< Numbers 11 >

1 Àwọn ènìyàn ń ṣe àròyé nípa wàhálà wọn sí etí ìgbọ́ Olúwa. Ìbínú Olúwa sì ru sókè nígbà tí ó gbọ́ àròyé yìí. Nígbà náà ni iná jáde láti ọ̀dọ̀ Olúwa bọ́ sí àárín wọn, ó sì run àwọn tó wà ní òpin ibùdó.
Tamimaya a phuenang awh toteh, BAWIPA lunghawinae awmhoeh. Bangkongtetpawiteh, hote hah BAWIPA ni a thai toteh, a lungkhuek teh a lungkâan. Hat torei teh BAWIPA e hmai hah ahnimouh rahak vah paluk a to pouh teh, roenae hmuen alawilah, a tangawn koung a kak pouh.
2 Nígbà náà ni àwọn ènìyàn kígbe sí Mose, Mose sì gbàdúrà sí Olúwa iná náà sì kú.
Hahoi teh, tamimaya ni Mosi koe a hram awh teh, Mosi ni BAWIPA koe a ratoum teh, hmai teh bout a roum.
3 Wọ́n sì ń pe ibẹ̀ ní Tabera nítorí pé, iná láti ọ̀dọ̀ Olúwa jó láàrín wọn.
BAWIPA e hmai hah ahnimouh rahak vah paluk a to pouh dawkvah, hote hmuen teh Taberah ati awh.
4 Àwọn ọ̀pọ̀ ènìyàn aláìníláárí tó wà láàrín àwọn ọmọ Israẹli pẹ̀lú ọkàn ìfẹ́kúfẹ̀ẹ́ wọn fi ìtara béèrè fún oúnjẹ mìíràn, àwọn ọmọ Israẹli náà bá bẹ̀rẹ̀ sí í sọkún wí pé, “Bí i pé kí á rí ẹran jẹ báyìí!
Hahoi ahnimouh rahak vah, mak kâkalawt e maya koehoi, takthai ngai awh e hah a tâco. Isarel canaw hai bout a khuika awh teh, apinimaw ca hane moi na poe awh han.
5 Àwa rántí ẹja tí à ń jẹ lọ́fẹ̀ẹ́ ní Ejibiti, apálà, bàrà, ewébẹ̀, àlùbọ́sà àti àwọn ẹ̀fọ́ mìíràn.
Aphu laipalah hoi Izip ram vah tanga moi canae hah ka pahnim thai awh hoeh. Payin paw hoi angkem paw, rasonpaling, rasonpangaw, ankahringnaw hah ka rabuipoung awh toe.
6 Ṣùgbọ́n báyìí gbogbo ara wa ti gbẹ, kò sí ohun mìíràn láti jẹ àfi manna nìkan tí a rí yìí!”
Atuteh ka rakhing koung a ke awh toe, Manna laipalah hoi banghai ka mit ni hmawt awh hoeh toe telah ati awh.
7 Manna náà dàbí èso korianderi, ìrísí rẹ̀ sì dàbí oje igi.
Manna teh songsuen mu patetlah a o, arong teh badellium patetlah ao.
8 Àwọn ènìyàn náà ń lọ káàkiri láti kó o, wọn ó lọ̀ ọ́ lórí ọlọ tàbí kí wọ́n gún un nínú odó. Wọ́n le sè é nínú ìkòkò tàbí kí wọn ó fi ṣe àkàrà, adùn rẹ̀ yóò sì dàbí adùn ohun tí a fi òróró ṣe.
Taminaw ni a racawng awh teh, a roe awhnae koe a phawm awh teh, hlaam dawk a thawng awh, vaiyei lah a sak awh, a ca awh toteh satui hoi karê e patetlah ao.
9 Nígbà tí ìrì bá ẹ̀ sí ibùdó lórí ni manna náà máa ń bọ́ pẹ̀lú rẹ̀.
Tangminlah a roenae rim koe tadamtui a bo toteh manna hai ouk a bo van.
10 Mose sì gbọ́ tí àwọn ènìyàn ń sọkún ní gbogbo ìdílé wọn, oníkálùkù ní ẹnu-ọ̀nà àgọ́ tirẹ̀. Olúwa sì bínú gidigidi. Inú Mose sì bàjẹ́ pẹ̀lú.
Taminaw pueng teh imthung lahoi roenae rim takhang koe a ka awh tie Mosi ni a thai. Hahoi BAWIPA lungphuennae teh puenghoi a kâan teh, Mosi hai a lunghawi hoeh.
11 Mose sì béèrè lọ́wọ́ Olúwa pé, “Kí ló dé tí o fi mú wàhálà yìí bá ìránṣẹ́ rẹ? Kí ni mo ṣe tí n kò fi tẹ ọ lọ́rùn tí ìwọ fi di ẹrù àwọn ènìyàn wọ̀nyí lé mi lórí.
Hot patetlah Mosi ni BAWIPA koe bangkongmaw na san heh runae na poe, bangkongmaw, na mitkhetcawp hoeh e maw, hete maya hnokarinaw heh kai ka van na patue.
12 Èmi ni mo ha lóyún gbogbo àwọn ènìyàn wọ̀nyí bí? Àbí èmi ló bí wọn? Tí ìwọ fi sọ fún mi pé, máa gbé wọn sí oókan àyà rẹ, gẹ́gẹ́ bí abiyamọ ti máa ń gbe ọmọ ọmú lọ sí ilẹ̀ tí o ti búra láti fún àwọn baba ńlá wọn.
Hete taminaw kai ni ka vawn e namaw. A na mintoenaw koe thoebonae ram koe ceikhai hanlah, camo kakhenaw ni sanu ka net lahun a tawm e patetlah na lungtabue dawk tawm awh na ti hanelah ka khe e na ma.
13 Níbo ni n ó ti rí ẹran fún àwọn ènìyàn wọ̀nyí? Nítorí wọ́n ń sọkún sí mi pé, ‘Fún wa lẹ́ran jẹ́!’
Hete taminaw na poe hane moi teh nâhoi maw ka la han. Bangkongtetpawiteh, ka ca hane moi hah na poe telah khuika laihoi na cusin awh toe.
14 Èmi nìkan kò lè dágbé wàhálà àwọn ènìyàn wọ̀nyí, ẹrù wọn ti wúwo jù fún mi.
Hete taminaw pueng hah, kai kamadueng teh ka phawt thai hoeh toe. Kai hanlah a ri poung
15 Bí ó bá sì ṣe pé báyìí ni ìwọ ó ṣe máa ṣe fún mi, kúkú pa mí báyìí, tí mo bá ti bá ojúrere rẹ pàdé—kí ojú mi má ba à rí ìparun mi.”
Het patet e na sak hane pawiteh, na pahren nateh na thei leih, ka rei na thaisak hanh leih telah a ti.
16 Nígbà náà ni Olúwa sọ fún Mose pé, “Mú àádọ́rin ọkùnrin nínú àwọn àgbàgbà àwọn ọmọ Israẹli, àwọn tí o mọ̀ gẹ́gẹ́ bí olórí àti olóyè láàrín àwọn ènìyàn wá sínú àgọ́ ìpàdé, kí wọ́n lé dúró níwájú mi.
BAWIPA ni Mosi koevah, Isarel kacuenaw, maya thung dawk kacuenaw hoi bet a lungkaha lah na panue e naw tami 70 touh pâkhueng nateh, kai koe kamkhuengnae koe lukkareiim dawk nang koe a ka due thai nahan thokhai loe.
17 Èmi ó sì sọ̀kalẹ̀ wá bá yín sọ̀rọ̀ níbẹ̀. Èmi ó sì mú díẹ̀ nínú agbára Ẹ̀mí tí ń bẹ lára rẹ láti fi sí orí àwọn ènìyàn wọ̀nyí. Wọn ó sì máa ràn ọ́ lọ́wọ́ láti ru àjàgà àwọn ènìyàn kí ó má ṣe pé ìwọ nìkan ni ó o máa ru àjàgà náà.
Hattorei haw vah tho vaiteh na pato han. Na tak dawk kaawm e muitha hah ka la vaiteh ahnimouh lathueng ka hruek han. Nang dueng ni phawt laipalah, maya e hmuenri hah ahnimouh ni na phu khai han.
18 “Sọ fún àwọn ènìyàn náà pé, ‘Ẹ ya ara yín sí mímọ́ ní ìmúrasílẹ̀ fún ọ̀la, ẹ ó sì jẹ ẹran. Nítorí pé Olúwa ti gbọ́ igbe ẹkún yín, èyí tí ẹ sun pé, “Ìbá ṣe pé a lè rí ẹran jẹ ni! Ó sàn fún wa ní Ejibiti jù báyìí lọ!” Nítorí náà ni Olúwa yóò fi fún yín ní ẹran, ẹ ó sì jẹ ẹ́.
Nang ni tamimaya koe tangtho hanelah kamthoung awh nateh, moi teh na ca awh han. Moi na ca awh hane apinimaw na poe awh han, bangtelamaw Izip ram vah phu ka nep lah ka o teh telah BAWIPA hnâthainae koe na ka awh vaw. Hatdawkvah, BAWIPA ni moi na poe awh vaiteh na ca awh han.
19 Ẹ kò ní i jẹ ẹ́ fún ọjọ́ kan, ọjọ́ méjì, ọjọ́ márùn-ún, ọjọ́ mẹ́wàá tàbí ogúnjọ́ lásán,
Hnin touh hnin hni touh laipalah, apanga hnin hra touh laipalah, hnin 20 touh laipalah,
20 ṣùgbọ́n fún odidi oṣù kan, títí tí ẹran náà yóò fi máa yọ ní imú yín, tí yóò sì sú yín, nítorí pé ẹ ti kẹ́gàn Olúwa tí ó wà láàrín yín, ẹ sì ti sọkún fún un wí pé, “Kí ló dé tí a fi kúrò ní Ejibiti gan an?”’”
thapa yung touh thung hmawtcei hoi palopalai nunnun a tho toteh, na ca awh han. Bangkongtetpawiteh, nama koe kaawmnaw ni BAWIPA na dudam awh, Bangkongmaw Izip ram hoi kaimanaw na tâcokhai telah a hmalah, na ka awh telah tet pouh ati telah a ati.
21 Ṣùgbọ́n Mose sọ pé, “Mo wà láàrín ọgbọ̀n ọ̀kẹ́ ènìyàn ni ìrìnkiri, ó sì sọ pé, ‘Èmi ó fún wọn ní ẹran láti jẹ fún oṣù kan gbáko!’
Mosi ni kai koe kaawm e khok hoi kacetnaw ting taruk touh a pha teh, thapa yung touh ca hane moi ka poe han telah na ti.
22 Ǹjẹ́ bí a tilẹ̀ pa àgbò ẹran àti ọmọ ẹran, yóò ha tó wọn bí? Tàbí bí a tilẹ̀ pa gbogbo ẹja inú omi fún wọn, yóò wa tó bí?”
Tuhu hoi maitohu naw hai thet pouh haw a boum awh han vaimoe. Talî dawk e tanganaw pueng man pouh nakunghai a boum awh han vaimoe telah a ti.
23 Olúwa sì dá Mose lóhùn pé, “Ọwọ́ Olúwa ha kúrú bí? Ìwọ yóò ri nísinsin yìí bóyá ọ̀rọ̀ tí mo sọ yóò ṣẹ tàbí kò ni í ṣẹ.”
BAWIPA ni Mosi koevah, BAWIPA e kut teh a duem maw. Ka dei e hah nang koe a kuep hoi kuep hoeh e na panue han doeh telah a ti.
24 Mose sì jáde, ó sọ ohun tí Olúwa wí fún àwọn ènìyàn. Ó mú àwọn àádọ́rin àgbàgbà Israẹli dúró yí àgọ́ ká.
Hahoi Mosi a tâco teh, BAWIPA lawk hah taminaw pueng koe a dei pouh. Tamihu kacuenaw 70 touh hah a kaw teh, lukkareiim petkâkalup lah a kangdue sak
25 Nígbà náà ni Olúwa sọ̀kalẹ̀ nínú àwọ̀ sánmọ̀ ó sì bá wọn sọ̀rọ̀, ó sì mú lára Ẹ̀mí tó wà lára Mose sí ara àwọn àádọ́rin àgbàgbà náà, Ó sì ṣẹlẹ̀ pé nígbà tí Ẹ̀mí náà bà lé wọn, wọ́n sọtẹ́lẹ̀, ṣùgbọ́n lẹ́yìn èyí wọn kò sọtẹ́lẹ̀ mọ́.
Hahoi BAWIPA teh tâmai dawk a kum teh a pato. Ahni koe kaawm e muitha hah kacuenaw 70 touh lathueng vah a ta. Ahnimouh tak dawk muitha a pha teh, Lawk a pâpho awh. Hot patetlah ouk sak awh boihoeh ei nan toung mah.
26 Àwọn ọkùnrin méjì, tí orúkọ wọn ń jẹ́ Eldadi àti Medadi kò kúrò nínú àgọ́. Orúkọ wọn wà lára àádọ́rin àgbàgbà yìí ṣùgbọ́n wọn kò jáde nínú àgọ́ síbẹ̀ Ẹ̀mí náà bà lé wọn, wọ́n sì sọtẹ́lẹ̀ nínú àgọ́.
Hatei, roenae hmuen koe tami kahni touh pou ao. Buet touh e a min teh Eldad doeh. Alouk buet touh e min teh Medad doeh, Muitha hah ahnimouh koe ao. Touk e naw dawk ka bawk awh e eiteh, kamkhuengnae lukkareiim koe cet vah hoeh. Roenae hmuen koe lawk hah a pâpho roi.
27 Ọmọkùnrin kan sì sáré lọ sọ fún Mose pé, “Eldadi àti Medadi ń sọtẹ́lẹ̀ nínú àgọ́.”
Hahoi thoundoun buet touh a yawng teh Mosi koe a dei pouh teh, Eldad hoi Medad ni lawk teh pâpho lahun telah atipouh.
28 Joṣua ọmọ Nuni tí í ṣe ìránṣẹ́ Mose, láti kékeré tó jẹ́ ọ̀kan nínú àwọn ọmọkùnrin rẹ̀ dáhùn pé, “Mose olúwa mi, dá wọn lẹ́kun!”
Nun capa Joshua a nawsai lahoi yah. Mosi thaw ka tawk pouh e ni a pathung teh, ka bawipa Mosi ahnimouh hah ngang haw ati pouh.
29 Mose sì wí fún un pé, “Àbí ìwọ ń jowú nítorí mi? Ìbá ti wù mí tó, kí gbogbo àwọn ènìyàn Olúwa jẹ́ wòlíì, kí Olúwa sì fi Ẹ̀mí rẹ̀ sí wọn lára!”
Mosi ni ahni koe, kai na dipma e na ou. BAWIPA ni taminaw pueng heh profet lah koung awm naseh, BAWIPA ni ahnimouh lathueng muitha hah ahnimouh van tat pouh naseh ka tie nahoehmaw.
30 Mose àti àwọn àgbàgbà Israẹli yìí sì padà sínú àgọ́.
Hahoi Mosi teh ama hoi Isarel a lungkahanaw hoi roenae hmuen koe a ban awh.
31 Afẹ́fẹ́ sì jáde láti ọ̀dọ̀ Olúwa ó sì kó àparò wá láti inú Òkun. Ó sì dà wọ́n káàkiri gbogbo ibùdó ní ìwọ̀n gíga ẹsẹ̀ bàtà mẹ́ta sórí ilẹ̀, bí ìwọ̀n ìrìn ọjọ́ kan ní gbogbo àyíká.
Hahoi BAWIPA koehoi kahlî a tho teh, talî koe lahoi tamuem hrut a palek pouh teh roenae rim avangvanglah hoi hnin touh lamcei reira dawk dong hni touh ka rasang lahoi a pabo pouh.
32 Ní gbogbo ọjọ́ náà àti òru, títí dé ọjọ́ kejì ni àwọn ènìyàn fi ń kó àparò yìí, ẹni tó kó kéré jùlọ kó ìwọ̀n homeri mẹ́wàá, wọ́n sì ṣà wọ́n sílẹ̀ fún ara wọn yí gbogbo ibùdó.
Hot patetlah tamimaya ni karum tuettuet kanîruirui a tangtho kanîruirui tamuem teh a racawng awh. Kayounpoung ka racawng e ni hai Homer 10 touh a racawng awh (homer teh ephah hra touh, 220 liters a cawng). Rim pueng koe amamouh hane lengkaleng a vaw awh.
33 Ṣùgbọ́n nígbà tí ẹran náà sì wà láàrín eyín wọn, kó tó di pé wọ́n jẹ ẹ́, ìbínú Olúwa sì ru sí àwọn ènìyàn, ó sì pa wọ́n pẹ̀lú àjàkálẹ̀-ààrùn.
Hatei moi teh a la awh lahun nah, be a ca awh hoehnahlan tamimaya lathueng BAWIPA e lungkhueknae a kâan teh, tamimaya koe takikatho poung e lacik hoi BAWIPA ni a rek awh.
34 Torí èyí ni wọ́n ṣe pe ibẹ̀ ní Kibirotu-Hattaafa nítorí pé níbẹ̀ ni wọ́n gbé sìnkú àwọn ènìyàn tó ní ọ̀kánjúwà oúnjẹ sí.
Hote hmuen teh a min Kiborthhattaavah telah ati. Bangkongtetpawiteh, haw vah, takthaingainae katawnnaw hah a pakawp awh.
35 Àwọn ènìyàn yòókù sì gbéra láti Kibirotu-Hattaafa lọ pa ibùdó sí Haserotu wọ́n sì dúró níbẹ̀.
Kiborthhattaavah koehoi tamihupui teh Hazeroth lah a pâtam awh teh Hazeroth a roe awh.

< Numbers 11 >