< Nehemiah 1 >
1 Ọ̀rọ̀ Nehemiah ọmọ Hakaliah. Ní oṣù Kisleu ní ogún ọdún (ìjọba Ahaswerusi ọba Persia) nígbà tí mo wà ní ààfin Susa,
Историсиря луй Неемия, фиул луй Хакалия. Ын луна Кишлеу, ын ал доуэзечеля ан, пе кынд ерам ын капитала Суса,
2 Hanani, ọ̀kan nínú àwọn arákùnrin mi wá láti Juda pẹ̀lú àwọn ọkùnrin kan, mo sì béèrè lọ́wọ́ wọn nípa àwọn Júù tí ó ṣẹ́kù tí wọn kò kó ní ìgbèkùn, àti nípa Jerusalẹmu.
а венит Ханани, унул дин фраций мей, ши кыцьва оамень дин Иуда. Й-ам ынтребат деспре иудеий скэпаць каре май рэмэсесерэ дин робие ши деспре Иерусалим.
3 Wọ́n sọ fún mi pé, “Àwọn tí ó kù tí a kó ní ìgbèkùn tí wọ́n sì padà sí agbègbè ìjọba wà nínú wàhálà púpọ̀ àti ẹ̀gàn. Odi Jerusalẹmu ti wó lulẹ̀ a sì ti fi iná sun ẹnu ibodè rẹ̀.”
Ей мь-ау рэспунс: „Чей че ау май рэмас дин робие сунт аколо, ын царэ, ын чя май маре ненорочире ши окарэ; зидуриле Иерусалимулуй сунт дэрымате ши порциле сунт арсе де фок.”
4 Nígbà tí mo gbọ́ àwọn nǹkan wọ̀nyí, mo jókòó mo sì sọkún. Mo ṣọ̀fọ̀, mo gbààwẹ̀, mo sì gbàdúrà fún ọjọ́ díẹ̀ níwájú Ọlọ́run ọ̀run.
Кынд ам аузит ачесте лукрурь, ам шезут жос, ам плынс ши м-ам желит мулте зиле. Ам постит ши м-ам ругат ынаинтя Думнезеулуй черурилор
5 Nígbà náà ni mo wí pé: “Olúwa, Ọlọ́run ọ̀run, Ọlọ́run tí ó tóbi tí ó sì ní ẹ̀rù, tí ó ń pa májẹ̀mú ìfẹ́ rẹ̀ mọ́ pẹ̀lú wọn tí ó fẹ́ ẹ tí wọ́n sì ń pa àṣẹ mọ́.
ши ам зис: „Доамне, Думнезеул черурилор, Думнезеуле маре ши ынфрикошат, Ту, каре ций легэмынтул Тэу ши ешть плин де ындураре фацэ де чей че Те юбеск ши пэзеск порунчиле Тале!
6 Jẹ́ kí etí rẹ kí ó ṣí sílẹ̀, kí ojú ù rẹ kí ó sì ṣí sílẹ̀ láti gbọ́ àdúrà tí ìránṣẹ́ rẹ ń gbà ní iwájú rẹ ní ọ̀sán àti ní òru fún àwọn ìránṣẹ́ rẹ, àwọn ènìyàn Israẹli. Mo jẹ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ àwa ọmọ Israẹli àti tèmi àti ti ilé baba mi, tí a ti ṣẹ̀ sí ọ.
Сэ я аминте урекя Та ши окий сэ-Ць фие дескишь: аскултэ ругэчуня пе каре ць-о фаче робул Тэу акум, зи ши ноапте, пентру робий Тэй, копиий луй Исраел, мэртурисинд пэкателе копиилор луй Исраел, пэкателе фэкуте де ной ымпотрива Та, кэч еу ши каса татэлуй меу ам пэкэтуит.
7 Àwa ti ṣe búburú sí ọ. A kò sì pa àṣẹ ìlànà àti òfin tí ìwọ fún Mose ìránṣẹ́ rẹ mọ́.
Те-ам супэрат ши н-ам пэзит порунчиле Тале, леӂиле ши орындуириле пе каре ле-ай дат робулуй Тэу Мойсе.
8 “Rántí ìlànà tí o fún Mose ìránṣẹ́ rẹ, wí pé, ‘Bí ìwọ bá jẹ́ aláìṣòótọ́, èmi yóò fọ́n yín ká sí àárín àwọn orílẹ̀-èdè.
Аду-Ць аминте де кувинтеле ачестя пе каре ле-ай дат робулуй Тэу Мойсе сэ ле спунэ: ‘Кынд вець пэкэтуи, вэ вой рисипи принтре попоаре,
9 Ṣùgbọ́n tí ẹ̀yin bá yípadà sí mi, tí ẹ bá sì pa àṣẹ mi mọ́, nígbà náà bí àwọn ènìyàn yín tí a kó ní ìgbèkùn tilẹ̀ wà ní jìnnà réré ìpẹ̀kun ọ̀run, èmi yóò kó wọn jọ láti ibẹ̀, èmi yóò sì mú wọn wá, sí ibi tí èmi ti yàn bí i ibùgbé fún orúkọ mi.’
дар, дакэ вэ вець ынтоарче ла Мине ши дакэ вець пэзи порунчиле Меле ши ле вець ымплини, атунч, кяр дакэ вець фи изгониць ла марӂиня чя май депэртатэ а черулуй, де аколо вэ вой адуна ши вэ вой адуче ярэшь ын локул пе каре л-ам алес ка сэ локуяскэ Нумеле Меу аколо.’
10 “Àwọn ni ìránṣẹ́ rẹ àti ènìyàn rẹ àwọn tí ìwọ rà padà pẹ̀lú agbára ńlá rẹ àti ọwọ́ agbára ńlá rẹ.
Ей сунт робий Тэй ши попорул Тэу пе каре л-ай рэскумпэрат прин путеря Та чя маре ши прин мына Та чя таре.
11 Olúwa, jẹ́ kí etí rẹ ṣí sílẹ̀ sí àdúrà ìránṣẹ́ rẹ yìí, àti sí àdúrà àwọn ìránṣẹ́ rẹ tí wọ́n ní inú dídùn láti bọ̀wọ̀ fún orúkọ rẹ. Fún ìránṣẹ́ rẹ ní àṣeyọrí lónìí kí o sì síjú àánú wò ó níwájú ọkùnrin yìí.” Nítorí tí mo jẹ́ agbọ́tí ọba nígbà náà.
Ах, Доамне, сэ я аминте урекя Та ла ругэчуня робулуй Тэу ши ла ругэчуня робилор Тэй, каре вор сэ се тямэ де Нумеле Тэу! Дэ астэзь избындэ робулуй Тэу ши фэ-л сэ капете тречере ынаинтя омулуй ачестуя!” Пе атунч ерам пахарникул ымпэратулуй.