< Numbers 15 >
Nake Jehova akĩĩra Musa atĩrĩ,
2 “Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, ‘Nígbà tí ẹ bá dé ilẹ̀ tí èmi ó fún yin gẹ́gẹ́ bí ibùgbé
“Arĩria andũ a Isiraeli, ũmeere atĩrĩ: ‘Thuutha wa gũtoonya bũrũri ũrĩa ngũmũhe ũtuĩke mũciĩ wanyu,
3 tí ẹ̀yin ó bá sì ṣe ẹbọ iná sí Olúwa ẹbọ sísun, tàbí ẹbọ, láti san ẹ̀jẹ́ pàtàkì tàbí ọrẹ àtinúwá, tàbí nínú àjọ yín, láti ṣe òórùn dídùn sí Olúwa nínú agbo ẹran tàbí ọ̀wọ́ ẹran,
na mũrutĩre Jehova maruta ma njino kuuma rũũru rwa ngʼombe kana rwa mbũri, matuĩke mũtararĩko wa gũkenia Jehova, marĩ maruta ma njino, kana magongona, nĩ ũndũ wa mĩĩhĩtwa ya mwanya, kana maruta ma kwĩyendera kana maruta ma ciathĩ-rĩ,
4 nígbà náà ni kí ẹni tí ó bá mú ọrẹ rẹ̀ wá, yóò tún mú ẹbọ ohun jíjẹ ìdámẹ́wàá òsùwọ̀n ìyẹ̀fun kíkúnná pẹ̀lú ìdámẹ́rin òsùwọ̀n òróró wá síwájú Olúwa.
ũrĩa ũrĩĩrehaga iruta rĩake, arĩĩrutagĩra Jehova iruta rĩa mũtu gĩcunjĩ gĩa ikũmi kĩa eba ĩmwe ya mũtu mũhinyu mũno, ũtukanĩtio na gĩcunjĩ kĩa inya kĩa hini ĩmwe ya maguta.
5 Pẹ̀lú ọ̀dọ́-àgùntàn kọ̀ọ̀kan yálà fún ọrẹ tàbí ẹbọ sísun ni, kí ẹ pèsè ìdámẹ́rin òsùwọ̀n wáìnì gẹ́gẹ́ bí ohun mímu.
Harĩ o gatũrũme ka iruta rĩa njino kana igongona, haaragĩria gĩcunjĩ kĩa inya kĩa hini ĩmwe ya ndibei ĩrĩ iruta rĩa kũnyuuo.
6 “‘Fún àgbò kan ni kí ẹ pèsè ọrẹ ohun jíjẹ ìdá méjì nínú mẹ́wàá òsùwọ̀n ìyẹ̀fun kíkúnná tí a fi ìdákan nínú mẹ́ta òsùwọ̀n òróró pò.
“‘Igongona rĩa ndũrũme-rĩ, haarĩria igongona rĩa mũtu icunjĩ igĩrĩ cia ikũmi cia eba ĩmwe ya mũtu mũhinyu mũno, ũtukanĩtio na gĩcunjĩ gĩa ithatũ kĩa hini ĩmwe ya maguta,
7 Àti ìdákan nínú mẹ́ta òsùwọ̀n wáìnì fún ọrẹ ohun mímu gẹ́gẹ́ bí òórùn dídùn sí Olúwa.
na gĩcunjĩ gĩa ithatũ kĩa hini ĩmwe ya ndibei ĩrĩ iruta rĩa kũnyuuo. Rĩrutei rĩrĩ mũtararĩko wa gũkenia Jehova.
8 “‘Nígbà tí ẹ bá sì pèsè ọ̀dọ́ akọ màlúù fún ọrẹ tàbí ẹbọ sísun, láti fi san ẹ̀jẹ́ tàbí fún ọrẹ àlàáfíà sí Olúwa,
“‘Rĩrĩa mũkũhaarĩria gategwa nĩ ũndũ wa iruta rĩa njino kana igongona, nĩ ũndũ wa mwĩhĩtwa wa mwanya kana iruta rĩa ũiguano rĩrutĩirwo Jehova-rĩ,
9 ẹni náà yóò mú ọ̀dọ́ akọ màlúù náà wá pẹ̀lú ọrẹ ohun jíjẹ, ìdámẹ́ta nínú mẹ́wàá òsùwọ̀n ìyẹ̀fun ìyẹ̀fun kíkúnná tí a fi ìdajì òsùwọ̀n òróró pò.
rehagai hamwe na ndegwa ĩyo iruta rĩa mũtu icunjĩ ithatũ cia ikũmi cia eba ĩmwe ya mũtu mũhinyu mũno, ũtukanĩtio na nuthu ya hini ĩmwe ya maguta.
10 Kí ó tún mú ìdajì òsùwọ̀n wáìnì wá fún ọrẹ ohun mímu. Yóò jẹ́ ọrẹ àfinásun, àní òórùn dídùn sí Olúwa.
O na ningĩ rehagai nuthu ya hini ĩmwe ya ndibei ĩrĩ iruta rĩa kũnyuuo. Narĩo igongona rĩu rĩgatuĩka iruta rĩa njino rĩrĩ mũtararĩko wa gũkenia Jehova.
11 Báyìí ni kí ẹ ṣe pèsè ọ̀dọ́ akọ màlúù tàbí àgbò, ọ̀dọ́-àgùntàn tàbí ọmọ ewúrẹ́.
Ndegwa kana ndũrũme o yothe, kana gatũrũme kana koori o gothe, irĩhaaragĩrio o ro ũguo.
12 Ẹ ṣe bẹ́ẹ̀ fún ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn, iyekíye tí ẹ̀yin ìbá à pèsè.
Ĩkagai ũguo harĩ o ĩmwe yacio ya iria ciothe mũrĩharagĩria.
13 “‘Ẹnikẹ́ni tí ó bá jẹ́ ọmọ bíbí ilẹ̀ yín ni kí ó máa ṣe àwọn nǹkan wọ̀nyí nígbà tí ó bá mú ọrẹ àfinásun gẹ́gẹ́ bí òórùn dídùn wá fún Olúwa.
“‘Mũndũ wothe ũciarĩirwo kwanyu no nginya ekage maũndũ macio ũguo rĩrĩa arĩrehaga iruta rĩa gũcinwo na mwaki rĩrĩ mũtararĩko wa gũkenia Jehova.
14 Bí àlejò kan bá ń gbé láàrín yín ní gbogbo ìran yín, bí irú ẹni bẹ́ẹ̀ bá fẹ́ mú ọrẹ àfinásun bí òórùn dídùn wá fún Olúwa, gbogbo bí ẹ bá ṣe ń ṣe náà ni kí ó ṣe.
Nĩ ũndũ wa njiarwa iria igooka, rĩrĩa rĩothe mũgeni kana mũndũ ũngĩ o wothe ũtũũranĩtie na inyuĩ arĩĩrutaga iruta rĩa gũcinwo na mwaki rĩrĩ mũtararĩko wa gũkenia Jehova-rĩ, no nginya ekage o ta ũrĩa inyuĩ mwĩkaga.
15 Gbogbo ìjọ ènìyàn gbọdọ̀ ní òfin kan náà fún ọmọ bíbí ilẹ̀ yín àti fún àwọn àlejò tó ń gbé láàrín yín, èyí jẹ́ ìlànà títí láé fún àwọn ìran tó ń bọ̀. Ẹ̀yin àti àlejò tó ń gbé láàrín yín sì jẹ́ bákan náà níwájú Olúwa.
Kĩrĩndĩ gĩkĩ kĩrĩkoragwo na watho o ũmwe wanyu na harĩ mũgeni ũrĩa ũtũũranĩtie na inyuĩ; ũyũ nĩ watho wa gũtũũra nĩ ũndũ wa njiarwa iria igooka. Inyuĩ na mũgeni mũrĩkoragwo mũrĩ o ũndũ ũmwe maitho-inĩ ma Jehova.
16 Òfin kan àti ìlànà kan ni yóò wà fún yín àti fún àwọn àlejò tí ń gbé láàrín yín.’”
Mawatho mamwe na mwathanĩre ũmwe nĩguo ũrĩhũthagĩrwo harĩ inyuĩ na harĩ mũgeni ũrĩa ũtũũranĩtie na inyuĩ.’”
Ningĩ Jehova akĩĩra Musa atĩrĩ,
18 “Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, ‘Nígbà tí ẹ bá dé ilẹ̀ tí mo ń mú yín lọ.
“Arĩria andũ a Isiraeli, ũmeere atĩrĩ: ‘Rĩrĩa mũgatoonya bũrũri ũrĩa ndĩramũtwara,
19 Tí ẹ sì jẹ oúnjẹ ilẹ̀ náà, ẹ mú nínú rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọrẹ ìgbésókè wá fún Olúwa.
na mũrĩe irio cia bũrũri ũcio, heanai imwe ciacio irĩ iruta harĩ Jehova.
20 Ẹ mú àkàrà wá nínú àkọ́so oúnjẹ yín wá gẹ́gẹ́ bí ọrẹ ìgbésókè sí Olúwa, ọrẹ láti inú ilẹ̀ ìpakà yín.
Nĩ mũkaaruta tũmĩgate kuuma mũtu-inĩ wanyu ũrĩa mũgaathĩa rĩa mbere na mũtũheane tũrĩ iruta kĩhuhĩro-inĩ kĩa ngano.
21 Nínú àkọ́so oúnjẹ yín ni kí ẹ ti máa mú ọrẹ ìgbésókè yìí fún Olúwa.
Nĩmũkaheanaga iruta rĩrĩ rĩa mũtu ũrĩa mũgathĩa rĩa mbere kũrĩ Jehova njiarwa-inĩ cianyu ciothe iria igooka thuutha.
22 “‘Bí ẹ bá kùnà láìròtẹ́lẹ̀ láti pa àwọn òfin tí Olúwa fún Mose mọ́,
“‘Na rĩrĩ, mũngĩkaaga kũrũmĩrĩra rĩathani o na rĩmwe rĩa maya Jehova aaheire Musa mũtekwenda-rĩ,
23 èyí ni gbogbo òfin tí Olúwa fún yín láti ẹnu Mose láti ọjọ́ tí Olúwa ti fún yín àti títí dé ìran tó ń bọ̀.
rĩathani o rĩothe Jehova aamũheire na kanua ka Musa kuuma mũthenya ũrĩa Jehova aamaheanire na kũrũmĩrĩra nginya njiarwa iria igooka,
24 Bí ẹ̀ṣẹ̀ bá wáyé láìròtẹ́lẹ̀ láìjẹ́ pé ìjọ ènìyàn mọ̀ sí i, nígbà náà ni kí gbogbo ìjọ ènìyàn mú ọ̀dọ́ akọ màlúù kan wá fún ẹbọ sísun bí òórùn dídùn sí Olúwa, pẹ̀lú ọrẹ ohun jíjẹ àti ọrẹ ohun mímu rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ìlànà, pẹ̀lú akọ ewúrẹ́ fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀.
na ũndũ ũcio ũngĩkorwo wĩkĩtwo mũtekwenda, kĩrĩndĩ gĩtekũmenya ũhoro ũcio, hĩndĩ ĩyo kĩrĩndĩ gĩothe nĩgĩkaruta gategwa gatuĩke igongona rĩa njino rĩna mũtararĩko wa gũkenia Jehova, hamwe na maruta ma mũtu na ma kũnyuuo, marĩa matuĩtwo, na thenge ya igongona rĩa kũhoroheria mehia.
25 Àlùfáà yóò sì ṣe ètùtù, fun gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli, a ó sì dáríjì wọ́n, nítorí ẹ̀ṣẹ̀ àìròtẹ́lẹ̀, wọ́n sì ti mú ọrẹ àfinásun wá fún Olúwa nítorí ẹ̀ṣẹ̀ tí wọ́n ṣẹ̀.
Mũthĩnjĩri-Ngai nĩakahoroheria kĩrĩndĩ kĩu gĩothe kĩa andũ a Isiraeli, na nĩmakarekerwo, nĩgũkorwo ũndũ ũcio ndwarĩ wa rũtũrĩko, na nĩ ũndũ wa kũrutĩra Jehova iruta rĩa gũcinwo na mwaki rĩa mahĩtia mao, na iruta rĩa kũhoroherio mehia.
26 A ó dárí jí gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli àti àwọn àjèjì tí ń gbé ní àárín wọn nítorí pé ní àìròtẹ́lẹ̀ ni wọ́n sẹ ẹ̀ṣẹ̀ náà.
Kĩrĩndĩ gĩothe kĩa andũ a Isiraeli na ageni arĩa matũũranagia nao nĩmakarekerwo, nĩ ũndũ andũ othe mehĩtie matekwenda.
27 “‘Ṣùgbọ́n bí ó bá jẹ́ pé ẹnìkan ló sẹ̀ ní àìròtẹ́lẹ̀, kí ó mú abo ewúrẹ́ ọlọ́dún kan wá fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀.
“‘No kũngĩkorwo no mũndũ ũmwe wĩhĩtie atekwenda, no nginya arehe kaharika ka mwaka ũmwe ka igongona rĩa kũhoroherio mehia.
28 Àlùfáà yóò ṣe ètùtù níwájú Olúwa fún ẹni tó ṣẹ̀ láìròtẹ́lẹ̀, tí wọ́n bá ṣe ètùtù fún un, a ó sì dáríjì í.
Mũthĩnjĩri-Ngai nĩakahoroheria mũndũ ũcio wĩhĩtie atekwenda hau mbere ya Jehova na aarĩkia kũhoroherio, nĩakarekerwo.
29 Òfin kan kí ẹ̀yin kí ó ní fún ẹnikẹ́ni tó bá ṣẹ̀ ní àìmọ̀, àti fún àwọn ẹni tí a bí nínú àwọn ọmọ Israẹli, àti fún àlejò tí ń ṣe àtìpó.
Watho o ro ũmwe nĩguo ũrĩhũthagĩrwo harĩ mũndũ o wothe ũkehia atekwenda, arĩ Mũisiraeli ũciarĩirwo kwanyu kana arĩ mũgeni.
30 “‘Ṣùgbọ́n bí ẹnikẹ́ni bá mọ̀ ọ́n mọ̀ dẹ́ṣẹ̀ yálà ó jẹ́ ọmọ bíbí ilẹ̀ yín tàbí àlejò, irú ẹni bẹ́ẹ̀ ti kó ẹ̀gàn bá orúkọ Olúwa, a ó sì gé irú ẹni bẹ́ẹ̀ kúrò lára àwọn ènìyàn rẹ̀.
“‘No mũndũ ũrĩa ũkehia na rũtũrĩko akĩendaga, arĩ wa gũciarĩrwo kwanyu kana arĩ mũgeni, ũcio nĩarumĩte Jehova, na mũndũ ũcio no nginya aingatwo kuuma kũrĩ andũ ao.
31 Nítorí pé ẹni náà ti kẹ́gàn ọ̀rọ̀ Olúwa ó sì ti rú òfin rẹ̀, a gbọdọ̀ gé irú ẹni bẹ́ẹ̀ kúrò láàrín àwọn ènìyàn rẹ̀; ẹ̀bi rẹ̀ yóò sì wà lórí rẹ̀.’”
Nĩ ũndũ nĩ amenete kiugo kĩa Jehova na akoina maathani make, mũndũ ũcio ti-itherũ no nginya aingatwo biũ naguo wĩhia wake nĩũkamũcokerera.’”
32 Nígbà tí àwọn ọmọ Israẹli wà nínú aginjù, wọ́n rí ọkùnrin kan tí ń ṣá igi ní ọjọ́ Ìsinmi.
Hĩndĩ ĩrĩa andũ a Isiraeli maarĩ werũ-inĩ, kũrĩ mũndũ wonirwo akiuna ngũ mũthenya wa Thabatũ.
33 Àwọn tó sì rí i níbi tó ti ń ṣá igi wọ́n sì mú un wá sí ọ̀dọ̀ Mose àti Aaroni àti síwájú gbogbo ìjọ ènìyàn,
Arĩa maamuonire akiuna ngũ makĩmũtwara kũrĩ Musa na Harũni, o na kũrĩ kĩũngano kĩu gĩothe gĩa Isiraeli,
34 wọ́n fi sí ìpamọ́ nítorí pé ohun tí wọn ó ṣe fún un kò tí ì yé wọn.
na makĩmũhingĩra nĩ ũndũ gũtiamenyekaga ũrĩa agĩrĩirwo nĩ gwĩkwo.
35 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Mose pé, “Kíkú ni ọkùnrin náà yóò kú kí gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli sọ ọ́ lókùúta pa ní ẹ̀yìn ibùdó.”
Nake Jehova akĩĩra Musa atĩrĩ, “Mũndũ ũcio no nginya akue. Kĩũngano gĩothe kĩa Isiraeli no nginya kĩmũhũũre na mahiga nyuguto nja ya kambĩ.”
36 Wọ́n mú un jáde sí ẹ̀yìn ibùdó, gbogbo ìjọ ènìyàn sì sọ ọ́ lókùúta pa, gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.
Nĩ ũndũ ũcio kĩũngano kĩu gĩkĩmũtwara nja ya kambĩ gĩkĩmũhũũra na mahiga nyuguto agĩkua, o ta ũrĩa Jehova aathĩte Musa.
Nake Jehova akĩĩra Musa atĩrĩ,
38 “Bá àwọn ọmọ Israẹli sọ̀rọ̀, kí o sọ fún wọn pé: ‘Títí dé àwọn ìran tó ń bọ̀ ni kí wọn máa ṣe wajawaja sí etí aṣọ wọn, kí wọn sì fi okùn tẹ́ẹ́rẹ́ aláwọ̀ búlúù sí wajawaja kọ̀ọ̀kan.
“Arĩria andũ a Isiraeli, ũmeere atĩrĩ: ‘Njiarwa-inĩ ciothe iria igooka, nĩmũgatumagĩrĩra ciohe cia ndigi koine-inĩ ka nguo cianyu, o kĩohe gĩkohererwo na rũrigi rwa rangi wa bururu.
39 Wajawaja yìí ni ẹ sì máa wọ̀ láti lè mú yín rántí gbogbo òfin Olúwa, kí ẹ bá à lè ṣe wọ́n, kí ẹ sì má bá à ṣe àgbèrè nípa títẹ̀lé ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ọkàn àti ojú yín.
Ciohe icio nĩcio mũrĩroraga nĩguo mũririkanage maathani mothe ma Jehova, nĩguo mũmathĩkagĩre, mũtikanahũũre ũmaraya na ũndũ wa kũrũmĩrĩra merirĩria ma ngoro o na kana maitho manyu.
40 Nígbà náà ni ẹ ó gbọ́rọ̀ láti pa gbogbo òfin mi mọ́, ẹ ó sì jẹ́ mímọ́ sí Ọlọ́run yín.
Ningĩ nĩmũkaririkanaga gwathĩkagĩra maathani makwa mothe na mũtuĩke andũ mamũrĩirwo Ngai wanyu.
41 Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín tí ó mú yín jáde láti Ejibiti láti jẹ́ Ọlọ́run yín. Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín.’”
Niĩ nĩ niĩ Jehova Ngai wanyu, ũrĩa wamũrutire bũrũri wa Misiri nĩguo nduĩke Ngai wanyu. Niĩ nĩ niĩ Jehova Ngai wanyu.’”