< Nehemiah 9 >

1 Ní ọjọ́ kẹrìnlélógún oṣù kan náà, àwọn ọmọ Israẹli péjọpọ̀, wọ́n gbààwẹ̀, wọ́n wọ aṣọ ọ̀fọ̀, wọ́n sì da eruku sórí ara wọn.
Hot patetlah, hate thapa 24 hnin nah Isarelnaw teh rawcahai hoi buri kâkhu teh, vaiphu a kâphuen awh teh kamkhueng awh.
2 Àwọn ọkùnrin Israẹli sì ya ara wọn sọ́tọ̀ kúrò nínú gbogbo àwọn àjèjì. Wọ́n dúró ní ààyè e wọn, wọ́n sì ń jẹ́wọ́ àwọn ẹ̀ṣẹ̀ ẹ wọn àti iṣẹ́ búburú àwọn baba wọn.
Isarelnaw teh ram alouknaw koehoi aloukcalah ao awh teh, a yonnae naw hoi mintoenaw e payonnae hah kangdue laihoi a pâpho awh.
3 Wọ́n dúró sí ibi tí wọ́n wà, wọ́n sì fi ìdámẹ́rin ọjọ́ kà nínú ìwé òfin Olúwa Ọlọ́run wọn, wọ́n sì tún fi ìdámẹ́rin mìíràn ní ìjẹ́wọ́ ẹ̀ṣẹ̀ àti ní sí sin Olúwa Ọlọ́run wọn.
Amamouh onae hmuen koe lengkaleng a kangdue awh teh, hnin touh hah pali touh lah a kapek awh teh, amamae hmuen koe lengkaleng a kangdue awh teh, buet touh dawk BAWIPA Cathut e kâlawk a touk awh. Buet touh dawk, yon a pâpho awh teh, buet touh dawk BAWIPA Cathut hah a bawk awh.
4 Nígbà náà ni Jeṣua, àti Bani, Kadmieli, Ṣebaniah, Bunni, Ṣerebiah, Bani àti Kenaani gòkè dúró lórí àwọn àtẹ̀gùn àwọn ọmọ Lefi, wọ́n sì fi ohùn rara kígbe sí Olúwa Ọlọ́run wọn.
Hot patetlah, Levih taminaw khalai rasang dawk Jeshua, Bani, Kadmiel, Shebaniah, Bunni, Sherebiah, Bani hoi Kenani naw hah a kangdue awh teh, kacaipounglah BAWIPA Cathut hah a kaw awh.
5 Nígbà náà ni àwọn ọmọ Lefi: Jeṣua, Kadmieli, Bani, Haṣbneiah, Ṣerebiah, Hodiah, Ṣebaniah àti Petahiah—wí pé, “Ẹ dìde ẹ fi ìyìn fún Olúwa Ọlọ́run yín, tí ó wà láé àti láéláé.” “Ìbùkún ni fún orúkọ rẹ tí ó ní ògo, kí ó sì di gbígbéga ju gbogbo ìbùkún àti ìyìn lọ.
Hot patetlah, Levih tami, Jeshua hoi Kadmiel, Bani, Hashabneiah, Sherebiah, Hodiah, Shebaniah, hoi Pethahiah naw ni kang dout awh nateh Jehovah Cathut teh a yungyoe hoi a yungyoe pholen awh. Pholennae a Lathueng Poung lah kaawm e, na min lentoenae teh pholennae awm seh telah ati awh.
6 Ìwọ nìkan ni Olúwa. Ìwọ ni ó dá ọ̀run, àní àwọn ọ̀run tí ó ga jù pẹ̀lú gbogbo ogun wọn, ayé àti ohun gbogbo tí ń bẹ nínú rẹ̀, òkun, àti ohun gbogbo tí ń bẹ nínú rẹ̀. Ìwọ sì pa gbogbo wọn mọ́ láàyè, ogun ọ̀run sì ń sìn ọ́.
Hahoi maya ni nang duengdoeh Jehovah lah na kaawm. Nama ni kalvan hah na sak. Kalvannaw e kalvan hoi athung kaawmnaw pueng hoi, talai hoi athung kaawmnaw pueng hoi, talî hoi athung kaawm e pueng hah na sak teh, abuemlah na khetyawt. Nang teh kalvan kaawm pueng ni na bawk awh.
7 “Ìwọ ni Olúwa Ọlọ́run, tí ó yan Abramu tí ó sì mú u jáde láti Uri ti Kaldea, tí ó sì sọ orúkọ rẹ̀ ní Abrahamu.
Nang ni Abraham na rawi teh, Khaldean ram Ur kho hoi na tâcokhai teh, a min lah Abraham telah na ka phung e Jehovah Cathut lah na o.
8 Ìwọ sì rí í pé ọkàn rẹ̀ jẹ́ olóòtítọ́ sí ọ, ìwọ sì dá májẹ̀mú pẹ̀lú u rẹ̀ láti fi ilẹ̀ àwọn ará a Kenaani, Hiti, Amori, Peresi, Jebusi àti Girgaṣi fún irú àwọn ọmọ rẹ̀. Ìwọ ti pa ìpinnu rẹ̀ mọ́ nítorí tí ìwọ jẹ́ olódodo.
A lungthin teh na hmalah yuemkamcu lah na hmu teh, Kanaan tami, Hit tami, Amor tami, Periz tami, Jebusit tami hoi Girgashite taminaw e ram hah, ca catounnaw poe hanelah lawkkam na sak. Na lawk teh na kuep sak. Bangkongtetpawiteh nang teh na lan.
9 “Ìwọ rí ìpọ́njú àwọn baba ńlá wa ní Ejibiti; ìwọ gbọ́ igbe ẹkún wọn ní Òkun Pupa.
Izip ram e mintoenaw rucat khangnae hah na hmu teh, tuipuipaling teng e a hramki awh e lawk hah na thai.
10 Ìwọ rán iṣẹ́ àmì àti iṣẹ́ ìyanu sí Farao, sí gbogbo àwọn ìjòyè rẹ̀ àti sí gbogbo ènìyàn ilẹ̀ ẹ rẹ̀, nítorí ìwọ mọ ìwà ìgbéraga tí àwọn ará Ejibiti hù sí wọn. Ìwọ ra orúkọ fún ara à rẹ, èyí tí ó sì wà títí di òní yìí.
Faro hoi ama koe kaawm e pueng hoi a ram dawk e tami pueng e lathueng vah, mitnoutnae kângairu hah na kamnue sak. Bangkongtetpawiteh, polainae nama dawk ouk a sak awh e hah, nama ni na panue. Hatdawkvah, nama hane na min hah na sak. Sahnin e kaawm e patetlah.
11 Ìwọ pín òkun níwájú wọn, nítorí kí wọn lè kọjá ní ìyàngbẹ ilẹ̀, ṣùgbọ́n ìwọ sọ àwọn tí ń lépa wọn sínú ibú, bí òkúta sínú omi ńlá.
Hahoi ahnimae hmalah tui hah na kapek teh talai kaphui dawk na cei awh. Ahnimouh thoe ka bo e hah kadung e tui thung, athakaawme tui thung vah talung patetlah na tâkhawng.
12 Ní ọ̀sán ìwọ darí i wọn pẹ̀lú ọ̀wọn àwọsánmọ̀ àti ní òru ni ìwọ darí i wọn pẹ̀lú ọ̀wọn iná láti fún wọn ní ìmọ́lẹ̀ ní ọ̀nà tí wọn yóò gbà.
Kanîthun vah tâmaikhom hoi na hrawi teh, karum lah a cei awh nahane lamthung dawk ka tue hanelah hmaikhom hoi a hrawi.
13 “Ìwọ sọ̀kalẹ̀ wá sí orí òkè Sinai; ìwọ bá wọn sọ̀rọ̀ láti ọ̀run. Ìwọ fún wọn ní ìlànà àti àwọn òfin tí ó jẹ́ òdodo tí ó sì tọ́ àti ìlànà tí ó dára.
Sinai mon dawk hoi na kum teh, kalvan hoi ahnimouh koe lawk na dei. Kalan e lawkcengnae, kalan e kâlawk, phunglawknaw hoi kâpoelawk hah na poe.
14 Ìwọ mú ọjọ́ ìsinmi rẹ mímọ́ di mí mọ̀ fún wọn, o sì fún wọn ní àwọn ìlànà, àwọn àṣẹ àti àwọn òfin láti ọwọ́ Mose ìránṣẹ́ rẹ.
Kathounge Sabbath hah na panue sak. Mosi hno lahoi kâ na poe. Phunglawknaw, kâpoelawknaw, hoi kâlawk hah na poe.
15 Ìwọ fún wọn ní oúnjẹ láti ọ̀run wá nígbà tí ebi ń pa wọ́n àti nígbà òǹgbẹ, o fún wọn ní omi láti inú àpáta; o sì sọ fún wọn pé, kí wọ́n lọ láti lọ gba ilẹ̀ náà tí ìwọ ti jẹ́ ẹ̀jẹ́ láti fi fún wọn nípa ìgbọ́wọ́sókè.
Hahoi a vonhlam navah, kalvan hoi vaiyei na poe. Tui kahran awh navah, lungsong dawk hoi tui na tâcosak teh, poe hanelah na noe pouh e ram hah ao awh nahan na poe.
16 “Ṣùgbọ́n àwọn, baba ńlá wa, wọ́n ṣe ìgbéraga, wọ́n sì ṣe agídí, wọn kò sì tẹríba fún àwọn ìlànà rẹ.
Hateiteh ahnimouh hoi mintoenaw ni polainae hoi a lungpata sak awh. Kâpoelawknaw hah tarawi awh hoeh.
17 Wọ́n kọ̀ láti fetísílẹ̀, wọ́n sì kùnà láti rántí iṣẹ́ ìyanu tí ìwọ ṣe ní àárín wọn. Wọ́n ṣe agídí, nínú ìṣọ̀tẹ̀ wọn, wọ́n yan olórí láti padà sí oko ẹrú wọn. Ṣùgbọ́n ìwọ Ọlọ́run tí ó ń dáríjì, olóore-ọ̀fẹ́ àti aláàánú, ó lọ́ra láti bínú, ó sì pọ̀ ní ìfẹ́. Nítorí náà ìwọ kò sì kọ̀ wọ́n sílẹ̀,
Tarawi han ngai awh hoeh. Kângairu hno na sak e naw hai thai han ngai awh hoeh toe. A lung hah a pata sak awh teh, taran a thaw awh teh san lah a onae koe lah ban hane kahrawikung hah a rawi awh. Hatei nang teh ngaithoum hanelah coungkacoe lah kaawm e Cathut, pahrennae lungmanae, hoi ka kawi e, lung kasawe, hawisaknae moi ka tawn e lah na o teh, ahnimouh teh na cettakhai boihoeh.
18 nítòótọ́ nígbà tí wọ́n ṣe ẹgbọrọ màlúù dídá, tí wọ́n sì wí pé, ‘Èyí ni Ọlọ́run rẹ tí ó mú ọ gòkè láti Ejibiti wá; tàbí nígbà tí wọ́n sọ ọ̀rọ̀-òdì tí ó burú jàì’.
Meikaphawk maitoca a sak awh teh, Izip ram hoi ka tâcawtkhai e Cathut teh puenghoi a lungkhuek nahanlah a sak awh nakunghai,
19 “Nítorí àánú ńlá rẹ, ìwọ kò kọ̀ wọ́n sílẹ̀ ní aginjù. Ní ọ̀sán ọ̀wọn ìkùùkuu kò kúrò ní ọ̀dọ̀ wọn láti ṣe amọ̀nà an wọn, tàbí ọ̀wọ́n iná láti tàn sí wọn ní òru ní ọ̀nà tí wọn yóò rìn.
Lungmanae kalenpounge dawk hoi kahrawngum vah na cettakhai boihoeh. Lam ka hrawi hane tâmaikhom ni cettakhai boihoeh. Lam a hmu thai na hanelah karum lah hmaikhom ni cettakhai boihoeh.
20 Ìwọ fi ẹ̀mí rere rẹ fún wọn láti kọ́ wọn. Ìwọ kò dá manna rẹ dúró ní ẹnu wọn, ó sì fún wọn ní omi fún òǹgbẹ.
Ahnimouh ka cangkhai hanelah, kahawi e na Muitha hah na poe teh, mana hoi na kawk teh nei hanelah tui na poe.
21 Fún ogójì ọdún ni ìwọ fi bọ́ wọn ní aginjù; wọn kò ṣe aláìní ohunkóhun, aṣọ wọn kò gbó bẹ́ẹ̀ ni ẹsẹ̀ wọn kò wú.
Kahrawngum kum 40 touh thung na kawk. Banghai voutthoupnae awmhoeh. Hnicu a pawnnae awmhoeh. A khoknaw hai phing hoeh.
22 “Ìwọ fi àwọn ìjọba àti àwọn orílẹ̀-èdè fún wọn, ó sì fi gbogbo ilẹ̀ náà fún wọ́n. Wọ́n sì gba ilẹ̀ ọba Sihoni ará a Heṣboni àti ilẹ̀ Ogu ọba Baṣani.
Hahoi uknaeram hoi miphun hah na poe teh ram buet touh hnukkhu buet touh na rei. Hottelah, Heshbon siangpahrang Sihon ram e, Bashan siangpahrang Og ram hah a la awh.
23 Ìwọ ti mú àwọn ọmọ wọn pọ̀ bí ìràwọ̀ ojú ọ̀run, ó sì mú wọn wá sí ilẹ̀ tí o ti sọ fún àwọn baba wọn pé kí wọn wọ̀, kí wọn sì jogún un rẹ̀.
Ca catounnaw teh kalvan e âsi yit touh na pung sak teh a coe awh hane mintoenaw koe na dei pouh e patetlah, ram dawk na kâenkhai.
24 Àwọn ọkùnrin wọn wọ inú rẹ̀, wọ́n sì gbà ilẹ̀ náà. Ìwọ sì tẹ orí àwọn ará a Kenaani, tí ń gbé inú ilẹ̀ náà ba níwájú wọn; ó fi àwọn ará a Kenaani lé wọn lọ́wọ́ pẹ̀lú àwọn ọba wọn àti àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà kí wọn ṣe wọn bí ó ti wù wọ́n.
Hot patetlah, ca catounnaw ni ram teh a coe awh. Nama ni hote ram dawk kaawm e Kanaan taminaw hah, ahnimae a hmalah na sung sak teh, a ngai patetlah a sak awh hanelah siangpahrangnaw hoi a ram e taminaw hah a kut dawk na poe.
25 Wọ́n gba àwọn ìlú olódi àti ilẹ̀ ọlọ́ràá; wọ́n gba àwọn ilé tí ó kún fún onírúurú gbogbo nǹkan rere, àwọn kànga tí a ti gbẹ́, àwọn ọgbà àjàrà, àwọn ọgbà olifi àti àwọn igi eléso ní ọ̀pọ̀lọpọ̀. Wọ́n jẹ, wọ́n yó, wọ́n sì sanra dáradára; wọ́n sì yọ̀ nínú oore ńlá rẹ.
Ka cak e khopuinaw hoi, kahawipoung e ramnaw hah a la awh teh, hnokahawi phunkuep hoi kakawi e imnaw, tai tangcoung e tuikhunaw hoi misur takha hoi, olive takhanaw hoi thingthaikungnaw a pang awh. Hottelah a ca awh teh, a von a paha awh. A thaw teh na lentoenae, na hawinae dawk a phunep awh.
26 “Ṣùgbọ́n wọ́n ṣe àìgbọ́ràn, wọ́n sì ṣọ̀tẹ̀ sí ọ; wọ́n gbàgbé òfin rẹ. Wọ́n pa àwọn wòlíì rẹ, tí o fi gbà wọn ni ìyànjú pé kí wọn yí padà sí ọ; wọ́n sì se ọ̀rọ̀-òdì tí ó burú jàì.
Hateiteh, ahnimouh teh lawkngai awh hoeh. Na taran awh teh, kâlawk hah amamae hnuklah a ta awh teh, nang koe bout ban hanelah, ka yue e profet hah a thei awh teh, puenghoi a tounkhouk awh.
27 Nítorí náà, ìwọ fi wọ́n lé àwọn ọ̀tá wọn lọ́wọ́, àwọn tí ó ni wọ́n lára. Ṣùgbọ́n nígbà tí a ni wọ́n lára wọ́n kígbe sí ọ. Ìwọ gbọ́ wọn láti ọ̀run wá àti nínú ọ̀pọ̀lọpọ̀ àánú rẹ, ìwọ fún wọn ní olùgbàlà, tí ó gbà wọ́n lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá wọn.
Hatdawkvah, ahnimouh hah amamae taran kut dawk na poe toe. Runae a kâhmo awh teh nang koe a hram awh toteh, kalvan hoi na thai pouh teh, lungmanae hoi na kawi dawkvah, taran kut dawk hoi rungngangkung hah na poe.
28 “Ṣùgbọ́n bí wọ́n bá ti wà nínú ìsinmi, wọn a sì túnṣe búburú lójú rẹ. Nígbà náà ni ìwọ kọ̀ wọ́n sílẹ̀ ṣọ́wọ́ àwọn ọ̀tá kí wọ́n lè jẹ ọba lórí wọn. Nígbà tí wọ́n bá sì tún kígbe sí ọ, ìwọ a gbọ́ láti ọ̀run wá, àti nínú àánú rẹ ni ìwọ gbà láti ìgbà dé ìgbà.
Hatei a kâhat awh toteh, na hmalah vah, hawihoehnae bout a sak awh dawkvah, taran kut dawk bout na poe. Ahnimouh ni bout a tho awh teh, nang koe bout a hram awh toteh, kalvan hoi na thai pouh teh lungmanae hoi na kawi dawkvah, boutbout na rungngang.
29 “Ìwọ kìlọ̀ fún wọn láti padà sínú òfin rẹ, ṣùgbọ́n wọ́n hu ìwà ìgbéraga, wọ́n sì ṣe àìgbọ́ràn si àṣẹ rẹ. Wọ́n ṣẹ̀ sí ìlànà rẹ, nípa èyí tí ènìyàn yóò yè tí wọ́n bá pa wọ́n mọ́. Nínú agídí ọkàn wọ́n kọ ẹ̀yìn sí ọ, wọ́n jẹ́ olórí kunkun wọn kò sì fẹ́ gbọ́.
Nange kampangkhai e bout tarawi hanelah, na yue eiteh, ahnimouh ni ngâi awh laipalah, a kâoup awh. Katarawinaw koe hringnae lah kaawm e kâpoelawknaw hah a taran awh. Katepoung e lahuen hoi, lunglennae hoi tarawi laipalah ao awh.
30 Fún ọ̀pọ̀lọpọ̀ ọdún ni ìwọ fi ní sùúrù pẹ̀lú wọn. Nípa ẹ̀mí rẹ ni ìwọ kìlọ̀ fún wọn nípasẹ̀ àwọn wòlíì. Síbẹ̀ wọn kò fi etí sílẹ̀, nítorí náà ni ìwọ ṣe fi wọ́n lé àwọn aládùúgbò wọn lọ́wọ́.
A kum moikapap ahnimouh na panguep teh, na Muitha lahoi na profetnaw hno lahoi na yue nakunghai, ahnimouh ni ngâi awh hoeh. Hatdawkvah, ram alouknaw e kut dawk na poe toe.
31 Ṣùgbọ́n nínú ọ̀pọ̀ àánú rẹ, ìwọ kò mú òpin bá wọn tàbí kọ̀ wọ́n sílẹ̀, nítorí ìwọ ni Ọlọ́run olóore-ọ̀fẹ́ àti aláàánú.
Hatnavah nang ni pahrenlungmanae hoi kakawi e Cathut lah na o teh, pahrennae a len dawkvah, ahnimouh khoeroe na raphoe hoeh, na pahnawt hoeh.
32 “Ǹjẹ́ nítorí náà, Ọlọ́run wa, Ọlọ́run tí ó tóbi, tí ó lágbára, tí ó sì ní ẹ̀rù, ẹni tí ó pa májẹ̀mú ìfẹ́ mọ́, má ṣe jẹ́ gbogbo ìnira yìí dàbí ohun kékeré ní ojú rẹ—ìnira tí ó ti wá sórí wa, sórí àwọn ọba wa àti àwọn olórí wa, sórí àwọn àlùfáà wa àti àwọn wòlíì, sórí àwọn baba wa àti sórí gbogbo ènìyàn rẹ̀, láti àwọn ọjọ́ àwọn ọba Asiria wá títí di òní.
Hatdawkvah, maimae Cathut, kalen, athakaawme, takikatho e Cathut, pahrennae hoi lawkkam kacakpounge, Assiria siangpahrang uknae koehoi sahnin totouh, kaimae siangpahrang bawi, vaihma, profet, a tami pueng e lathueng ka phat e runae pueng, banglahai noutna hoeh e lah awm hoeh.
33 Ìwọ jẹ́ olódodo nínú ohun gbogbo tí ó ti ṣẹlẹ̀ sí wa; ìwọ sì ti ṣe òtítọ́, nígbà tí a bá ṣe búburú.
Nang ni kaimae lathueng na pha sak e hnonaw teh a kamsoum. Kaimanaw teh, kamsoum hoeh lah hno ka sak awh toe. Nang ni teh yuemkamcu lah na sak.
34 Àwọn ọba wa, àwọn olórí wa, àwọn àlùfáà wa, àti àwọn baba wa kò tẹ̀lé òfin rẹ; wọn kò fetísílẹ̀ sí àṣẹ rẹ tàbí àwọn ìkìlọ̀ tí ìwọ fún wọn.
Maimae siangpahrang hoi ukkungnaw, maimae vaihma hoi mintoenaw ni hai, kâlawk tarawi awh hoeh. Kâpoelawk hoi na panuesaknae, na yuenae thai ngai awh hoeh.
35 Àní nígbà tí wọ́n wà nínú ìjọba wọn, tí wọ́n ń gbádùn oore ńlá tí ìwọ fi fún wọn, ní ilẹ̀ tí ó tóbi tí ó sì lọ́ràá, wọn kò sìn ọ́ tàbí padà kúrò nínú àwọn ọ̀nà búburú wọn.
Ahnimanaw teh na uknaeram thung vah, kakaw poung, kahawipoung na poe e dawk thaw tawk ngai awh hoeh. Kahawi hoeh lah tawknae hai kâhat ngai awh hoeh.
36 “Ṣùgbọ́n wò ó, àwa jẹ́ ẹrú lónìí, àwa jẹ́ ẹrú ní ilẹ̀ tí ìwọ fún àwọn baba ńlá wa, nítorí kí wọn bá máa jẹ èso rẹ̀ àti ìre mìíràn tí ó mú jáde.
Khenhaw! atuvah san lah o awh. Athung e canei katui e hoi hnokahawinaw hah yampa mintoenaw koe na poe e ram dawkvah san lah ka o awh toe.
37 Nítorí àwọn ẹ̀ṣẹ̀ wa, ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìkórè rẹ lọ sí ọ̀dọ̀ àwọn ọba tí ó fi ṣe olórí wa. Wọ́n ń ṣe àkóso lórí wa àti lórí ẹran wa bí ó ti wù wọ́n, àwa sì wà nínú ìpọ́njú ńlá.
Ka yon awh dawkvah, siangpahrangnaw ni kaimouh lathueng vah a bawi awh nahanelah, kaimae takthai hoi hnopainaw e lathueng a ngai awh e patetlah kâ a tawn awh toe. Ka lungreithai awh tangngak toe telah a dei awh.
38 “Nítorí gbogbo èyí, a ń ṣe àdéhùn tí ó fẹsẹ̀múlẹ̀, a sì kọ ọ́ sínú ìwé, àwọn olórí ọmọ Lefi àwọn àlùfáà sì fi èdìdì dì í.”
Hnopainaw dawkvah, kacakpounge lawkkam ka sak awh teh, ka thut awh hnukkhu kacuenaw, vaihmanaw hoi Levih taminaw ni tacik a kin awh.

< Nehemiah 9 >