< Numbers 15 >
BOEIPA loh Moses te a voek tih,
2 “Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, ‘Nígbà tí ẹ bá dé ilẹ̀ tí èmi ó fún yin gẹ́gẹ́ bí ibùgbé
“'Kai loh nangmih taengah kam paek ham na tolrhum khohmuen la na pawk uh vaengah, Israel ca rhoek te voek lamtah amih te thui pah.
3 tí ẹ̀yin ó bá sì ṣe ẹbọ iná sí Olúwa ẹbọ sísun, tàbí ẹbọ, láti san ẹ̀jẹ́ pàtàkì tàbí ọrẹ àtinúwá, tàbí nínú àjọ yín, láti ṣe òórùn dídùn sí Olúwa nínú agbo ẹran tàbí ọ̀wọ́ ẹran,
BOEIPA taengah hmueihhlutnah hmaihlutnah khaw, olcaeng soep sak ham hmueih khaw, kothoh ham khaw, na khoning ham nawn pah. Saelhung khui lamkah khaw, boiva khui lamkah khaw, BOEIPA taengah hmuehmuei la botui nawn.
4 nígbà náà ni kí ẹni tí ó bá mú ọrẹ rẹ̀ wá, yóò tún mú ẹbọ ohun jíjẹ ìdámẹ́wàá òsùwọ̀n ìyẹ̀fun kíkúnná pẹ̀lú ìdámẹ́rin òsùwọ̀n òróró wá síwájú Olúwa.
BOEIPA taengah amah kah nawnnah aka khuen long tah situi bunang pali neh a thoek khocang vaidam doh te khuen saeh.
5 Pẹ̀lú ọ̀dọ́-àgùntàn kọ̀ọ̀kan yálà fún ọrẹ tàbí ẹbọ sísun ni, kí ẹ pèsè ìdámẹ́rin òsùwọ̀n wáìnì gẹ́gẹ́ bí ohun mímu.
Tuisi la misurtui bunang pali ah hmoel pah. Hmueihhlutnah neh hmueih ham khaw tuca neh rhip saii.
6 “‘Fún àgbò kan ni kí ẹ pèsè ọrẹ ohun jíjẹ ìdá méjì nínú mẹ́wàá òsùwọ̀n ìyẹ̀fun kíkúnná tí a fi ìdákan nínú mẹ́ta òsùwọ̀n òróró pò.
Tutal ham tah situi bunang pathum neh a thoek khocang vaidam doh nit hmoel pah.
7 Àti ìdákan nínú mẹ́ta òsùwọ̀n wáìnì fún ọrẹ ohun mímu gẹ́gẹ́ bí òórùn dídùn sí Olúwa.
Tuisi ham misurtui bunang khoi thum te BOEIPA taengah hmuehmuei botui la nawn.
8 “‘Nígbà tí ẹ bá sì pèsè ọ̀dọ́ akọ màlúù fún ọrẹ tàbí ẹbọ sísun, láti fi san ẹ̀jẹ́ tàbí fún ọrẹ àlàáfíà sí Olúwa,
Hmaihhlutnah saelhung ca khaw, olcaeng aka soep sak ham hmueih khaw, BOEIPA taengah rhoepnah khaw saii.
9 ẹni náà yóò mú ọ̀dọ́ akọ màlúù náà wá pẹ̀lú ọrẹ ohun jíjẹ, ìdámẹ́ta nínú mẹ́wàá òsùwọ̀n ìyẹ̀fun ìyẹ̀fun kíkúnná tí a fi ìdajì òsùwọ̀n òróró pò.
Saelhung ca nen tah situi bunang ngancawn neh a thoek khocang vaidam doh thum te khuen saeh.
10 Kí ó tún mú ìdajì òsùwọ̀n wáìnì wá fún ọrẹ ohun mímu. Yóò jẹ́ ọrẹ àfinásun, àní òórùn dídùn sí Olúwa.
Tuisi ham misurtui bunang ngancawn ah khuen lamtah hmaihlutnah khaw BOEIPA taengah hmuehmuei botui la nawn.
11 Báyìí ni kí ẹ ṣe pèsè ọ̀dọ́ akọ màlúù tàbí àgbò, ọ̀dọ́-àgùntàn tàbí ọmọ ewúrẹ́.
Vaito ham pakhat, tutal ham khaw pakhat neh tu ham khaw tuca khui lamkah khaw maae khui lamkah khaw hmoel saeh.
12 Ẹ ṣe bẹ́ẹ̀ fún ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn, iyekíye tí ẹ̀yin ìbá à pèsè.
Hlangmi tarhing ah na saii te a hlangmi bangla pakhat rhip ham saii tangloeng.
13 “‘Ẹnikẹ́ni tí ó bá jẹ́ ọmọ bíbí ilẹ̀ yín ni kí ó máa ṣe àwọn nǹkan wọ̀nyí nígbà tí ó bá mú ọrẹ àfinásun gẹ́gẹ́ bí òórùn dídùn wá fún Olúwa.
Tolrhum mupoe boeih loh he he saii kuekluek saeh lamtah tah te rhoek te BOEIPA taengkah hmaihlutnah hmuehmuei botui la khuen saeh.
14 Bí àlejò kan bá ń gbé láàrín yín ní gbogbo ìran yín, bí irú ẹni bẹ́ẹ̀ bá fẹ́ mú ọrẹ àfinásun bí òórùn dídùn wá fún Olúwa, gbogbo bí ẹ bá ṣe ń ṣe náà ni kí ó ṣe.
Nangmih taengah aka bakuep yinlai khaw namamih khui kah bangla na cadilcahma ham hmaihlutnah te BOEIPA taengah hmuehmuei botui la nawn saeh lamtah na saii uh bangla saii van saeh.
15 Gbogbo ìjọ ènìyàn gbọdọ̀ ní òfin kan náà fún ọmọ bíbí ilẹ̀ yín àti fún àwọn àlejò tó ń gbé láàrín yín, èyí jẹ́ ìlànà títí láé fún àwọn ìran tó ń bọ̀. Ẹ̀yin àti àlejò tó ń gbé láàrín yín sì jẹ́ bákan náà níwájú Olúwa.
Hlangping kah khosing he nangmih ham neh yinlai aka bakuep ham khaw pakhat la om saeh. Na cadilcahma kah kumhal khosing nen khaw yinlai te BOEIPA mikhmuh ah nangmih bangla om van saeh.
16 Òfin kan àti ìlànà kan ni yóò wà fún yín àti fún àwọn àlejò tí ń gbé láàrín yín.’”
Nangmih ham neh nangmih taengah aka bakuep yinlai ham he olkhueng pakhat neh laitloeknah pakhat mah om saeh,’ ti nah,” a ti nah.
BOEIPA loh Moses te a voek tih,
18 “Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli pé, ‘Nígbà tí ẹ bá dé ilẹ̀ tí mo ń mú yín lọ.
“Israel ca rhoek te voek lamtah amih te, 'Kai loh nangmih kam pawk khohmuen la na pawk uh tih,
19 Tí ẹ sì jẹ oúnjẹ ilẹ̀ náà, ẹ mú nínú rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọrẹ ìgbésókè wá fún Olúwa.
khohmuen kah buh te na caak vaengah BOEIPA taengah khosaa tloeng uh.
20 Ẹ mú àkàrà wá nínú àkọ́so oúnjẹ yín wá gẹ́gẹ́ bí ọrẹ ìgbésókè sí Olúwa, ọrẹ láti inú ilẹ̀ ìpakà yín.
Na buhhuem tanglue vaidam laep te khocang la tloeng uh lamtah cangtilhmuen kah khocang bangla tloeng uh.
21 Nínú àkọ́so oúnjẹ yín ni kí ẹ ti máa mú ọrẹ ìgbésókè yìí fún Olúwa.
Nangmih kah buhhuem tanglue khui lamkah te na cadilcahma due BOEIPA taengah khocang la pae uh.
22 “‘Bí ẹ bá kùnà láìròtẹ́lẹ̀ láti pa àwọn òfin tí Olúwa fún Mose mọ́,
Tedae na palang dongah BOEIPA loh Moses taengah a thui olpaek he boeih na vai uh moenih.
23 èyí ni gbogbo òfin tí Olúwa fún yín láti ẹnu Mose láti ọjọ́ tí Olúwa ti fún yín àti títí dé ìran tó ń bọ̀.
Te boeih te BOEIPA loh Moses kut dongah nangmih te ng'uen. Te khohnin lamkah BOEIPA loh a uen he a voel kah na cadilcahma ham hil pawn ni.
24 Bí ẹ̀ṣẹ̀ bá wáyé láìròtẹ́lẹ̀ láìjẹ́ pé ìjọ ènìyàn mọ̀ sí i, nígbà náà ni kí gbogbo ìjọ ènìyàn mú ọ̀dọ́ akọ màlúù kan wá fún ẹbọ sísun bí òórùn dídùn sí Olúwa, pẹ̀lú ọrẹ ohun jíjẹ àti ọrẹ ohun mímu rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ìlànà, pẹ̀lú akọ ewúrẹ́ fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀.
Rhaengpuei mik lamloh la a saii khaming, te vaengah rhaengpuei pum loh hmueihhlutnah ham saelhung ca vaito pumat neh, a laitloeknah bangla a khocang neh a tuisi khaw, boirhaem la maae ca pumat te, BOEIPA taengah hmuehmuei botui la nawn uh saeh.
25 Àlùfáà yóò sì ṣe ètùtù, fun gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli, a ó sì dáríjì wọ́n, nítorí ẹ̀ṣẹ̀ àìròtẹ́lẹ̀, wọ́n sì ti mú ọrẹ àfinásun wá fún Olúwa nítorí ẹ̀ṣẹ̀ tí wọ́n ṣẹ̀.
Khosoih loh Israel ca rhaengpuei boeih ham a dawth pah daengah ni tohtamaeh dongah khaw amih te khodawk a ngai eh. Te vaengah amih loh amamih kah nawnnah te BOEIPA taengah hmaihlutnah la khuen uh saeh. Amih kah tohtamaeh dongah amamih kah boirhaem te BOEIPA mikhmuh ah tloeng uh saeh.
26 A ó dárí jí gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli àti àwọn àjèjì tí ń gbé ní àárín wọn nítorí pé ní àìròtẹ́lẹ̀ ni wọ́n sẹ ẹ̀ṣẹ̀ náà.
Te daengah ni Israel ca rhaengpuei boeih ham neh amih lakli ah aka bakuep yinlai ham, tohtamaeh khuikah pilnam cungkuem ham khodawk a ngai eh.
27 “‘Ṣùgbọ́n bí ó bá jẹ́ pé ẹnìkan ló sẹ̀ ní àìròtẹ́lẹ̀, kí ó mú abo ewúrẹ́ ọlọ́dún kan wá fún ẹbọ ẹ̀ṣẹ̀.
Hinglu pakhat long he tohtamaeh la a tholh khaming, te vaengah maae la kum khat ca te boirhaem la khuen saeh.
28 Àlùfáà yóò ṣe ètùtù níwájú Olúwa fún ẹni tó ṣẹ̀ láìròtẹ́lẹ̀, tí wọ́n bá ṣe ètùtù fún un, a ó sì dáríjì í.
BOEIPA mik ah tohtamaeh kah hlangtholh la aka taengphael hinglu ham khosoih dawth pah saeh. Anih ham adawth pah daengah ni anih te khodawk a ngai eh.
29 Òfin kan kí ẹ̀yin kí ó ní fún ẹnikẹ́ni tó bá ṣẹ̀ ní àìmọ̀, àti fún àwọn ẹni tí a bí nínú àwọn ọmọ Israẹli, àti fún àlejò tí ń ṣe àtìpó.
Israel ca lamkah mupoe neh a khui kah aka bakuep yinlai ham khaw tohtamaeh la a saii vaengkah olkhueng he nangmih taengah pakhat la om saeh.
30 “‘Ṣùgbọ́n bí ẹnikẹ́ni bá mọ̀ ọ́n mọ̀ dẹ́ṣẹ̀ yálà ó jẹ́ ọmọ bíbí ilẹ̀ yín tàbí àlejò, irú ẹni bẹ́ẹ̀ ti kó ẹ̀gàn bá orúkọ Olúwa, a ó sì gé irú ẹni bẹ́ẹ̀ kúrò lára àwọn ènìyàn rẹ̀.
Tedae kut thueng neh aka saii hinglu tah mupoe khaw, yinlai khaw BOEIPA ni a hliphen. Te dongah tekah hinglu te a pilnam khui lamloh hnawt pah saeh.
31 Nítorí pé ẹni náà ti kẹ́gàn ọ̀rọ̀ Olúwa ó sì ti rú òfin rẹ̀, a gbọdọ̀ gé irú ẹni bẹ́ẹ̀ kúrò láàrín àwọn ènìyàn rẹ̀; ẹ̀bi rẹ̀ yóò sì wà lórí rẹ̀.’”
BOEIPA ol te a sawtsit tih a olpaek te a phae dongah amah sokah amah kathaesainah bangla a hinglu te hnawt rhoe hnawt pah saeh,” a ti nah.
32 Nígbà tí àwọn ọmọ Israẹli wà nínú aginjù, wọ́n rí ọkùnrin kan tí ń ṣá igi ní ọjọ́ Ìsinmi.
Israel ca rhoek te khosoek ah a om uh vaengah Sabbath hnin ah thing aka coi hlang te a hmuh uh.
33 Àwọn tó sì rí i níbi tó ti ń ṣá igi wọ́n sì mú un wá sí ọ̀dọ̀ Mose àti Aaroni àti síwájú gbogbo ìjọ ènìyàn,
Te dongah thing aka coi amah te aka hmu rhoek loh Moses, Aaron taeng neh rhaengpuei boeih taengla a khuen uh.
34 wọ́n fi sí ìpamọ́ nítorí pé ohun tí wọn ó ṣe fún un kò tí ì yé wọn.
Tedae anih taengah metla saii ham khaw a puk pawt dongah thongim khuila a up uh.
35 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Mose pé, “Kíkú ni ọkùnrin náà yóò kú kí gbogbo ìjọ ènìyàn Israẹli sọ ọ́ lókùúta pa ní ẹ̀yìn ibùdó.”
Te vaengah BOEIPA loh Moses taengah, “Tekah hlang te duek rhoe duek saeh, anih te rhaehhmuen vongvoel ah rhaengpuei pum loh lungto neh dae uh saeh,” a ti nah.
36 Wọ́n mú un jáde sí ẹ̀yìn ibùdó, gbogbo ìjọ ènìyàn sì sọ ọ́ lókùúta pa, gẹ́gẹ́ bí Olúwa ti pàṣẹ fún Mose.
Te dongah anih te rhaengpuei pum loh rhaehhmuen vongvoel la a khuen uh tih lungto neh a dae uh dongah BOEIPA loh Moses a uen vanbangla duek.
BOEIPA loh Moses te a voek tih,
38 “Bá àwọn ọmọ Israẹli sọ̀rọ̀, kí o sọ fún wọn pé: ‘Títí dé àwọn ìran tó ń bọ̀ ni kí wọn máa ṣe wajawaja sí etí aṣọ wọn, kí wọn sì fi okùn tẹ́ẹ́rẹ́ aláwọ̀ búlúù sí wajawaja kọ̀ọ̀kan.
“Israel ca rhoek te voek lamtah amih te thui pah. Amih ham maelaw te a cadilcahma due a himbai hmoi ah saii uh saeh lamtah hamnak hmoi kah maelaw dongah a thim khueh uh saeh.
39 Wajawaja yìí ni ẹ sì máa wọ̀ láti lè mú yín rántí gbogbo òfin Olúwa, kí ẹ bá à lè ṣe wọ́n, kí ẹ sì má bá à ṣe àgbèrè nípa títẹ̀lé ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ ọkàn àti ojú yín.
Maelaw la nangmih taengah om vetih te te na hmuh uh daengah ni BOEIPA kah olpaek cungkuem te na poek uh eh. Te te na ngai uh van daengah ni na thinko hnuk neh na mik hnuk te na yaam uh pawt eh. Nangmih tah te rhoi hnukah ni na cukhalh uh.
40 Nígbà náà ni ẹ ó gbọ́rọ̀ láti pa gbogbo òfin mi mọ́, ẹ ó sì jẹ́ mímọ́ sí Ọlọ́run yín.
Kai kah olpaek cungkuem he na poek uh tih na ngai uh daengah ni na Pathen taengah a cim la na om uh eh.
41 Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín tí ó mú yín jáde láti Ejibiti láti jẹ́ Ọlọ́run yín. Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín.’”
Kai tah nangmih kah Pathen la om ham Egypt kho lamloh nangmih aka khuen nangmih kah Pathen Yahweh ni. Kai tah nangmih kah Pathen Yahweh ni,” a ti nah.