< Nehemiah 8 >

1 gbogbo àwọn ènìyàn kó ara wọn jọ bí ẹnìkan ní gbangba ìta níwájú ibodè omi. Wọ́n sọ fún Esra akọ̀wé pé kí ó gbé ìwé òfin Mose jáde, èyí tí Olúwa ti pàṣẹ fún Israẹli.
Na rĩrĩ, mweri wa mũgwanja wagĩkinya-rĩ, andũ a Isiraeli magĩkorwo maatũũrĩte thĩinĩ wa matũũra mao. Nao andũ othe makĩũngana marĩ ta mũndũ ũmwe kĩhaaro-inĩ kĩrĩa kĩarĩ mbere ya Kĩhingo kĩa Maaĩ. Nao makĩĩra Ezara ũrĩa mwandĩki-marũa arute Ibuku rĩrĩa rĩa Watho wa Musa ũrĩa Jehova aathĩte andũ a Isiraeli.
2 Ní ọjọ́ kìn-ín-ní oṣù keje ni àlùfáà Esra gbé ìwé òfin jáde ní iwájú ìjọ ènìyàn, èyí tí ó jẹ́ àpapọ̀ ọkùnrin àti obìnrin àti gbogbo àwọn ènìyàn tí wọ́n le è gbọ́ ọ ní àgbọ́yé.
Nĩ ũndũ ũcio, mũthenya wa mbere wa mweri wa mũgwanja, Ezara ũrĩa mũthĩnjĩri-Ngai agĩtwara ibuku rĩu rĩa Watho mbere ya kĩũngano kĩu kĩonganĩte kĩa arũme na andũ-a-nja, na arĩa angĩ othe mangĩahotire gũtaũkĩrwo nĩ ũhoro ũcio.
3 Ó kà á sókè láti òwúrọ̀ títí di ọ̀sán bí ó ti kọjú sí ìta ní iwájú ibodè omi ní ojú u gbogbo ọkùnrin, obìnrin àti àwọn ènìyàn tókù tí òye le è yé tí wọ́n wà níbẹ̀. Gbogbo ènìyàn sì fetísílẹ̀ sí ìwé òfin náà pẹ̀lú ìfarabalẹ̀.
Agĩthoma ibuku rĩu aanĩrĩire kuuma rũciinĩ nginya mĩaraho, angʼetheire kĩhaaro kĩrĩa kĩarĩ mbere ya Kĩhingo kĩa Maaĩ, arĩ mbere ya arũme, na andũ-a-nja, na andũ arĩa angĩ mangĩahotire gũtaũkĩrwo nĩ ũhoro ũcio. Nao andũ othe magĩtega matũ, magĩthikĩrĩria ciugo cia Ibuku rĩa Watho.
4 Akọ̀wé Esra dìde dúró lórí i pẹpẹ ìdúrólé tí a fi igi kàn fún ètò yìí. Ní ẹ̀gbẹ́ rẹ̀ ọ̀tún ni Mattitiah, Ṣema, Anaiah, Uriah, Hilkiah àti Maaseiah gbé dúró sí, ní ẹ̀gbẹ́ òsì rẹ̀ ní Pedaiah, Misaeli, Malkiah, Haṣumu, Haṣabadana, Sekariah àti Meṣullamu dúró sí.
Ezara ũrĩa mwandĩki-marũa aarũgamĩte igũrũ rĩa gĩtara kĩa mbaũ kĩrĩa gĩakĩtwo nĩ ũndũ wa ũndũ ũcio kĩũmbe. Mwena wake wa ũrĩo haarũgamĩte Matithia, na Shema, na Anaia, na Uria, na Hilikia, na Maaseia, naguo mwena wa ũmotho hakarũgama Pedaia, na Mishaeli, na Malikija, na Hashumu, na Hashibadana, na Zekaria, na Meshulamu.
5 Esra ṣí ìwé náà, gbogbo ènìyàn sì le rí í nítorí ó dúró níbi tí ó ga ju gbogbo ènìyàn lọ; bí ó sì ti ṣí ìwé náà, gbogbo ènìyàn dìde dúró.
Ezara akĩhingũra ibuku rĩu. Andũ othe nĩmamuonaga tondũ aarũgamĩte handũ hatũũgĩru. Na rĩrĩa aahingũrire ibuku, andũ othe makĩrũgama na igũrũ.
6 Esra yin Olúwa, Ọlọ́run alágbára; gbogbo ènìyàn gbé ọwọ́ wọn sókè, wọ́n sì wí pé, “Àmín! Àmín!” Nígbà náà ni wọ́n wólẹ̀ wọ́n sì sin Olúwa ní ìdojúbolẹ̀.
Ezara akĩgooca Jehova, Ngai ũrĩa mũnene; nao andũ othe makĩoya moko mao na igũrũ makiuga atĩrĩ, “Ameni! Ameni!” Magĩcooka makĩinamĩrĩra, makĩhooya Jehova maturumithĩtie mothiũ mao thĩ.
7 Àwọn Lefi—Jeṣua, Bani, Ṣerebiah, Jamini, Akkubu, Ṣabbetai, Hodiah, Maaseiah, Kelita, Asariah, Josabadi, Hanani àti Pelaiah—kọ́ wọn ni òfin náà bí àwọn ènìyàn ṣe wà ní ìdúró síbẹ̀.
Nao Alawii, na nĩo Jeshua, na Bani, na Sherebia, na Jamini, na Akubu, na Shabethai, na Hodia, na Maaseia, na Kelita, na Azaria, na Jozabadu, na Hanani, na Pelaia, makĩruta andũ ũhoro wa Watho, andũ acio marũgamĩte o hau.
8 Wọ́n kà láti inú ìwé òfin Ọlọ́run, wọ́n túmọ̀ rẹ̀, wọ́n ṣe àlàyé kí ohun tí wọ́n kà bá à le yé àwọn ènìyàn yékéyéké.
Magĩthoma kuuma Ibuku rĩa Watho wa Ngai, magĩtaũraga na magĩtaaragĩria wega nĩgeetha andũ acio mataũkĩrwo wega nĩ ũhoro ũcio wathomagwo.
9 Nígbà náà ni Nehemiah tí ó jẹ́ baálẹ̀, Esra àlùfáà àti akọ̀wé, àti àwọn Lefi tí wọ́n ń kọ́ àwọn ènìyàn wí fún gbogbo wọn pé, “Ọjọ́ yìí jẹ́ ọjọ́ mímọ́ fún Olúwa Ọlọ́run yín. Ẹ má ṣe ṣọ̀fọ̀ tàbí sọkún,” nítorí gbogbo àwọn ènìyàn ti ń sọkún bí wọ́n ti ń tẹ́tí sí ọ̀rọ̀ inú òfin náà.
Ningĩ Nehemia ũrĩa barũthi wa kũu na Ezara mũthĩnjĩri-Ngai na mwandĩki-marũa hamwe na Alawii arĩa maarutaga andũ, makĩĩra andũ acio othe atĩrĩ, “Mũthenya ũyũ wa ũmũthĩ nĩmwamũrĩre Jehova Ngai wanyu. Mũtigaacakaye kana mũrĩre.” Nĩgũkorwo andũ acio othe nĩmarĩraga maigua ciugo cia Watho ũcio.
10 Nehemiah wí pé, “Ẹ lọ kí ẹ gbádùn oúnjẹ tí ẹ yàn láàyò kí ẹ sì mú ohun dídùn, kí ẹ sì mú díẹ̀ ránṣẹ́ sí àwọn tí kò ní. Ọjọ́ yìí, mímọ́ ni fún Olúwa wa. Ẹ má ṣe banújẹ́, nítorí ayọ̀ Olúwa ni agbára yín.”
Nehemia akĩmeera atĩrĩ, “Thiĩi mũgekenie na irio iria njega, na mũnyue indo irĩ mũrĩo, na indo icio imwe mũhe arĩa matarĩ na kĩndũ mathondekeirwo. Mũthenya wa ũmũthĩ nĩmwamũrĩre Mwathani witũ. Mũtikagĩe na kĩeha, nĩgũkorwo gĩkeno kĩa Jehova nĩkĩo hinya wanyu.”
11 Àwọn ọmọ Lefi mú kí gbogbo ènìyàn dákẹ́ jẹ́, wọ́n wí pé, “Ẹ dákẹ́, nítorí mímọ́ ni ọjọ́ yìí. Ẹ má ṣe banújẹ́.”
Alawii makĩhooreria andũ acio othe, makĩmeeraga atĩrĩ, “Hoorerai tondũ ũyũ nĩ mũthenya mwamũre. Mũtikagĩe na kĩeha.”
12 Nígbà náà ni gbogbo ènìyàn lọ láti jẹ àti láti mu, wọ́n sì fi ìpín oúnjẹ ránṣẹ́, wọ́n sì ṣe àjọyọ̀ pẹ̀lú ayọ̀ ńlá, nítorí báyìí àwọn òfin tí a sọ di mímọ́ fun wọn ti yé wọn.
Ningĩ andũ othe magĩthiĩ makarĩe na makanyue, na makaheane irio imwe, na magakũngũĩre makenete nĩ ũndũ nĩmataũkĩirwo nĩ ciugo iria maarutĩtwo.
13 Ní ọjọ́ kejì oṣù náà, àwọn olórí, gbogbo ìdílé, àti àwọn àlùfáà àti àwọn ọmọ Lefi, péjọ sọ́dọ̀ Esra akọ̀wé, wọ́n fi ara balẹ̀ láti fetí sí àwọn ọ̀rọ̀ òfin.
Mũthenya wa keerĩ wa mweri, atongoria a nyũmba ciothe, marĩ hamwe na athĩnjĩri-Ngai na Alawii, makĩũngana harĩ Ezara ũcio mwandĩki-marũa nĩguo mathikĩrĩrie ciugo cia Watho.
14 Wọ́n ri ní àkọsílẹ̀ nínú ìwé òfin, èyí tí Olúwa ti pa ní àṣẹ nípasẹ̀ Mose, kí àwọn ọmọ Israẹli gbé inú àgọ́ ní àkókò àjọ àgọ́ oṣù keje
Nao magĩkora kwandĩkĩtwo watho-inĩ ũrĩa Jehova aathanĩte na kanua ka Musa, atĩ andũ a Isiraeli maikarage thĩinĩ wa ithũnũ hĩndĩ ya gĩathĩ kĩa mweri wa mũgwanja,
15 àti kí wọn kéde ọ̀rọ̀ yìí, kí wọn sì tàn án kálẹ̀ ní gbogbo ìlú wọn àti ní Jerusalẹmu: “Ẹ jáde lọ sí ìlú olókè, kí ẹ mú àwọn ẹ̀ka inú olifi àti ẹ̀ka igi olifi igbó, àti láti inú maritili, àwọn imọ̀ ọ̀pẹ àti àwọn igi tí ó léwé dáradára wá, láti ṣe àgọ́”—gẹ́gẹ́ bí a ti kọ ọ́.
na atĩ maanagĩrĩre na mahunjagie ũhoro ũyũ matũũra-inĩ mao o na kũu Jerusalemu makiugaga atĩrĩ: “Thiĩi kũu bũrũri ũrĩa ũrĩ irĩma mũrehe honge cia mĩtamaiyũ ya mĩgũnda na ya gĩthaka, na cia mĩhandathi, na cia mĩkĩndũ, o na cia mĩtĩ ya kĩĩruru cia gwaka ithũnũ,” o ta ũrĩa kwandĩkĩtwo.
16 Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ènìyàn jáde lọ, wọ́n sì mú àwọn ẹ̀ka wá, wọ́n sì kọ́ àgọ́ fún ara wọn sí orí òrùlé ara wọn, ní àgbàlá wọn àti ní àgbàlá ilé Ọlọ́run àti ní ìta gbangba lẹ́gbẹ̀ẹ́ ẹnu ibodè omi àti èyí tí ó wà lẹ́gbẹ̀ẹ́ ẹnu ibodè Efraimu.
Nĩ ũndũ ũcio andũ makiumagara, makĩrehe honge, makĩĩakĩra ithũnũ igũrũ rĩa nyũmba ciao o na nja ciao, na nja cia nyũmba ya Ngai, na kĩhaaro-inĩ kĩrĩa kĩarĩ Kĩhingo-inĩ kĩa Maaĩ, na kĩrĩa kĩarĩ Kĩhingo-inĩ kĩa Efiraimu.
17 Gbogbo ìjọ ènìyàn tí wọ́n padà láti ìgbèkùn kọ́ àgọ́, wọ́n sì ń gbé inú wọn. Láti ọjọ́ Jeṣua ọmọ Nuni títí di ọjọ́ náà, àwọn ọmọ Israẹli kò tí ì ṣe àjọyọ̀ ọ rẹ̀ bí irú èyí. Ayọ̀ ọ wọn sì pọ̀.
Andũ arĩa othe maacookete kuuma kũrĩa maatwarĩtwo maatahwo makĩĩakĩra ithũnũ, magĩikara thĩinĩ wacio. Kuuma matukũ ma Joshua mũrũ wa Nuni nginya mũthenya ũcio, andũ a Isiraeli matiakoretwo makũngũĩire gĩathĩ kĩu ta ũguo. Nakĩo gĩkeno kĩao kĩarĩ kĩnene mũno.
18 Esra kà nínú ìwé òfin Ọlọ́run, bí ọjọ́ ṣe ń gorí ọjọ́, láti ọjọ́ kìn-ín-ní dé ọjọ́ ìkẹyìn. Wọ́n ṣe àjọyọ̀ àjọ náà fún ọjọ́ méje, ní ọjọ́ kẹjọ wọ́n ní àpéjọ, ní ìbámu pẹ̀lú òfin.
Mũthenya o mũthenya, kuuma mũthenya wa mbere nginya wa mũthia, Ezara nĩathomaga Ibuku rĩa Watho wa Ngai. Nao nĩmakũngũĩire gĩathĩ kĩu mĩthenya mũgwanja, na mũthenya wa kanana, kũringana na watho, gũkĩgĩa na kĩũngano.

< Nehemiah 8 >