< Numbers 15 >
OLELO mai la o Iehova ia Mose, i mai la,
2 “Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, ‘Nígbà tí ẹ bá dé ilẹ̀ tí èmi ó fún yin gẹ́gẹ́ bí ibùgbé
E olelo aku oe i na mamo a Iseraela, a e i aku ia lakou, Aia komo aku oukou i ka aina o ko oukou noho ana, kahi a'u e haawi aku ai no oukou;
3 tí ẹ̀yin ó bá sì ṣe ẹbọ iná sí Olúwa ẹbọ sísun, tàbí ẹbọ, láti san ẹ̀jẹ́ pàtàkì tàbí ọrẹ àtinúwá, tàbí nínú àjọ yín, láti ṣe òórùn dídùn sí Olúwa nínú agbo ẹran tàbí ọ̀wọ́ ẹran,
A e kaumaha aku oukou ma ke ahi i mohai na Iehova, i mohaikuni paha, i mohaihooko i ka hoohiki paha, a i mohaialoha paha, a ma ka oukou mau ahaaina laa paha, i mea e hana'i i ke ala oluolu no Iehova, no na bipi paha, no na hipa paha;
4 nígbà náà ni kí ẹni tí ó bá mú ọrẹ rẹ̀ wá, yóò tún mú ẹbọ ohun jíjẹ ìdámẹ́wàá òsùwọ̀n ìyẹ̀fun kíkúnná pẹ̀lú ìdámẹ́rin òsùwọ̀n òróró wá síwájú Olúwa.
Alaila o ka mea nana e kaumaha aku kana mohai na Iehova, e lawe mai ia i mohaiai, he hapaumi o ka epa palaoa, i kawili pu ia me ka hapaha o ka hina aila.
5 Pẹ̀lú ọ̀dọ́-àgùntàn kọ̀ọ̀kan yálà fún ọrẹ tàbí ẹbọ sísun ni, kí ẹ pèsè ìdámẹ́rin òsùwọ̀n wáìnì gẹ́gẹ́ bí ohun mímu.
A o ka hapaha o ka hina waina i mohaiinu kau e hoomakaukau ai, me ka mohaikuni, a he mohai maoli paha, no ke keikihipa hookahi.
6 “‘Fún àgbò kan ni kí ẹ pèsè ọrẹ ohun jíjẹ ìdá méjì nínú mẹ́wàá òsùwọ̀n ìyẹ̀fun kíkúnná tí a fi ìdákan nínú mẹ́ta òsùwọ̀n òróró pò.
Ina no kekahi hipakane, e hoomakaukau oe i mohaiai, i elua hapaumi o ka epa palaoa i kawiliia me ka hapakolu o ka hina aila.
7 Àti ìdákan nínú mẹ́ta òsùwọ̀n wáìnì fún ọrẹ ohun mímu gẹ́gẹ́ bí òórùn dídùn sí Olúwa.
A e kaumaha aku oe i ka hapakolu o ka hina waina, i mohaiinu, i mea ala oluolu no Iehova.
8 “‘Nígbà tí ẹ bá sì pèsè ọ̀dọ́ akọ màlúù fún ọrẹ tàbí ẹbọ sísun, láti fi san ẹ̀jẹ́ tàbí fún ọrẹ àlàáfíà sí Olúwa,
I ka manawa au e hoomakaukau ai i ka bipikane i mohaikuni, a i mohaihooko i ka hoohiki paha, a i mohaihoomalu paha na Iehova;
9 ẹni náà yóò mú ọ̀dọ́ akọ màlúù náà wá pẹ̀lú ọrẹ ohun jíjẹ, ìdámẹ́ta nínú mẹ́wàá òsùwọ̀n ìyẹ̀fun ìyẹ̀fun kíkúnná tí a fi ìdajì òsùwọ̀n òróró pò.
Alaila e lawe pu mai oia me ka bipikane i mohaiai he akolu hapaumi o ka epa palaoa, i kawiliia me ka hapalua o ka hina aila.
10 Kí ó tún mú ìdajì òsùwọ̀n wáìnì wá fún ọrẹ ohun mímu. Yóò jẹ́ ọrẹ àfinásun, àní òórùn dídùn sí Olúwa.
A e lawe mai hoi oe i ka hapalua o ka hina waina i mohaiinu, he mohai i hanaia ma ke ahi, i mea ala oluolu no Iehova.
11 Báyìí ni kí ẹ ṣe pèsè ọ̀dọ́ akọ màlúù tàbí àgbò, ọ̀dọ́-àgùntàn tàbí ọmọ ewúrẹ́.
Pela e hanaia'ku ai no ka bipikane hookahi, a no ka hipakane hookahi, a no ke keikihipa, a no ke keikikao.
12 Ẹ ṣe bẹ́ẹ̀ fún ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn, iyekíye tí ẹ̀yin ìbá à pèsè.
E like me ka nui o na mea a oukou e hoomakaukau ai, pela no oukou e hana aku ai i kela mea keia mea a pau, e like me ka nui o lakou.
13 “‘Ẹnikẹ́ni tí ó bá jẹ́ ọmọ bíbí ilẹ̀ yín ni kí ó máa ṣe àwọn nǹkan wọ̀nyí nígbà tí ó bá mú ọrẹ àfinásun gẹ́gẹ́ bí òórùn dídùn wá fún Olúwa.
O na mea a pau i hanau ma ka aina, ma keia kumu ka lakou e hana'i ia mau mea, ma ke kaumaha ana aku i ka mohai i hanaia ma ke ahi, he mea ala oluolu no Iehova.
14 Bí àlejò kan bá ń gbé láàrín yín ní gbogbo ìran yín, bí irú ẹni bẹ́ẹ̀ bá fẹ́ mú ọrẹ àfinásun bí òórùn dídùn wá fún Olúwa, gbogbo bí ẹ bá ṣe ń ṣe náà ni kí ó ṣe.
Ina e noho ana ke kanaka e me oukou, a o kela mea keia mea iwaena o oukou, i na hanauna o oukou, a manao ia e kaumaha i ka mohai i hanaia ma ke ahi, he mea ala oluolu no Iehova; e like me ka oukou hana ana, pela hoi oia e hana'i.
15 Gbogbo ìjọ ènìyàn gbọdọ̀ ní òfin kan náà fún ọmọ bíbí ilẹ̀ yín àti fún àwọn àlejò tó ń gbé láàrín yín, èyí jẹ́ ìlànà títí láé fún àwọn ìran tó ń bọ̀. Ẹ̀yin àti àlejò tó ń gbé láàrín yín sì jẹ́ bákan náà níwájú Olúwa.
Hookahi no kanawai no oukou o ke anaina kanaka, a no ke kanaka e hoi e noho pu ana, he kanawai e mau loa ana no na hanauna o oukou: e like me oukou nei, pela no hoi ka malihini imua o Iehova.
16 Òfin kan àti ìlànà kan ni yóò wà fún yín àti fún àwọn àlejò tí ń gbé láàrín yín.’”
Hookahi no kanawai, a hookahi no kumu hana no oukou, a no ke kanaka e, e noho ana me oukou.
Olelo mai o Iehova ia Mose, i mai la,
18 “Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, ‘Nígbà tí ẹ bá dé ilẹ̀ tí mo ń mú yín lọ.
E olelo aku oe i na marao a Iseraela, a e i aku ia lakou, Aia hiki aku oukou i ka aina kahi a'u e hookomo ai ia oukou:
19 Tí ẹ sì jẹ oúnjẹ ilẹ̀ náà, ẹ mú nínú rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọrẹ ìgbésókè wá fún Olúwa.
A ai iho oukou i ka berena o ia aina, alaila e mohai aku oukou i mohaihoali na Iehova.
20 Ẹ mú àkàrà wá nínú àkọ́so oúnjẹ yín wá gẹ́gẹ́ bí ọrẹ ìgbésókè sí Olúwa, ọrẹ láti inú ilẹ̀ ìpakà yín.
A e lawe mai oukou i ka popo mua o ka oukou palaoa kawili i mohaihoali, e like me ka mohaihoali o kahi hehipalaoa, pela oukou e mohai ai ia.
21 Nínú àkọ́so oúnjẹ yín ni kí ẹ ti máa mú ọrẹ ìgbésókè yìí fún Olúwa.
No ka mua o ka oukou palaoa kawili ka oukou e haawi aku ia Iehova i mohaihoali ma ko oukou mau hanauna.
22 “‘Bí ẹ bá kùnà láìròtẹ́lẹ̀ láti pa àwọn òfin tí Olúwa fún Mose mọ́,
Ina i lalau oukou, aole hoi i malama i keia mau kauoha a pau a Iehova i olelo mai ai ma o Mose la,
23 èyí ni gbogbo òfin tí Olúwa fún yín láti ẹnu Mose láti ọjọ́ tí Olúwa ti fún yín àti títí dé ìran tó ń bọ̀.
I na mea a pau a Iehova i kauoha mai ai ma ka lima o Mose mai ka la a Iehova i kauoha mai ai, a ma keia hope aku iwaeua o na hanauna o oukou;
24 Bí ẹ̀ṣẹ̀ bá wáyé láìròtẹ́lẹ̀ láìjẹ́ pé ìjọ ènìyàn mọ̀ sí i, nígbà náà ni kí gbogbo ìjọ ènìyàn mú ọ̀dọ́ akọ màlúù kan wá fún ẹbọ sísun bí òórùn dídùn sí Olúwa, pẹ̀lú ọrẹ ohun jíjẹ àti ọrẹ ohun mímu rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ìlànà, pẹ̀lú akọ ewúrẹ́ fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀.
Alaila, ina paha e hana hewa naaupo ia, a ua ike ole ia e ke anaina kanaka, e kaumaha aku no ke anaina kanaka a pau i hookahi bipikane hou i mohaikuni, i mea ala oluolu no Iehova, me kana mohaiai, a me kana mohaiinu, mamuli o ke kanawai; a i hookahi keikikao i mohaihala;
25 Àlùfáà yóò sì ṣe ètùtù, fun gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli, a ó sì dáríjì wọ́n, nítorí ẹ̀ṣẹ̀ àìròtẹ́lẹ̀, wọ́n sì ti mú ọrẹ àfinásun wá fún Olúwa nítorí ẹ̀ṣẹ̀ tí wọ́n ṣẹ̀.
A na ke kahuna e hookala-hala no ke anaina kanaka a pau o na mamo a Iseraela, a e kalaia ia no lakou; no ka mea, he naaupo ia: a e lawe mai lakou i ka lakou mohai, i mohai i hanaia ma ke ahi na Iehova, a me ka lakou mohailiala imua o Iehova, no ko lakou naaupo ana:
26 A ó dárí jí gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli àti àwọn àjèjì tí ń gbé ní àárín wọn nítorí pé ní àìròtẹ́lẹ̀ ni wọ́n sẹ ẹ̀ṣẹ̀ náà.
A e kalaia ia no ke anaina a pau o na mamo a Iseraela, a no ke kanaka e e noho ana iwaena o lakou: no ka mea, iloko o ka naaupo ka poe kanaka a pau.
27 “‘Ṣùgbọ́n bí ó bá jẹ́ pé ẹnìkan ló sẹ̀ ní àìròtẹ́lẹ̀, kí ó mú abo ewúrẹ́ ọlọ́dún kan wá fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀.
A i hana hewa naaupo kekahi kanaka, alaila, e lawe mai ia i kaowahine o ka makahiki mua, i mohaihala.
28 Àlùfáà yóò ṣe ètùtù níwájú Olúwa fún ẹni tó ṣẹ̀ láìròtẹ́lẹ̀, tí wọ́n bá ṣe ètùtù fún un, a ó sì dáríjì í.
A e hookalahala ke kahuna no ke kanaka i hana hewa naaupo, ke hana hewa naaupo ia imua o Iehova, i mea kalaia i ka hala nona; a e kalaia no ia nona.
29 Òfin kan kí ẹ̀yin kí ó ní fún ẹnikẹ́ni tó bá ṣẹ̀ ní àìmọ̀, àti fún àwọn ẹni tí a bí nínú àwọn ọmọ Israẹli, àti fún àlejò tí ń ṣe àtìpó.
I hookahi no kanawai o oukou no ka mea hana hewa naaupo, no ka mea i hanau iwaena o na mamo a Iseraela, a no ke kanaka e e noho ana me oukou.
30 “‘Ṣùgbọ́n bí ẹnikẹ́ni bá mọ̀ ọ́n mọ̀ dẹ́ṣẹ̀ yálà ó jẹ́ ọmọ bíbí ilẹ̀ yín tàbí àlejò, irú ẹni bẹ́ẹ̀ ti kó ẹ̀gàn bá orúkọ Olúwa, a ó sì gé irú ẹni bẹ́ẹ̀ kúrò lára àwọn ènìyàn rẹ̀.
Aka, o ke kanaka hana hewa me ka hookiekie, o ke keikipapa, a me ke kanaka e, oia ka mea hoino ia Iehova; a e hookiia'ku ua kanaka la maiwaena aku o kona hanauna.
31 Nítorí pé ẹni náà ti kẹ́gàn ọ̀rọ̀ Olúwa ó sì ti rú òfin rẹ̀, a gbọdọ̀ gé irú ẹni bẹ́ẹ̀ kúrò láàrín àwọn ènìyàn rẹ̀; ẹ̀bi rẹ̀ yóò sì wà lórí rẹ̀.’”
No ka mea, ua hoowahawaha aku ia i ka olelo a Iehova, ua haihai iho oia i kona kanawai, e hooki loa ia aku oia; maluna iho ona kona hewa.
32 Nígbà tí àwọn ọmọ Israẹli wà nínú aginjù, wọ́n rí ọkùnrin kan tí ń ṣá igi ní ọjọ́ Ìsinmi.
Maloko o ka waonahele na mamo a Iseraela, a loaa ia lakou he kanaka nana i hoiliili i ka wahie i ka la Sabati.
33 Àwọn tó sì rí i níbi tó ti ń ṣá igi wọ́n sì mú un wá sí ọ̀dọ̀ Mose àti Aaroni àti síwájú gbogbo ìjọ ènìyàn,
A o ka poe i ike ia ia e hoiliili ana i ka wahie, kai mai la lakou ia ia io Mose laua o Aarona la, a i ke anaina kanaka a pau.
34 wọ́n fi sí ìpamọ́ nítorí pé ohun tí wọn ó ṣe fún un kò tí ì yé wọn.
Hoonoho iho la lakou ia ia ma kahi paa; no ka mea, aole i hoikeia mai ka mea i hanaia'ku ai ia ia.
35 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Mose pé, “Kíkú ni ọkùnrin náà yóò kú kí gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli sọ ọ́ lókùúta pa ní ẹ̀yìn ibùdó.”
Olelo mai la o Iehova ia Mose, He oiaio no, e make ia kanaka: na ke anaina kanaka a pau ia e hailuku aku mawaho o kahi hoomoana.
36 Wọ́n mú un jáde sí ẹ̀yìn ibùdó, gbogbo ìjọ ènìyàn sì sọ ọ́ lókùúta pa, gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.
Kai aku la na kanaka a pau ia ia mawaho o kahi hoomoana, hailuku aku la ia ia a make, me ka Iehova i kauoha mai ai ia Mose.
Olelo mai la o Iehova ia Mose, i mai la,
38 “Bá àwọn ọmọ Israẹli sọ̀rọ̀, kí o sọ fún wọn pé: ‘Títí dé àwọn ìran tó ń bọ̀ ni kí wọn máa ṣe wajawaja sí etí aṣọ wọn, kí wọn sì fi okùn tẹ́ẹ́rẹ́ aláwọ̀ búlúù sí wajawaja kọ̀ọ̀kan.
E olelo aku oe i na mamo a Iseraela, e i aku ia lakou, e hana lakou i na pihapiha ma na kihi o ko lakou mau aahu, ma na hanauna o lakou, a e hoopili iho lakou i ke kaula ribina uliuli ma na pihapiha o na kihi.
39 Wajawaja yìí ni ẹ sì máa wọ̀ láti lè mú yín rántí gbogbo òfin Olúwa, kí ẹ bá à lè ṣe wọ́n, kí ẹ sì má bá à ṣe àgbèrè nípa títẹ̀lé ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ọkàn àti ojú yín.
A e lilo iho ia no oukou i pihapiha, e nana iho ai, a e hoomanao i na kauoha a pau a Iehova, a e malama hoi ia lakou; i ole ai oukou e imi aku mamuli o ko oukou mau naau, a me ko oukou mau maka; mamuli o ia mau mea ka oukou i hele moekolohe ai:
40 Nígbà náà ni ẹ ó gbọ́rọ̀ láti pa gbogbo òfin mi mọ́, ẹ ó sì jẹ́ mímọ́ sí Ọlọ́run yín.
I hoomanao ai oukou, a e hana hoi i ka'u mau kauoha a pau, a e lilo oukou i poe laa no ko oukou Akua.
41 Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín tí ó mú yín jáde láti Ejibiti láti jẹ́ Ọlọ́run yín. Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín.’”
Owau no Iehova o ko oukou Akua, nana oukou i lawe ae mailoko mai o ka aina o Aigupita, i Akua wau no oukou: owau no Iehova o ko oukou Akua.