí Datani àti Abiramu àwọn ọmọ Eliabu. Ṣùgbọ́n wọ́n wí pé, “Àwa kò ní í wá!
Hoouna aku la o Mose, e kii ia Datana laua o Abirama na keiki a Eliaba: i mai la hoi laua, Aole maua e hele aku.
13 Kò ha tó gẹ́ẹ́ pé o ti mú wa jáde láti ilẹ̀ tí ó ń sàn fún wàrà àti oyin láti pa wá sínú aginjù yìí? O tún wá fẹ́ sọ ara rẹ di olúwa lé wa lórí bí?
He mea liilii anei kou lawe ana mai ia makou mailoko mai o ka aina e kahe ana o ka waiu a me ka meli, e pepehi ia makou ma ka waonahele, ke hiki ole ia oe e hoolilo ia oe iho i alii maluna o makou?
14 Síbẹ̀síbẹ̀ ìwọ kò sì tí ì mú wa dé ilẹ̀ tí ó ń sàn fún wàrà àti oyin, bẹ́ẹ̀ ni o kò sì pín ilẹ̀ ìní àti ọgbà àjàrà. Ìwọ ha fẹ́ sọ wá di ẹrú bí? Rárá o, àwa kì yóò gòkè wá!”
Aole no hoi oe i lawe aku ia makou i ka aina e kahe ana o ka waiu a me ka melt, me ka haawi mai no makou i na kula a me na malawaina. K poalo anei oe i na maka o keia poe kanaka? Aole no maua e hele aku.
15 Nígbà náà ni Mose bínú gidigidi, ó sì sọ fún Olúwa pé, “Má ṣe gba ọrẹ wọn, èmi kò gba kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ lọ́wọ́ wọn, bẹ́ẹ̀ ni n kò sì pa ẹnikẹ́ni nínú wọn lára!”
Huhu loa iho la o Mose, a i aku la ia Iehova, Mai maliu mai oe i ka lakou mohai: aole au i lawe no'u i kekahi hoki o lakou, aole hoi au i hana eha aku i kekahi o lakou.
16 Mose sọ fún Kora pé, “Ìwọ àti ọmọ lẹ́yìn rẹ gbọdọ̀ fi ara hàn níwájú Olúwa lọ́la—gbogbo yín, ìwọ, àwọn ọmọ lẹ́yìn rẹ àti Aaroni.
I aku la o Mose ia Kora, Apopo, e hele oe me ou poe a pau imua o Iehova, o oe, o lakou a me Aarona.
17 Kí ẹnìkọ̀ọ̀kan yín mú àwo tùràrí, kí ó sì fi tùràrí sínú rẹ̀, kí gbogbo rẹ̀ jẹ́ àádọ́ta lé nígba àwo tùràrí kí ẹ sì ko wá síwájú Olúwa. Ìwọ àti Aaroni yóò mú àwo tùràrí wá pẹ̀lú.”
E lawe hoi keia kanaka kela kanaka i kona ipukuniala, e hahao i ka mea ala maloko, a e lawe mai na kanaka o oukou a pau i ko lakou ipukuniala imua o Iehova, i elua haneri a me kanalima na ipukuniala; o oe hoi, a o Aarona, o kela mea keia mea me kona ipukuniala.
18 Nígbà náà ni oníkálùkù wọn mú àwo tùràrí, wọ́n fi iná àti tùràrí sí i nínú, wọ́n sì dúró sí ẹnu-ọ̀nà àgọ́ ìpàdé, àwọn pẹ̀lú Mose àti Aaroni.
A lawe ae la kela kanaka keia kanaka i kona ipukuniala, hahao iho la i ke ahi maloko, a kau i ka mea ala maluna, a ku ae la ma ka puka o ka halelewa o ke anaina me Mose a me Aarona.
19 Nígbà tí Kora kó gbogbo àwọn ẹlẹgbẹ́ rẹ̀ jọ sí ẹnu-ọ̀nà àgọ́ ìpàdé, ògo Olúwa sì farahan gbogbo ìjọ ènìyàn.
Houluulu ae la o Kora i ke anaina kanaka a pau ma ka puka o ka halelewa e ku e ia laua: a ikea ae la ka nani o Iehova e ke anaina kanaka a pau.
20 Olúwa sì sọ fún Mose àti Aaroni pé,
Olelo mai la o Iehova ia Mose a me Aarona, i mai la,
21 “Ẹ ya ara yín sọ́tọ̀ kúrò láàrín ìjọ wọ̀nyí, kí ń ba à le pa wọ́n run lẹ́ẹ̀kan náà.”
K hookaawale ae olua ia olua iho mai keia anaina kanaka aku, i hoopau koke ai au ia lakou.
22 Ṣùgbọ́n Mose àti Aaroni dojúbolẹ̀ wọ́n sì kígbe sókè pé, “Ọlọ́run, Ọlọ́run ẹ̀mí gbogbo ènìyàn, Ìwọ ó wa bínú sí gbogbo ìjọ ènìyàn nígbà tó jẹ́ pé ẹnìkan ló ṣẹ̀?”
Moe iho la laua, ilalo ke alo, i aku la, E ke Akua, ke Akua o na uhane o na kanaka a pau, a i hewa ke kanaka hookahi, e inaina mai no anei oe i ke anaina kanaka a pau?
23 Olúwa tún sọ fún Mose pé,
Olelo mai la o Iehova ia Mose, i mai la,
24 “Sọ fún ìjọ ènìyàn pé, ‘Kí wọ́n jìnnà sí àgọ́ Kora, Datani àti Abiramu.’”
E olelo aku oe i ke anaina kanaka, e i aku, E hookaawale ae ia oukou iho mai kela aoao a mai keia aoao aku o ka halelewa o Kora, o Datana a o Abirama.
25 Mose sì dìde lọ bá Datani àti Abiramu àwọn àgbàgbà Israẹli sì tẹ̀lé.
Ku ae la o Mose, a hele aku la io Datana a me Abirama la, a hahai aku la na lunakahiko o ka Iseraela ia ia.
26 Ó sì kìlọ̀ fún ìjọ ènìyàn pé, “Ẹ kúrò ní àgọ́ àwọn ènìyàn búburú yìí! Ẹ má ṣe fọwọ́ kan ohun kan tí í ṣe tiwọn kí ẹ má ba à parun nítorí ẹ̀ṣẹ̀ wọn.”
Olelo aku la ia i ke anaina kanaka, i aku la, E hookaawale aku ia oukou iho mai na halelewa aku o keia mau kanaka hewa, mai hoopa aku i kekahi mea o lakou nei, o make auanei oukou iloko o ko lakou hewa a pau.
27 Àwọn ènìyàn sì sún kúrò ní àgọ́ Kora, Datani àti Abiramu. Datani àti Abiramu jáde, àwọn ìyàwó wọn àti àwọn ọmọ wọn sì dúró sí ẹnu-ọ̀nà àgọ́ wọn.
Alaila, haalele aku la lakou i ka halelewa o Kora a me Datana a me Abirama mai keia aoao a mai kela aoao aku: a puka mai la o Datana laua o Abirama iwaho, a ku mai la ma ka puka o ko laua mau halelewa, me ka laua mau wahine, me na keikikane a laua, a me ka laua mau keiki uuku.
28 Nígbà náà ni Mose wí pé, “Báyìí ni ẹ ó ṣe mọ̀ pé Olúwa ló rán mi láti ṣe gbogbo iṣẹ́ wọ̀nyí àti pé kì í ṣe ìfẹ́ inú mi ni àwọn ohun tí mò ń ṣe.
I aku la o Mose, Ma keia mea e ike ai oukou, owau no ka Iehova i hoouna mai nei e hana i keia mau hana a pau; no ka mea, aole ia na kuu manao iho.
29 Bí àwọn ènìyàn yìí bá kú bí gbogbo ènìyàn ti ń kú, bí ìrírí wọn kò bá sì yàtọ̀ sí ti àwọn ènìyàn yòókù, a jẹ́ pé kì í ṣe Olúwa ló rán mi.
Ina paha e make keia poe kanaka e like me ka make ana o na kanaka a pau, a i ikeia'ku lakou e like me ka ikeia'na o na kanaka a pau, alaila aole na Iehova wau i hoouna mai.
30 Ṣùgbọ́n bí Olúwa bá ṣe ohun tuntun, tí ilẹ̀ sì la ẹnu, tó gbé wọn mì, àwọn pẹ̀lú gbogbo ohun tí wọ́n ní, tí wọ́n sì wọ inú ibojì wọn lọ láààyè, nígbà náà ni ẹ̀yin ó mọ̀ pé àwọn ènìyàn yìí ti kẹ́gàn Olúwa.” (Sheol h7585)
Aka ina e hana mai o Iehova i ka mea hou, a hamama ae ka honua i kona waha, a moni iho ia lakou nei, me na mea a pau ia lakou, a iho koke lakou ilalo i ka lua; alaila e ike pono oukou, ua hoonaukiuki aku keia mau kanaka ia Iehova. (Sheol h7585)
31 Bí ó sì ṣe parí ọ̀rọ̀ wọ̀nyí, ilẹ̀ pín sí méjì nísàlẹ̀ wọn,
A i ka manawa i hooki ai oia i ka olelo ana i keia mau mea a pau, naha'e la ka honua malalo iho o lakou:
32 ilẹ̀ sì lanu ó sì gbé wọn mì pẹ̀lú gbogbo ará ilé wọn àti àwọn ènìyàn Kora àti gbogbo ohun tí wọ́n ní.
A hamama ae la ka honua i kona waha, ale iho la ia lakou, me ko lakou mau hale, a me na kanaka a pau i pili aku ia Kora, a me ko lakou waiwai a pau.
33 Gbogbo wọn sì sọ̀kalẹ̀ sínú ibojì wọn láààyè pẹ̀lú ohun gbogbo tí wọ́n ní, ilẹ̀ sì padé mọ́ wọn, wọ́n sì ṣègbé kúrò láàrín ìjọ ènìyàn. (Sheol h7585)
O lakou a me ko lakou mea a pau, iho ola iho la iloko o ka lua, a paa hou mai la ka honua maluna o lakou; a make iho la lakou maiwaena aku o ke anaina kanaka. (Sheol h7585)
34 Gbogbo ènìyàn Israẹli tí ó yí wọn ká sì sálọ tí àwọn yòókù gbọ́ igbe wọn, wọ́n wí pé, “Ilẹ̀ yóò gbé àwa náà mì pẹ̀lú.”
A holo aku la ka Iseraela a pau ma kela aoao a ma keia aoao o lakou, i ko lakou hooho ana; i ae la lakou, O ale auanei ka honua ia kakou.
35 Iná sì jáde láti ọ̀dọ̀ Olúwa ó sì run àádọ́ta lé nígba ọkùnrin tí wọ́n mú tùràrí wá.
Puka mai la ke ahi mai o Iehova mai, a ai mai la i na kanaka elua haneri me kanalima, o ka poe i mohai aku i ka mea ala.
36 Olúwa sọ fún Mose pé,
Olelo mai la o Iehova ia Mose, i mai la,
37 “Sọ fún Eleasari ọmọ Aaroni tí í ṣe àlùfáà, pé kí ó mú àwọn àwo tùràrí jáde kúrò nínú iná nítorí pé wọ́n jẹ́ mímọ́, kí ó sì tan iná náà káàkiri sí ibi tó jìnnà.
E olelo aku ia Eleazara ke keiki a Aarona, ke kahuna, e lawe ia i na ipukuniala mailoko ae o ke ahi, a e hoolei aku i ke ahi ma o; no ka mea, ua laa ia mau mea.
38 Èyí ni àwo tùràrí àwọn tí ó kú nítorí ẹ̀ṣẹ̀ wọn. Kí ẹ gún àwo tùràrí yìí, kí ẹ sì fi ṣe ìbòrí fún pẹpẹ, wọ́n jẹ́ mímọ́ nítorí pé wọ́n ti mú wọn wá síwájú Olúwa. Kí wọ́n jẹ́ àmì fún àwọn ọmọ Israẹli.”
O na ipukuniala o keia poe i hana hewa aku i ko lakou mau uhane, e hana lakou ia mau mea i mau pa palahalaha, i uhi no ke kuahu: no ka mea, na kaumaha iho la lakou ia mau mea imua o Iehova, nolaila ua laa; a e lilo lakou i hoailona no na mamo a Iseraela.
39 Eleasari tí í ṣe àlùfáà sì kó gbogbo àwo tùràrí tí àwọn tí ó jóná mú wa, ó gún wọn pọ̀, ó fi ṣe ìbòrí fún pẹpẹ,
A lawe ae la o Eleazara ke kahuna i na ipukuniala keleawe, i na mea a ka poe pau i ke ahi i mohai aku ai; a ua hanaia ua mau mea la i mau pa palahalaha no ke kuahu:
40 gẹ́gẹ́ bí Olúwa ṣe sọ láti ẹnu Mose. Èyí yóò jẹ́ ohun ìrántí fún àwọn ọmọ Israẹli pé, àlejò yàtọ̀ sí irú-ọmọ Aaroni kò gbọdọ̀ jó tùràrí níwájú Olúwa, ẹni tí ó bá ṣe bẹ́ẹ̀, yóò dàbí Kora àti àwọn ẹgbẹ́ rẹ̀.
I mea hoomanao no na mamo a Iseraela, i ole ai ke kanaka e, ka mea aole na ka hua a Aarona, e hele mai a kokoke e kuni i ka mea ala imua o Iehova, i like ole ai ia me Kora, a me kona poe; me ka Iehova i olelo mai ai ia ia ma ka lima o Mose.
41 Ní ọjọ́ kejì gbogbo ìjọ àwọn ọmọ Israẹli kùn sí Mose àti Aaroni pé, “Ẹ ti pa àwọn ènìyàn Olúwa.”
Ia la ae, ohumu ae la ke anaina kanaka a pau o na mamo a Iseraela, ia Mose a ia Aarona, i mai la, Ua make ia olua ko Iehova poe kanaka.
42 Ṣùgbọ́n nígbà tí gbogbo ìjọ ènìyàn péjọ lòdì sí Mose àti Aaroni, níwájú àgọ́ ìpàdé, lójijì ni ìkùùkuu bolẹ̀, ògo Olúwa sì fi ara hàn.
Aia akoakoa ae ke anaina kanaka e ku e ia Mose a ia Aarona, nana ae la lakou i ka halelewa o ke anaina, aia hoi, uhi mai la ke ao, a ikea mai la hoi ka nani o Iehova.
43 Nígbà náà ni Mose àti Aaroni lọ síwájú àgọ́ ìpàdé,
Hele aku la o Mose laua o Aarona imua o ka halelewa o ke anaina.
44 Olúwa sì sọ fún Mose pé,
Olelo mai la o Iehova ia Mose, i mai la,
45 “Yàgò kúrò láàrín ìjọ ènìyàn yìí, kí ń ba le run wọ́n ní ìṣẹ́jú kan.” Wọ́n sì dojúbolẹ̀.
E hookaawale ae ia olua iho maiwaena ae o keia anaina kanaka, i hoopau koke ai au ia lakou. A moe iho la laua ilalo ke alo.
46 Mose sì sọ fún Aaroni pé, “Mú àwo tùràrí, kí o fi iná sí i lórí pẹpẹ, fi tùràrí sínú rẹ̀, kí o sì tètè mu lọ sí àárín ìjọ ènìyàn láti ṣe ètùtù fún wọn nítorí pé ìbínú Olúwa ti jáde, àjàkálẹ̀-ààrùn sì ti bẹ̀rẹ̀.”
I aku la o Mose ia Aarona, E lawe oe i wahi ipukuniala, a e hahao i ke ahi maloko mailuna mai o ke kuahu, e kau hoi i ka mea ala maluna, a e hele koke aku i ke anaina kanaka, a e hookalahala no la kou; no ka mea, ua hele aku la ka inaina mai o Iehova aku; ua hoomakaia ke ahulau.
47 Aaroni ṣe bí Mose ti wí, ó sáré lọ sí àárín àwọn ènìyàn, ṣùgbọ́n àjàkálẹ̀-ààrùn ti bẹ̀rẹ̀ láàrín wọn, ṣùgbọ́n Aaroni fín tùràrí, ó sì ṣe ètùtù fún wọn.
Lawe aku la o Aarona, e like me ka Mose i kauoha'i, a holo aku la iwaena o ke anaina kanaka; aia hoi, ua hoomakaia ke ahulau iwaena o ka poe kanaka: kau iho la ia i ka mea ala, a hookalahala aku la no ka poe kanaka.
48 Ó dúró láàrín àwọn alààyè àti òkú, àjàkálẹ̀-ààrùn náà sì dúró.
Ku iho la ia iwaena o ka poe make a me ka poe ola; a hookiia iho la ke ahulau.
49 Ṣùgbọ́n àjàkálẹ̀-ààrùn ti pa ẹgbàá méje ó lé lẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀rin ènìyàn ní àfikún sí àwọn tí ó kú níbi ìṣẹ̀lẹ̀ Kora.
A o ka poe i make i ke ahulau, he umikumamaha tausani a me na haneri ehiku; he okoa ka poe i make no ka mea o Kora.
50 Aaroni padà tọ Mose lọ ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́ ìpàdé nítorí pé àjàkálẹ̀-ààrùn náà ti dúró.
A hoi hou ae la o Aarona io Mose la, ma ka puka o ka halelewa o ke anaina: a ua hookiia ke ahulau.

< Numbers 16 >