< Numbers 15 >

1 Olúwa sọ fún Mose pé,
BAWIPA ni Mosi hah a pato teh,
2 “Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, ‘Nígbà tí ẹ bá dé ilẹ̀ tí èmi ó fún yin gẹ́gẹ́ bí ibùgbé
Isarelnaw hah pato nateh ahnimouh koe Na o nahane ram kai ni na poe e ram koe na pha awh toteh,
3 tí ẹ̀yin ó bá sì ṣe ẹbọ iná sí Olúwa ẹbọ sísun, tàbí ẹbọ, láti san ẹ̀jẹ́ pàtàkì tàbí ọrẹ àtinúwá, tàbí nínú àjọ yín, láti ṣe òórùn dídùn sí Olúwa nínú agbo ẹran tàbí ọ̀wọ́ ẹran,
BAWIPA koe hmai hoi thuengnae, hmaisawi thuengnae thoseh, lawkkam kuep sak nahanelah, ma lungtho lahoi pawito nah na poe awh e thuengnae thoseh, saringhu dawk hoi tuhunaw thung dawk hoi thoseh, BAWIPA hanlah hmuitui hanelah na poe awh toteh,
4 nígbà náà ni kí ẹni tí ó bá mú ọrẹ rẹ̀ wá, yóò tún mú ẹbọ ohun jíjẹ ìdámẹ́wàá òsùwọ̀n ìyẹ̀fun kíkúnná pẹ̀lú ìdámẹ́rin òsùwọ̀n òróró wá síwájú Olúwa.
BAWIPA koe thuengnae ka poe e pueng ni, tavai thuengnae, tavaikanui ephah pung hra pung touh, satui pung pali pung touh kanawk e hoi,
5 Pẹ̀lú ọ̀dọ́-àgùntàn kọ̀ọ̀kan yálà fún ọrẹ tàbí ẹbọ sísun ni, kí ẹ pèsè ìdámẹ́rin òsùwọ̀n wáìnì gẹ́gẹ́ bí ohun mímu.
nei hane thuengnae koevah, misurtui hnin pung pali pung touh, hmaisawi thuengnae koevah thoseh, poenae koevah tuca tangkuem hanelah na rakueng awh han.
6 “‘Fún àgbò kan ni kí ẹ pèsè ọrẹ ohun jíjẹ ìdá méjì nínú mẹ́wàá òsùwọ̀n ìyẹ̀fun kíkúnná tí a fi ìdákan nínú mẹ́ta òsùwọ̀n òróró pò.
Telah hoehpawiteh, tutan buet touh dawkvah, tavai thuengnae a kanui e tavai ephah pung hra pung hni, satui pung thum pung touh hoi kanawk e,
7 Àti ìdákan nínú mẹ́ta òsùwọ̀n wáìnì fún ọrẹ ohun mímu gẹ́gẹ́ bí òórùn dídùn sí Olúwa.
BAWIPA hanlah nei thuengnae hmuitui dawk misurtui hin pung thum pung touh na poe awh han.
8 “‘Nígbà tí ẹ bá sì pèsè ọ̀dọ́ akọ màlúù fún ọrẹ tàbí ẹbọ sísun, láti fi san ẹ̀jẹ́ tàbí fún ọrẹ àlàáfíà sí Olúwa,
Hmaisawi thuengnae thoseh, lawkkam kuepsaknae thuengnae thoseh, BAWIPA koe roum thuengnae dawk maitotan na rakueng awh toteh,
9 ẹni náà yóò mú ọ̀dọ́ akọ màlúù náà wá pẹ̀lú ọrẹ ohun jíjẹ, ìdámẹ́ta nínú mẹ́wàá òsùwọ̀n ìyẹ̀fun ìyẹ̀fun kíkúnná tí a fi ìdajì òsùwọ̀n òróró pò.
maitotan poenae hoi tavai thuengnae, tavaikanui ephah pung hra pung thum, satui hin tangawn hoi kanawk e,
10 Kí ó tún mú ìdajì òsùwọ̀n wáìnì wá fún ọrẹ ohun mímu. Yóò jẹ́ ọrẹ àfinásun, àní òórùn dídùn sí Olúwa.
nei thueng nahanelah misurtui hin tangawn, BAWIPA hanlah hmuitui hoi thuengnae na sak awh han.
11 Báyìí ni kí ẹ ṣe pèsè ọ̀dọ́ akọ màlúù tàbí àgbò, ọ̀dọ́-àgùntàn tàbí ọmọ ewúrẹ́.
Hot patetlah maitotan hanlah thoseh, tutan hanlah thoseh, tuca hoiyah hmaeca hanlah na sak awh han.
12 Ẹ ṣe bẹ́ẹ̀ fún ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn, iyekíye tí ẹ̀yin ìbá à pèsè.
Ayoun apap e lahoi na rakueng awh vaiteh, ayoun apap e lahoi na sak awh han.
13 “‘Ẹnikẹ́ni tí ó bá jẹ́ ọmọ bíbí ilẹ̀ yín ni kí ó máa ṣe àwọn nǹkan wọ̀nyí nígbà tí ó bá mú ọrẹ àfinásun gẹ́gẹ́ bí òórùn dídùn wá fún Olúwa.
Hote ram dawk hoi ka tâcawt e pueng ni, het patetlah BAWIPA hanlah hmuitui hmaisawi thuengnae a poe awh navah, a sak awh han.
14 Bí àlejò kan bá ń gbé láàrín yín ní gbogbo ìran yín, bí irú ẹni bẹ́ẹ̀ bá fẹ́ mú ọrẹ àfinásun bí òórùn dídùn wá fún Olúwa, gbogbo bí ẹ bá ṣe ń ṣe náà ni kí ó ṣe.
Nangmouh koe kho ka sak e imyin thoseh, nangmouh se nah nangmouh koe kho ka sak e naw pueng ni, BAWIPA hanlah hmai hoi hmuitui thuengnae hah nama ni na sak e patetlah a sak awh van han.
15 Gbogbo ìjọ ènìyàn gbọdọ̀ ní òfin kan náà fún ọmọ bíbí ilẹ̀ yín àti fún àwọn àlejò tó ń gbé láàrín yín, èyí jẹ́ ìlànà títí láé fún àwọn ìran tó ń bọ̀. Ẹ̀yin àti àlejò tó ń gbé láàrín yín sì jẹ́ bákan náà níwájú Olúwa.
Na se yunglam pueng dawkvah, kamkhueng e maya hoi nangmouh koe kaawm e imyin han haiyah, phung buet touh dueng doeh kaawm han. BAWIPA hmalah imyin teh namamouh patetlah ao han.
16 Òfin kan àti ìlànà kan ni yóò wà fún yín àti fún àwọn àlejò tí ń gbé láàrín yín.’”
Namamouh han hoi nangmouh koe imyin kaawm e hanlah kâlawk buet touh hoi sak kawi buet touh dueng doeh kaawm han, tet pout telah ati.
17 Olúwa sọ fún Mose pé,
BAWIPA ni Mosi hah a pato teh,
18 “Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, ‘Nígbà tí ẹ bá dé ilẹ̀ tí mo ń mú yín lọ.
Isarelnaw pato nateh, ahnimouh koe ceikhai hanelah ka noe e ram dawk na pha awh toteh,
19 Tí ẹ sì jẹ oúnjẹ ilẹ̀ náà, ẹ mú nínú rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọrẹ ìgbésókè wá fún Olúwa.
hote ram dawk vaiyei na ca awh toteh, BAWIPA koe kahek thuengnae na sak awh han.
20 Ẹ mú àkàrà wá nínú àkọ́so oúnjẹ yín wá gẹ́gẹ́ bí ọrẹ ìgbésókè sí Olúwa, ọrẹ láti inú ilẹ̀ ìpakà yín.
Nangmouh koe hmaloe kanawk e, vaiyei heh kahek thuengnae koe na poe awh han. Kahek thuengnae na sak awh e patetlah na kahek awh han.
21 Nínú àkọ́so oúnjẹ yín ni kí ẹ ti máa mú ọrẹ ìgbésókè yìí fún Olúwa.
Na catounnaw totouh tavai hmaloe kanawk e hah BAWIPA koe kahek thuengnae na poe awh han.
22 “‘Bí ẹ bá kùnà láìròtẹ́lẹ̀ láti pa àwọn òfin tí Olúwa fún Mose mọ́,
Hete kâpoe BAWIPA ni Mosi koevah, a dei e pueng BAWIPA ni kâpoelawknaw a kamtawngnae koehoi na catounnaw hanelah,
23 èyí ni gbogbo òfin tí Olúwa fún yín láti ẹnu Mose láti ọjọ́ tí Olúwa ti fún yín àti títí dé ìran tó ń bọ̀.
Mosi hno lahoi kâpoelawk a poe e naw pueng hah dâw laipalah, ceknoe e awm laipalah hoi yonnae na sak awh pawiteh,
24 Bí ẹ̀ṣẹ̀ bá wáyé láìròtẹ́lẹ̀ láìjẹ́ pé ìjọ ènìyàn mọ̀ sí i, nígbà náà ni kí gbogbo ìjọ ènìyàn mú ọ̀dọ́ akọ màlúù kan wá fún ẹbọ sísun bí òórùn dídùn sí Olúwa, pẹ̀lú ọrẹ ohun jíjẹ àti ọrẹ ohun mímu rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ìlànà, pẹ̀lú akọ ewúrẹ́ fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀.
hot teh tamimaya panuek laipalah ceknoe hoeh hoi yonnae na sak awh pawiteh, tamimaya ni hmaisawi thuengnae, BAWIPA koevah hmuitui hanlah, maitotan kanaw e buet touh a poe vaiteh, tamimaya ni hmaisawi thuengnae, BAWIPA koevah hmuitui hanlah maitotan kanaw e buet touh a poe vaiteh, aphung patetlah tavai thuengnae hoi roum thuengnae hoi yon thueng nahanelah hmaetan buet touh na poe awh han.
25 Àlùfáà yóò sì ṣe ètùtù, fun gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli, a ó sì dáríjì wọ́n, nítorí ẹ̀ṣẹ̀ àìròtẹ́lẹ̀, wọ́n sì ti mú ọrẹ àfinásun wá fún Olúwa nítorí ẹ̀ṣẹ̀ tí wọ́n ṣẹ̀.
Hottelah, vaihma ni, Isarel catoun tamimaya hanlah, yontha nahanlah a sak vaiteh, ngaithoum e lah ao han. Bangkongtetpawiteh, hot teh ceknoe laipalah sakpayon e doeh. BAWIPA koe thuengnae, hmai hoi sak e thuengnae, BAWIPA hmalah yon thuengnae, ceknoe e awm laipalah sakpayonnae hanlah a thokhai awh han.
26 A ó dárí jí gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli àti àwọn àjèjì tí ń gbé ní àárín wọn nítorí pé ní àìròtẹ́lẹ̀ ni wọ́n sẹ ẹ̀ṣẹ̀ náà.
Isarel catoun tamimaya teh, ahnimouh koe kho ka sak e, imyinnaw pueng hai ngaithoum e lah ao han. Bangkongtetpawiteh, taminaw pueng ni ceknoenae awm laipalah a sak awh e doeh.
27 “‘Ṣùgbọ́n bí ó bá jẹ́ pé ẹnìkan ló sẹ̀ ní àìròtẹ́lẹ̀, kí ó mú abo ewúrẹ́ ọlọ́dún kan wá fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀.
Hahoi tami buet touh ni ceknoe laipalah yonnae sak pawiteh, yontha thueng nahanlah hmaela âvâ ka cawt hoeh rae kum touh ka phat e a poe han.
28 Àlùfáà yóò ṣe ètùtù níwájú Olúwa fún ẹni tó ṣẹ̀ láìròtẹ́lẹ̀, tí wọ́n bá ṣe ètùtù fún un, a ó sì dáríjì í.
Hahoi, ama hanlah yon thuengnae sak hanlah BAWIPA hmalah, ceknoe e awm laipalah payonnae koe a sak toteh, vaihma ni ceknoe e awm laipalah payonae ka sak e tami hanlah yontha nahan a sak vaiteh, yontha lah ao han.
29 Òfin kan kí ẹ̀yin kí ó ní fún ẹnikẹ́ni tó bá ṣẹ̀ ní àìmọ̀, àti fún àwọn ẹni tí a bí nínú àwọn ọmọ Israẹli, àti fún àlejò tí ń ṣe àtìpó.
Ceknoe e awm laipalah ka payonkung hanelah Isarel catounnaw thung dawk, amamanaw hoi ahnimouh koe kaawm imyin hanlah hai reikâvan lah kâlawk a tawn awh han.
30 “‘Ṣùgbọ́n bí ẹnikẹ́ni bá mọ̀ ọ́n mọ̀ dẹ́ṣẹ̀ yálà ó jẹ́ ọmọ bíbí ilẹ̀ yín tàbí àlejò, irú ẹni bẹ́ẹ̀ ti kó ẹ̀gàn bá orúkọ Olúwa, a ó sì gé irú ẹni bẹ́ẹ̀ kúrò lára àwọn ènìyàn rẹ̀.
Hatei ceknoe hoi yonnae ka sak e teh, ram thung tami thoseh, imyin thoseh, BAWIPA min mathoe sak e lah ao dawkvah, a miphun dawk hoi takhoe lah ao han.
31 Nítorí pé ẹni náà ti kẹ́gàn ọ̀rọ̀ Olúwa ó sì ti rú òfin rẹ̀, a gbọdọ̀ gé irú ẹni bẹ́ẹ̀ kúrò láàrín àwọn ènìyàn rẹ̀; ẹ̀bi rẹ̀ yóò sì wà lórí rẹ̀.’”
Bangkongtetpawiteh, BAWIPA e lawk a dudam teh kâpoelawk a ek dawkvah, hote tami teh pahnawt roeroe lah ao han. Yonpennae lah a onae phu hah a phu han, tet pouh telah ati.
32 Nígbà tí àwọn ọmọ Israẹli wà nínú aginjù, wọ́n rí ọkùnrin kan tí ń ṣá igi ní ọjọ́ Ìsinmi.
Hottelah Isarel catounnaw kahrawngum ao awh navah, sabbath hnin thing a ei e hmawt pawiteh,
33 Àwọn tó sì rí i níbi tó ti ń ṣá igi wọ́n sì mú un wá sí ọ̀dọ̀ Mose àti Aaroni àti síwájú gbogbo ìjọ ènìyàn,
thing a ei e kahmawtkung ni Mosi hoi Aron tamimaya koe a ceikhai han.
34 wọ́n fi sí ìpamọ́ nítorí pé ohun tí wọn ó ṣe fún un kò tí ì yé wọn.
Ahni hah bangtelamaw ti han tie deipan hoeh rah dawkvah thongim a pabo awh.
35 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Mose pé, “Kíkú ni ọkùnrin náà yóò kú kí gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli sọ ọ́ lókùúta pa ní ẹ̀yìn ibùdó.”
BAWIPA ni Mosi koe hote tami teh thei han roeroe lah ao, rapan alawilah taminaw pueng ni talung hoi dêi roeroe hanlah ao telah atipouh.
36 Wọ́n mú un jáde sí ẹ̀yìn ibùdó, gbogbo ìjọ ènìyàn sì sọ ọ́ lókùúta pa, gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.
BAWIPA ni Mosi koevah, kâ a poe e patetlah taminaw pueng ni rapan hloilah a ceikhai awh teh, talung hoi koung kadout lah a dei awh.
37 Olúwa sọ fún Mose pé,
BAWIPA ni Mosi hah a pato teh,
38 “Bá àwọn ọmọ Israẹli sọ̀rọ̀, kí o sọ fún wọn pé: ‘Títí dé àwọn ìran tó ń bọ̀ ni kí wọn máa ṣe wajawaja sí etí aṣọ wọn, kí wọn sì fi okùn tẹ́ẹ́rẹ́ aláwọ̀ búlúù sí wajawaja kọ̀ọ̀kan.
Isarel catounnaw pato nateh, na catounnaw totouh, khohna pawi koe akana na sak awh vaiteh, kamthim e ralui hoi na na yep awh han.
39 Wajawaja yìí ni ẹ sì máa wọ̀ láti lè mú yín rántí gbogbo òfin Olúwa, kí ẹ bá à lè ṣe wọ́n, kí ẹ sì má bá à ṣe àgbèrè nípa títẹ̀lé ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ọkàn àti ojú yín.
Hote akananaw hah na hmu awh toteh, BAWIPA e kâpoelawknaw pou na panue awh teh na tarawi awh nahan hoi, ahmaloe vah ma ngainae pâlei awh teh, ma lungpouknae lahoi payon awh e patetlah payon laipalah,
40 Nígbà náà ni ẹ ó gbọ́rọ̀ láti pa gbogbo òfin mi mọ́, ẹ ó sì jẹ́ mímọ́ sí Ọlọ́run yín.
kaie kâpoelawknaw pueng na panue awh teh na tarawi awh teh na Cathut hanelah na thoung awh nahan hottelah na sak awh han.
41 Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín tí ó mú yín jáde láti Ejibiti láti jẹ́ Ọlọ́run yín. Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín.’”
Kai teh nangmae Cathut lah ka o nahan, nangmouh hah Izip ram hoi ka tâcawtkhai e nangmae Cathut Jehovah doeh. Kai teh nangmae Cathut Jehovah doeh atipouh.

< Numbers 15 >